< 2 Chronicles 33 >

1 Manase jẹ́ ọmọ ọdún méjìlá nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún márùndínlọ́gọ́ta.
Manase aarĩ wa mĩaka ikũmi na ĩĩrĩ rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ Jerusalemu mĩaka mĩrongo ĩtano na ĩtano.
2 Ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa. Nípa títẹ̀lé ọ̀nà iṣẹ́ ìríra ti àwọn orílẹ̀-èdè tí Olúwa ti lé jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli rìn.
Nake agĩĩka maũndũ marĩa mataagĩrĩire maitho-inĩ ma Jehova na ũndũ wa kũrũmĩrĩra maũndũ maarĩ magigi marĩa meekagwo nĩ ndũrĩrĩ iria Jehova aaingatĩte ciehere mbere ya andũ a Isiraeli.
3 Ó tún kọ́ àwọn ibi gíga tí baba rẹ̀ Hesekiah ti fọ́ túútúú. Ó sì gbé àwọn pẹpẹ dìde fún àwọn Baali ó sì ṣe àwọn ère Aṣerah. Ó foríbalẹ̀ fún gbogbo àwọn ogun ọ̀run ó sì sìn wọ́n.
Agĩaka rĩngĩ kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru kũrĩa ithe Hezekia aamomorete; ningĩ agĩakĩra Baali igongona na agĩthondeka itugĩ cia Ashera. Ningĩ akĩinamĩrĩra na akĩhooya mĩhianano yothe ya mbũtũ cia njata cia igũrũ na agĩcitungatĩra.
4 Ó kọ́ àwọn pẹpẹ sínú ilé Olúwa ní èyí tí Olúwa ti wí pé, “Orúkọ mi yóò wà ní Jerusalẹmu títí láé.”
Manase nĩaakire igongona thĩinĩ wa hekarũ ya Jehova, o ĩrĩa Jehova oigĩte ũhoro wayo atĩrĩ, “Rĩĩtwa rĩakwa rĩgaatũũra Jerusalemu nginya tene.”
5 Nínú ààfin méjèèje ti ilé Olúwa, ó kọ́ àwọn pẹpẹ fún gbogbo àwọn ogun ọ̀run
Nĩakĩire mĩhianano yothe ya mbũtũ cia njata cia igũrũ igongona kũu nja cierĩ cia hekarũ ya Jehova.
6 Ó sì mú kí àwọn ọmọ ara rẹ̀ kí ó kọjá láàrín iná ní àfonífojì Beni-Hinnomu, ó ń ṣe àkíyèsí àfọ̀ṣẹ, ó sì ń lo àlúpàyídà, ó sì ń bá àwọn òku àti oṣó lò. Ó ṣe ọ̀pọ̀ ohun búburú ní ojú Olúwa láti mú un bínú.
Nĩaarutire ariũ ake matuĩke igongona, magĩcinĩrwo Gĩtuamba-inĩ kĩa Beni-Hinomu, na nĩaragũraga na agatuĩria nyoni, na akarogana, na agathiiaga kũrĩ andũ arĩa maarĩ na maroho ma kũragũra, o na agatuĩria ũhoro kuuma kũrĩ maroho mooru. Nĩekire maũndũ maingĩ mooru maitho-inĩ ma Jehova, akĩmũrakaria.
7 Ó mú ère gbígbẹ́ tí ó ti gbẹ́ ó sì gbé e sínú ilé Olúwa, ní èyí tí Ọlọ́run ti sọ fún Dafidi àti sí ọmọ rẹ̀ Solomoni, “Nínú ilé Olúwa yìí àti ní Jerusalẹmu, tí mo ti yàn kúrò nínú gbogbo àwọn ẹ̀yà Israẹli, èmi yóò fi orúkọ mi síbẹ̀ títí láé.
Nĩooire mũhianano mũicũhie ũrĩa aathondekete na akĩũiga thĩinĩ wa hekarũ ya Ngai, ĩrĩa Ngai eerĩte Daudi na mũriũ Solomoni ũhoro wayo atĩrĩ, “Thĩinĩ wa hekarũ ĩno na thĩinĩ wa Jerusalemu, o kũrĩa ndĩthuurĩire kuuma mĩhĩrĩga-inĩ yothe ya Isiraeli, nĩkuo ngũtũũria Rĩĩtwa rĩakwa nginya tene.
8 Èmi kì yóò ṣí ẹsẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli kúrò mọ́ ní ilẹ̀ náà tí èmi ti yàn fún àwọn baba ńlá yín, níwọ̀n bí wọ́n bá ṣe pẹ̀lẹ́ láti ṣe gbogbo ohun tí mo paláṣẹ fún wọn, gẹ́gẹ́ bí gbogbo òfin, àṣẹ àti àwọn ìlànà tí a fún yín láti ọwọ́ Mose wá.”
