< 2 Chronicles 31 >

1 Nígbà tí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ti dé òpin, àwọn ọmọ Israẹli tí ó wà níbẹ̀ jáde lọ sí àwọn ìlú Juda, wọ́n fọ́ àwọn òkúta ìyàsọ́tọ̀ sí wẹ́wẹ́, wọ́n gé àwọn ère Aṣerah lulẹ̀. Wọ́n ba àwọn ibi gíga jẹ́ àti àwọn pẹpẹ jákèjádò Juda àti Benjamini àti ní Efraimu àti Manase. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n ti pa gbogbo wọn run, àwọn ọmọ Israẹli padà sí ìlú wọn àti sí nǹkan ìní wọn.
Bu ishlarning hemmisi tügigendin kéyin, bu yerde hazir bolghan Israillarning hemmisi Yehudaning herqaysi sheherlirige bérip, u yerlerdiki «but tüwrük»lerni chéqip, Asherah butlirini késip tashliwetti; yene Yehuda we Binyamin zéminda, shundaqla Efraim we Manasseh zéminining herqaysi yerliridiki «yuqiri jaylar» we qurban’gahlarni, hemmisini buzup yoqatquche söküp tashlidi. Shuningdin kéyin Israil xelqining herqaysisi öz tewelikige, öz sheherlirige qaytip kétishti.
2 Hesekiah fi lé àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi lọ́wọ́ sí àwọn ìpín olúkúlùkù wọn gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ wọn gẹ́gẹ́ bí àlùfáà tàbí ará Lefi láti tẹ́ ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, láti ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ láti fi ọpẹ́ fún àti láti kọ àwọn orin ìyìn ní ẹnu-ọ̀nà ibùgbé Olúwa.
Hezekiya kahinlar bilen Lawiylarni nöwet-guruppilargha bölüp, kahinlar bilen Lawiylarning herqaysisini özige xas xizmitige békitip, köydürme qurbanliq we inaqliq qurbanliqliri sunup, Perwerdigar öyining hoylilirida, ishik-derwaziliri ichide wezipe ötep, Perwerdigargha teshekkür-medhiye oquydighan qildi.
3 Ọba fi sílẹ̀ láti ara ohun ìní rẹ̀ fun ẹbọ sísun àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ àti fún ẹbọ sísun ní ọjọ́ ìsinmi, òṣùpá tuntun àti ní àjọ̀dún tí a yàn gẹ́gẹ́ bi a ti ṣe kọ ọ́ nínú òfin Olúwa.
Padishah yene öz mélidin bir ülüshni élip köydürme qurbanliqlar üchün ishlitishke buyrudi; bular Perwerdigarning Tewrat qanunida pütülgini boyiche etigenlik we kechlik köydürme qurbanliqlar, shabat küni, yéngi ay we héyt-bayram künliridiki köydürme qurbanliqlar üchün ayrildi.
4 Ó pàṣẹ fún àwọn ènìyàn tí ń gbé ní Jerusalẹmu láti fi ìpín tí ó yẹ fún àlùfáà fún un àti àwọn ará Lefi, kí wọn kí ó lè fi ara wọn jì fún òfin Olúwa.
Padishah yene kahinlar bilen Lawiylarning Perwerdigarning Tewrat qanunini ching ijra qilishi üchün, teqdim qilishqa tégishlik ülüshini ulargha béringlar, dep Yérusalémda turushluq xelqqe buyrudi.
5 Ní kété tí àṣẹ náà jáde lọ, àwọn ọmọ Israẹli fi tìfẹ́tìfẹ́ fi àkọ́so ti ọkà wọn, ọtí tuntun, òróró àti oyin àti gbogbo ohun tí pápá mú jáde lélẹ̀. Wọ́n kó ọ̀pọ̀ iye, àti ìdámẹ́wàá gbogbo nǹkan wá.
Bu buyruq chiqirilishi bilenla, Israillar hosul-mehsulatlirining deslepki élin’ghan qismi ashliq, yéngi sharab, [zeytun] méyi we hesellerni hemde étizliqtin chiqqan herxil mehsulatlarning hosulliridin ekilishti, yene herxil nersilirining ondin birini öshrige türkümlep ekilishti.
6 Àwọn ọkùnrin Israẹli àti Juda ti gbe inú àwọn ìlú Juda pẹ̀lú mú ìdámẹ́wàá agbo ẹran àti ohun èlò àti ohun ọ̀sìn àti ìdámẹ́wàá ti àwọn nǹkan mímọ́ tí a ti yà sọ́tọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wọn, wọ́n sì kó wọn jọ ní òkìtì.
