< 2 Chronicles 33 >
1 Manase jẹ́ ọmọ ọdún méjìlá nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún márùndínlọ́gọ́ta.
Ma: na: se da lalelegele, ode fagoyale esalu, ea Yuda ouligisu bai muni hamoi. E da Yelusaleme moilaiga esala, Yuda fi ode 55 agoanega ouligilalu.
2 Ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa. Nípa títẹ̀lé ọ̀nà iṣẹ́ ìríra ti àwọn orílẹ̀-èdè tí Olúwa ti lé jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli rìn.
Ma: na: se da Hina Godema wadela: le hamoi. Ga: ina: ne sogega musa: esalebe fi da baligili gogosiasu wadela: i hou hamobeba: le, Isala: ili dunu da Ga: ina: ne soge golili sa: ili, gusuba: i ahoanoba, Hina Gode da Ga: ina: ne fi gadili sefasi. Be Ma: na: se da amo fi ilia wadela: idafa hou amoma fa: no bobogesu.
3 Ó tún kọ́ àwọn ibi gíga tí baba rẹ̀ Hesekiah ti fọ́ túútúú. Ó sì gbé àwọn pẹpẹ dìde fún àwọn Baali ó sì ṣe àwọn ère Aṣerah. Ó foríbalẹ̀ fún gbogbo àwọn ogun ọ̀run ó sì sìn wọ́n.
E da ogogosu ‘gode’ma nodone sia: ne gadosu sogebi, amo ea ada Hesigaia da wadela: lesi, Ma: na: se da bu buga: le gagui. E da Ba: ilema nodone sia: ne gadomusa: , oloda bagohame gagui. E da Isala: ili hina bagade A: iha: be ea hou defele, ogogosu uda ‘gode’ Asila e agoaila hahamoi. Amola Ma: na: se da gasumunima nodone sia: ne gadoi.
4 Ó kọ́ àwọn pẹpẹ sínú ilé Olúwa ní èyí tí Olúwa ti wí pé, “Orúkọ mi yóò wà ní Jerusalẹmu títí láé.”
E da ogogosu ‘gode’ ilia oloda Debolo Diasu ganodini gagui. Hina Gode Ea musa: hamoma: ne sia: i, amo da Debolo Diasu ganodini, dunu da Ema fawane nodone sia: ne gadosu hamoma: ne sia: i.
5 Nínú ààfin méjèèje ti ilé Olúwa, ó kọ́ àwọn pẹpẹ fún gbogbo àwọn ogun ọ̀run
Debolo Diasu gagoi aduna ganodini, e da oloda amo gasumunima nodone sia: ne gadomusa: gagui.
6 Ó sì mú kí àwọn ọmọ ara rẹ̀ kí ó kọjá láàrín iná ní àfonífojì Beni-Hinnomu, ó ń ṣe àkíyèsí àfọ̀ṣẹ, ó sì ń lo àlúpàyídà, ó sì ń bá àwọn òku àti oṣó lò. Ó ṣe ọ̀pọ̀ ohun búburú ní ojú Olúwa láti mú un bínú.
E da Hinome Fago ganodini, egefelali amo ogogosu ‘gode’ma gobele sali. E da wadela: i ba: la: lusu hou hamosu. E da wamuni dawa: su hou hamosu amola gesami dasu ilia fada: i sia: nabalusu. E da Hina Godema bagadewane wadela: le hamobeba: le, Hina Gode Ea ougi da lalu agoane heda: i.
7 Ó mú ère gbígbẹ́ tí ó ti gbẹ́ ó sì gbé e sínú ilé Olúwa, ní èyí tí Ọlọ́run ti sọ fún Dafidi àti sí ọmọ rẹ̀ Solomoni, “Nínú ilé Olúwa yìí àti ní Jerusalẹmu, tí mo ti yàn kúrò nínú gbogbo àwọn ẹ̀yà Israẹli, èmi yóò fi orúkọ mi síbẹ̀ títí láé.
E da wadela: i uda ‘gode’ Asila agoai loboga hamoi liligi, amo Debolo Diasu ganodini ligisi. Be Hina Gode da musa: Da: ibidi amola, Da: ibidi ea mano Soloumane elama amane sia: i, “Guiguda: Yelusaleme moilai bai bagade ganodini, Na da amo Debolo ganodini sogebi ilegei. Amo sogebiga fawane, Isala: ili fi fagoyale gala da Nama fawane nodone sia: ne gadoma: ne, Na da ilegei.