Ndigatũma magũrũ ma andũ a Isiraeli macooke kũũrũũra moime bũrũri ũyũ ndaheire maithe manyu ma tene, korwo no metĩkĩre kũmenyerera maũndũ mothe marĩa ndĩmaathĩte makonainie na mawatho mothe na kĩrĩra gĩakwa gĩa kũrũmĩrĩrwo na matuĩro marĩa maaheirwo na kanua ka Musa ma kũrũmĩrĩrwo.”
9 Ṣùgbọ́n Manase mú kí Juda àti àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu yapa, àti láti ṣe búburú ju àwọn orílẹ̀-èdè lọ, àwọn tí Olúwa ti parun níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
No rĩrĩ, Manase akĩhĩtithia andũ a Juda na andũ a Jerusalemu, nginya magĩĩka maũndũ mooru o na gũkĩra ndũrĩrĩ iria Jehova aaniinĩte ciehere mbere ya andũ a Isiraeli.
10 Olúwa bá Manase sọ̀rọ̀ àti àwọn ènìyàn rẹ̀, ṣùgbọ́n wọn kò kọbi ara sí i.
Jehova akĩarĩria Manase na andũ ake, no matiigana kũmũigua.
11 Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa mú àwọn alákòóso ọmọ-ogun ọba Asiria láti dojúkọ wọ́n, tí ó mú Manase nígbèkùn, ó fi ìwọ̀ mú un ní imú rẹ̀, ó dè é pẹ̀lú ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ idẹ ó sì mú un lọ sí Babeli.
Nĩ ũndũ ũcio Ngai akĩmarehithĩria anene a mbũtũ cia ita cia mũthamaki wa Ashuri, nao makĩnyiita Manase, makĩmwĩkĩra kĩbini iniũrũ, makĩmuoha na mĩnyororo ya gĩcango, na makĩmũtwara Babuloni.
12 Nínú ìpọ́njú rẹ̀, ó wá ojúrere Olúwa Ọlọ́run rẹ̀. Ó sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ gidigidi níwájú Ọlọ́run àwọn baba rẹ̀.
Hĩndĩ ĩyo aarĩ mũhinyĩrĩrĩku ngoro-rĩ, akĩrongooria ũtugi wa Jehova Ngai wake, na akĩĩnyiihia mũno mbere ya Ngai wa maithe mao.
13 Nígbà tí ó sì gbàdúrà sí i, inú Olúwa dùn sí àdúrà rẹ̀, ó sì tẹ́tí sí ẹ̀bẹ̀ rẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni ó mú un padà wá sí Jerusalẹmu àti sí ìjọba rẹ̀. Nígbà náà Manase mọ̀ wí pé Olúwa ni Ọlọ́run.
Na rĩrĩa aamũhooire, Jehova akĩigua ihooya rĩake na akĩigua gũthaithana gwake; nĩ ũndũ ũcio, akĩmũcookia Jerusalemu na akĩmũcookeria ũthamaki wake. Hĩndĩ ĩyo Manase akĩmenya atĩ Jehova nĩwe Ngai.
14 Ǹjẹ́ lẹ́yìn èyí, ó mọ odi kan lẹ́yìn ìlú Dafidi, ní ìhà ìwọ̀-oòrùn Gihoni, ní àfonífojì, àní ní àtiwọ ẹnu ibodè ẹja, ó sì yí orí òkè Ofeli ká; ó sì mọ ọ́n ga sókè gidigidi, ó sì fi balógun sínú gbogbo ìlú olódi Juda wọ̀n-ọn-nì.
Thuutha-inĩ-rĩ, agĩaka rĩngĩ rũthingo rwa nja rwa Itũũra Inene rĩa Daudi mwena wa ithũĩro wa gĩthima kĩa Gihoni kũu gĩtuamba-inĩ, o nginya itoonyero-inĩ rĩa Kĩhingo gĩa Thamaki, na gũthiũrũrũkĩria karĩma ka Ofeli; o na ningĩ akĩrũraihia na igũrũ. Nĩaigire anene a thigari matũũra-inĩ mothe ma Juda marĩa maarĩ mairigĩre na thingo cia hinya.
15 Ó pa gbogbo àwọn Ọlọ́run àjèjì run. Ó sì hú gbogbo àwọn ère kúrò nínú ilé Olúwa, pẹ̀lú gbogbo àwọn pẹpẹ tí ó ti kọ́ ní òkè ilé Olúwa àti ní Jerusalẹmu; ó sì kó wọn jáde kúrò nínú ìlú.