Yehudaning herqaysi sheherliride turuwatqan Israillar bilen Yehudalarmu qoy-kalilirining ondin birini öshrige we Perwerdigar Xudasigha atalghan muqeddes buyumlarning ondin birini öshrige ekilip, döwe-döwe döwiliwetti.
7 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ ṣíṣe èyí ní oṣù kẹta, wọ́n sì parí ní oṣù keje.
Üchinchi aydin bashlap döwilinip, yettinchi aygha kelgende toxtidi.
8 Nígbà tí Hesekiah àti àwọn oníṣẹ́ rẹ̀ wá, tí wọ́n sì rí òkìtì náà, wọ́n yin Olúwa, pẹ̀lú ìbùkún àwọn ènìyàn rẹ̀ Israẹli.
Hezekiya emeldarlar bilen bille kélip, döwe-döwe bolghan bu mehsulatlarni körüp Perwerdigargha teshekkür-medhiye oqudi we Uning xelqi bolghan Israillargha bext-saadet tilidi.
9 Hesekiah béèrè lọ́wọ́ àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi nípa òkìtì;
Hezekiya kahinlar bilen Lawiylardin bu döwe-döwe mehsulatlar toghruluq soriwidi,
10 àti Asariah olórí àlùfáà ti ìdílé Sadoku sì dáhùn pé, “Ní ìwọ̀n ìgbà tí àwọn ènìyàn ti bẹ̀rẹ̀ sí ní mú ìdáwó wọn wá sí ilé Olúwa àti ní èyí tí yóò tó jẹ àti ọ̀pọ̀ láti tọ́jú pamọ́ nítorí Olúwa ti bùkún àwọn ènìyàn rẹ̀, ó sì ṣẹ́kù lọ́pọ̀lọ́pọ̀.”
Zadok jemetidin bolghan bash kahin Azariya uninggha jawap bérip: — Xelq Perwerdigarning öyige hediye keltürgili bashlighandin buyan toyghudek yéduq, yene nurghun éship qaldi. Chünki Perwerdigar Öz xelqini beriketligen, shunga éship qalghinimu shunche köp, dédi.
11 Hesekiah pàṣẹ láti tọ́jú àwọn yàrá ìṣúra nínú ilé Olúwa, wọ́n sì ṣe èyí.
Hezekiya Perwerdigarning öyide ambarlarni teyyarlashni buyruwidi, ular shundaq qildi.
12 Nígbà náà wọ́n mú ọrẹ àti ìdámẹ́wàá àti àwọn ẹ̀bùn tí a yà sí mímọ́ wọ ilé náà wá nítòótọ́. Lórí èyí tí Konaniah ọmọ Lefi, ń ṣe olórí, Ṣimei arákùnrin rẹ̀ ni igbákejì rẹ̀.
Ular semimiy-sadaqetlik bilen hediyelerni, ondin bir öshre we Xudagha alahide atalghan nersilerni ambarlargha ekirdi. Lawiylardin bolghan Kononiya bash ambarchi, inisi Shimey muawin bash ambarchi boldi.
13 Jehieli, Asasiah, Nahati, Asaheli, Jerimoti, Josabadi, Elieli, Ismakia, Mahati àti Benaiah jẹ́ àwọn alábojútó lábẹ́ Konaniah àti Ṣimei arákùnrin rẹ̀ nípa ipá ọba Hesekiah àti Asariah olórí ti ó wà ní ìkáwọ́ ilé Ọlọ́run.
Kononiya we inisi Shimeyning qol astida Yehiyel, Azariya, Naxat, Asahel, Yerimot, Yozabad, Eliyel, Yismaqiya, Mahat we Binayalar nazaret qilish xizmitige mes’ul boldi; bularning hemmisini Hezekiya padishah bilen Xudaning öyining bashqurghuchisi Azariyaning körsetmisi bilen ishleytti.
14 Kore ọmọ Imina ará Lefi olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ìlà-oòrùn, wà ní ìkáwọ́ àwọn ọrẹ àtinúwá tí a fi fún Ọlọ́run, o ń pín ìdáwó tí a ṣe fún Olúwa pẹ̀lú àwọn ẹ̀bùn tí a yà sọ́tọ̀
Sherqiy derwazining derwaziwini Lawiy Yimnahning oghli Kore Xudagha xalis qilin’ghan hediye-sowghatlargha mes’ul idi; u Perwerdigargha sunulghan we «eng muqeddes» bolghan nersilerni teqsim qilatti.