8 Èmi kì yóò ṣí ẹsẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli kúrò mọ́ ní ilẹ̀ náà tí èmi ti yàn fún àwọn baba ńlá yín, níwọ̀n bí wọ́n bá ṣe pẹ̀lẹ́ láti ṣe gbogbo ohun tí mo paláṣẹ fún wọn, gẹ́gẹ́ bí gbogbo òfin, àṣẹ àti àwọn ìlànà tí a fún yín láti ọwọ́ Mose wá.”
Isala: ili fi dunu da Na hamoma: ne sia: i huluane nabawane hamosea, amola sema amo Na da Na hamosu dunu Mousesegili i, amo huluane ilia nabawane hamosea, Na da ili, amo soge Na da ilia aowalalima i, amoga ili enoga gadili sefasima: ne, logo hamedafa doasimu.”
9 Ṣùgbọ́n Manase mú kí Juda àti àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu yapa, àti láti ṣe búburú ju àwọn orílẹ̀-èdè lọ, àwọn tí Olúwa ti parun níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
Be Yuda fi dunu da Hina Gode Ea sia: nabawane hame hamosu. Amola Ma: na: se da ilia wadela: i hou (amo da musa: Ga: ina: ne fi da bagadewane wadela: le hamobeba: le, Isala: ili dunu da gusuba: i heda: loba, Hina Gode da Ga: ina: ne fi gadili sefasi) amo wadela: i hou baligili hamoma: ne, Ma: na: se da Yuda fi oule asi.
10 Olúwa bá Manase sọ̀rọ̀ àti àwọn ènìyàn rẹ̀, ṣùgbọ́n wọn kò kọbi ara sí i.
Hina Gode da Ma: na: se amola ea fi dunuma sisasu sia: i. Be ilia nabimu higa: i.
11 Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa mú àwọn alákòóso ọmọ-ogun ọba Asiria láti dojúkọ wọ́n, tí ó mú Manase nígbèkùn, ó fi ìwọ̀ mú un ní imú rẹ̀, ó dè é pẹ̀lú ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ idẹ ó sì mú un lọ sí Babeli.
Amaiba: le, Hina Gode da logo doasiba: le, Asilia dadi gagui wa: i da Yuda fi doagala: i. Ilia da Ma: na: se gagulaligili, ea mi gelaba ma: go sanawane, sia: inega la: gili, Ba: bilone sogega hiouginana asi.
12 Nínú ìpọ́njú rẹ̀, ó wá ojúrere Olúwa Ọlọ́run rẹ̀. Ó sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ gidigidi níwájú Ọlọ́run àwọn baba rẹ̀.
E se bagadewane nababeba: le, ea hou fonoboi. E da ea Hina Godema sinidigili, fidima: ne adole ba: su.
13 Nígbà tí ó sì gbàdúrà sí i, inú Olúwa dùn sí àdúrà rẹ̀, ó sì tẹ́tí sí ẹ̀bẹ̀ rẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni ó mú un padà wá sí Jerusalẹmu àti sí ìjọba rẹ̀. Nígbà náà Manase mọ̀ wí pé Olúwa ni Ọlọ́run.
Gode da Ma: na: se ea sia: ne gadobe nabalu, e Yuda fi bu ouligima: ne, bu Yelusalemega asunasi. Amo hou ba: beba: le, Ma: na: se da Hina Gode da Godedafa dafawaneyale dawa: i.
14 Ǹjẹ́ lẹ́yìn èyí, ó mọ odi kan lẹ́yìn ìlú Dafidi, ní ìhà ìwọ̀-oòrùn Gihoni, ní àfonífojì, àní ní àtiwọ ẹnu ibodè ẹja, ó sì yí orí òkè Ofeli ká; ó sì mọ ọ́n ga sókè gidigidi, ó sì fi balógun sínú gbogbo ìlú olódi Juda wọ̀n-ọn-nì.
Amalu fa: no, Ma: na: se da gadili dobea Da: ibidi Moilai bai bagadega gusudili dialu amo da fago Gihone Gu Hano gadenene dialu, amoga asili, Menabo Logo Ga: su amola moilai sogebi ea dio Oufele, amoga doaga: su, bu sedagili gagagula heda: i. Amola e da dadi gagui ouligisu dunu, amo da Yuda soge gagili sali moilai bai bagade afae afae ouligima: ne, ilegei dagoi.
15 Ó pa gbogbo àwọn Ọlọ́run àjèjì run. Ó sì hú gbogbo àwọn ère kúrò nínú ilé Olúwa, pẹ̀lú gbogbo àwọn pẹpẹ tí ó ti kọ́ ní òkè ilé Olúwa àti ní Jerusalẹmu; ó sì kó wọn jáde kúrò nínú ìlú.