Akĩeheria ngai cia kũngĩ, o na akĩeheria mũhianano ũrĩa warĩ thĩinĩ wa hekarũ ya Jehova, o na igongona ciothe iria aakĩte karĩma-inĩ ka hekarũ na kũu Jerusalemu, na agĩcite na kũu nja ya itũũra inene.
16 Nígbà náà ni ó mú àwọn pẹpẹ padà bọ̀ sípò. Ó sì rú ọrẹ ìdàpọ̀ àti ọrẹ-ọpẹ́ lórí rẹ̀. Ó sì sọ fún Juda láti sin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
Ningĩ agĩcookereria kĩgongona kĩa Jehova, na akĩrutĩra igũrũ rĩakĩo maruta ma ũiguano na ma gũcookia ngaatho, na akĩĩra andũ a Juda matungatĩre Jehova Ngai wa Isiraeli.
17 Àwọn ènìyàn, ko tẹ̀síwájú láti máa rú ẹbọ ní àwọn ibi gíga. Ṣùgbọ́n sí Olúwa Ọlọ́run wọn nìkan.
No rĩrĩ, andũ magĩthiĩ o na mbere kũrutĩra magongona kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru, no mamarutagĩra Jehova Ngai wao o we wiki.
18 Àwọn iṣẹ́ yòókù ti ìjọba Manase pẹ̀lú àdúrà rẹ̀ sí Ọlọ́run rẹ̀ àti àwọn ọ̀rọ̀ tí àwọn aríran sọ sí i ní orúkọ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, wà nínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli.
Maũndũ marĩa mangĩ makoniĩ wathani wa Manase, o hamwe na ũrĩa aahooire Ngai wake, o na ciugo iria ooni-maũndũ maamwarĩirie thĩinĩ wa rĩĩtwa rĩa Jehova, Ngai wa Isiraeli-rĩ, nĩmandĩke maandĩko-inĩ ma mahinda ma athamaki a Isiraeli.
19 Àdúrà rẹ̀ àti bí inú Ọlọ́run ṣe dùn sí àdúrà rẹ̀ àti gbogbo àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ àti àìṣòótọ́, àti àwọn òpó níbi tí ó kọ́ àwọn ibi gíga sí, ó sì gbé àwọn ère Aṣerah àti àwọn òrìṣà kí ó tó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, gbogbo rẹ̀ ni a kọ sínú ìwé ìrántí àwọn aríran.
Ihooya rĩake, na ũrĩa Ngai aahutirio nĩ gũthaithana gwake, o na ningĩ mehia make mothe, na kwaga kwĩhokeka gwake, o na kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru kũrĩa aakire mahooero ma Baali, na akĩhaanda itugĩ cia Ashera na mĩhianano mbere ya atanenyiihĩria Jehova-rĩ, mothe nĩmandĩkĩtwo maandĩko-inĩ ma andũ arĩa ooni-maũndũ.
20 Manase sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín sínú ààfin rẹ̀. Amoni ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Manase akĩhurũka hamwe na maithe make na agĩthikwo nyũmba-inĩ yake ya ũthamaki. Nake mũriũ Amoni agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake.
21 Amoni jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún méjì.
Amoni aarĩ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na ĩĩrĩ rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ Jerusalemu mĩaka ĩĩrĩ.
22 Ó ṣe búburú ní ojú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí baba rẹ̀ Manase ti ṣe. Amoni rú ẹbọ sí gbogbo àwọn òrìṣà tí Manase baba rẹ̀ ti ṣe, ó sì sìn wọ́n.
Nake agĩĩka maũndũ mooru maitho-inĩ ma Jehova, o ta ũrĩa ithe Manase eekĩte. Amoni nĩahooire na akĩrutĩra mĩhianano yothe magongona ĩrĩa Manase aathondekithĩtie.
23 Ṣùgbọ́n kì í ṣe bí i baba rẹ̀ Manase. Kò rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú Olúwa: ṣùgbọ́n ẹ̀ṣẹ̀ Amoni sì ń pọ̀ sì í.
Nowe ndeekire ta ithe Manase tondũ ndaigana kwĩnyiihĩria Jehova; Amoni nĩaingĩhirie mahĩtia make.
24 Àwọn oníṣẹ́ Amoni dìtẹ̀ sí i. Wọ́n sì pa á ní ààfin rẹ̀.
Anene a Amoni makĩmũciirĩrĩra, na makĩmũũragĩra o kũu nyũmba-inĩ yake ya ũthamaki.
25 Nígbà náà, gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà pa gbogbo àwọn tí wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí ọba Amoni, wọ́n sì mú Josiah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Hĩndĩ ĩyo andũ a bũrũri ũcio makĩũraga andũ arĩa othe maaciirĩire kũũraga Mũthamaki Amoni; nao magĩtua mũriũ Josia mũthamaki ithenya rĩake.

< 2 Chronicles 33 >