15 Edeni, Miniamini, Jeṣua, Ṣemaiah, Amariah àti Ṣekaniah ràn án lọ́wọ́ tọkàntọkàn nínú àwọn ìlú àwọn àlùfáà tí ń dáwó fún àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ wọn gẹ́gẹ́ bí ìpín wọn, àgbà àti kékeré.
Éden, Minyamin, Yeshua, Shémaya, Amariya we Shékaniyalar uning qol astida bolup, ular kahinlarning herqaysi sheherliride, chong-kichiklikige qaralmay, nöwet boyiche öz qérindashlirigha bularni üleshtürüp bérishke teyinlendi;
16 Ní àfikún, wọ́n pín sí àwọn ọkùnrin àgbà ọdún mẹ́ta tàbí ọ̀pọ̀ tí orúkọ wọn wà nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn. Gbogbo àwọn ti yóò wọ ilé Olúwa láti ṣe oríṣìí iṣẹ́ ti a gbà wọ́n fún gẹ́gẹ́ bí ìgbẹ́kẹ̀lé wọn àti ìpín wọn.
Buningdin bashqa, ular nesebnamige tizimlan’ghan üch yashtin yuqiri erkeklerdin, her küni nöwiti boyiche Perwerdigarning öyige kirip, yüklen’gen wezipisini orunlaydighanlarning hemmisigimu teqsim qilip béretti.
17 Wọ́n sì pín àwọn àlùfáà, wọn kọ orúkọ àwọn ìdílé wọn sínú ìtàn ìdílé àti sí àwọn ará Lefi ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìpinnu àti ìpín wọn.
Ular nesebi tizimlan’ghan jemetliri boyiche kahinlarghimu hemde yigirme yashtin ashqan Lawiylargha nöwiti we wezipisige qarap teqsim qilip béretti;
18 Wọ́n fi gbogbo àwọn ọmọ kéékèèké sí i, àwọn ìyàwó, àti àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin gbogbo ará ìlú tí a kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé ti baba ńlá wọn fún ìrántí. Nítorí tí wọ́n ṣe òtítọ́ ní yíya ara wọn sí ọ̀tọ̀.
nesebnamide «[Lawiy jamaiti]» [dep], pütülginige qarap bularning barliq kichik balilirigha, xotunliri we oghul-qiz perzentlirigimu teqsim qilip béretti; chünki ular sadaqetlik bilen özlirini Xudagha atap paklinip, muqeddes bolushqa béghishlighanidi.
19 Ní ti àwọn àlùfáà, àwọn ìran ọmọ Aaroni, tí ń gbé ni àwọn ilẹ̀ oko lẹ́bàá àwọn ìlú wọn tàbí ní àwọn ìlú mìíràn. A yan àwọn ọkùnrin pẹ̀lú orúkọ láti pín ìlú fún gbogbo ọkùnrin láàrín wọn àti sí gbogbo àwọn tí a kọ sínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá àwọn ará Lefi.
Herqaysi sheherlerning etraplirida olturaqlashqan, Harunning ewladliri bolghan kahinlargha bolsa, herbir sheherde mexsus tizimlan’ghan adem qoyulghanidi; ular kahinlar ichidiki barliq erkeklerge we shundaqla nesebnamide pütülgen barliq Lawiylargha tégishlik ülüshlirini béretti.
20 Èyí ni Hesekiah ṣe jákèjádò Juda, ó sì ṣe ohun tí ó dára àti tí ó tọ́ àti ohun òtítọ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀.
Hezekiya pütün Yehuda zéminida shundaq qildi; u öz Xudasi bolghan Perwerdigar aldida yaxshi, durus we heq bolghanni qildi.
21 Nínú ohun gbogbo tí ó dáwọ́lé ní ti iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Ọlọ́run àti ní ìgbọ́ràn sí òfin àti àwọn àṣẹ. Ó wá Ọlọ́run rẹ̀, ó sì ṣiṣẹ́ tọkàntọkàn. Ó sì ṣe rere.
Meyli Perwerdigarning öyidiki xizmetlerge ait ishta bolsun, meyli Tewrat qanunigha hem emrlirige emel qilish niyitide Xudasini izdeshte bolsun, u pütün qelbi bilen qildi we ronaq tapti.

< 2 Chronicles 31 >