E da ga fi ogogosu ‘gode’ amola loboga hamoi ‘gode’ agoaila liligi amo e da musa: ligisi, amo Debolo Diasuga gadili fadegai. Amo amola ogogosu ‘gode’ma gobele salimusa: oloda amo da Debolo Diasu agolo dabua amola Yelusaleme sogebi enoga dialebe ba: i, amo huluane moilai hamega gadili gaguli asili, ha: digi dagoi.
16 Nígbà náà ni ó mú àwọn pẹpẹ padà bọ̀ sípò. Ó sì rú ọrẹ ìdàpọ̀ àti ọrẹ-ọpẹ́ lórí rẹ̀. Ó sì sọ fún Juda láti sin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
Amola e da oloda amoga ilia musa: Hina Godema nodone sia: ne gadosu, amo bu dodoa: i. Amola e da amoga Hahawane Gilisili Olofole Iasu amola Godema Nodosu Iasu, amo gobele sali. E da Yuda fi dunu huluane, ilia Isala: ili Hina Godema nodone sia: ne gadoma: ne sia: i.
17 Àwọn ènìyàn, ko tẹ̀síwájú láti máa rú ẹbọ ní àwọn ibi gíga. Ṣùgbọ́n sí Olúwa Ọlọ́run wọn nìkan.
Yuda dunu da sogebi higagaia gebewane gobele salalasu. Be ilia da Hina Gode Ema fawane gobele salasu.
18 Àwọn iṣẹ́ yòókù ti ìjọba Manase pẹ̀lú àdúrà rẹ̀ sí Ọlọ́run rẹ̀ àti àwọn ọ̀rọ̀ tí àwọn aríran sọ sí i ní orúkọ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, wà nínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli.
Ma: na: se ea hawa: hamonanu eno, ea Godema sia: ne gadosu amola balofede dunu amo da Isala: ili Hina Gode Ea Dioba: le ema sia: i, ilia sia: ne iasu, amo huluane da “Isala: ili hina bagade Ilia Hawa: Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
19 Àdúrà rẹ̀ àti bí inú Ọlọ́run ṣe dùn sí àdúrà rẹ̀ àti gbogbo àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ àti àìṣòótọ́, àti àwọn òpó níbi tí ó kọ́ àwọn ibi gíga sí, ó sì gbé àwọn ère Aṣerah àti àwọn òrìṣà kí ó tó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, gbogbo rẹ̀ ni a kọ sínú ìwé ìrántí àwọn aríran.
Hina bagade ea sia: ne gadosu, ema Gode Ea dabe iasu, ea Godema hame sinidigi esoga wadela: i hou hamoi, ea ogogosu ‘gode’ma nodone sia: ne gadosu sogebi, amola wadela: i uda ‘gode’ Asila agoai e da loboga hamoi, amo huluane da “Balofede Dunu ilia Hamonanu Meloa” ganodini dedene legei.
20 Manase sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín sínú ààfin rẹ̀. Amoni ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Ma: na: se da bogole, hina bagade diasua uli dogonesali. Egefe A: imone da e bagia, Yuda hina bagade hamoi.
21 Amoni jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún méjì.
A: imone da lalelegele, ode 22 agoane esalu, bai muni Yuda hina bagade hamoi. E da Yelusaleme moilai bai bagade ganodini esala, ode aduna fawane, Yuda fi ouligilalu
22 Ó ṣe búburú ní ojú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí baba rẹ̀ Manase ti ṣe. Amoni rú ẹbọ sí gbogbo àwọn òrìṣà tí Manase baba rẹ̀ ti ṣe, ó sì sìn wọ́n.
A: imone da ea ada Mana: se defele, Hina Godema wadela: i hou hamosu. E da ea ada ea hou amoma fa: no bobogele, loboga hamoi ogogosu ‘gode’ ilima ea ada nodone sia: ne gadoi, e amolawane ilima nodone sia: ne gadosu.
23 Ṣùgbọ́n kì í ṣe bí i baba rẹ̀ Manase. Kò rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú Olúwa: ṣùgbọ́n ẹ̀ṣẹ̀ Amoni sì ń pọ̀ sì í.
Be ea ada da ea hou fonobone, Hina Godema sinidigi. Be A: imone da agoane hame hamoi. E da ea ada ea wadela: i hou amo baligi dagoi.
24 Àwọn oníṣẹ́ Amoni dìtẹ̀ sí i. Wọ́n sì pa á ní ààfin rẹ̀.
A: imone eagene ouligisu dunu ilia da e medoma: ne, wamo sia: dasu. Amola ilia da hina bagade diasu ganodini, e medole legei dagoi.
25 Nígbà náà, gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà pa gbogbo àwọn tí wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí ọba Amoni, wọ́n sì mú Josiah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Yuda fi dunu da A: imone fasu dunu medole legei. Amola ilia da ea mano Yousaia, e bagia hina bagade ilegei.