< 2 Chronicles 29 >

1 Hesekiah sì jẹ́ ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Abijah ọmọbìnrin Sekariah.
E rua tekau ma rima nga tau o Hetekia i tona kingitanga, a e rua tekau ma iwa nga tau i kingi ai ia ki Hiruharama; ko te ingoa hoki o tona whaea ko Apia, he tamahine na Hakaraia.
2 Ó sì ṣe ohun tí ó tọ́ ní ojú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí baba rẹ̀ Dafidi ti ṣe.
A he tika tana mahi ki ta Ihowa titiro, i rite ki nga mea katoa i mea ai tona papa, a Rawiri.
3 Ní oṣù àkọ́kọ́ ní ọdún kìn-ín-ní ìjọba rẹ̀, ó sì ṣí àwọn ìlẹ̀kùn ilé Olúwa ó sì tún wọn ṣe.
I te tuatahi o nga tau o tona kingitanga, i te marama tuatahi, ka uakina e ia nga tatau o te whare o Ihowa, hanga ana e ia kia pai.
4 Ó sì mú àwọn àlùfáà wá àti àwọn ọmọ Lefi, ó sì kó wọn jọ yíká ìta ìlà-oòrùn.
Na ka mauria mai e ia ki roto nga tohunga ratou ko nga Riwaiti, a ka huihuia ratou ki te marae i te taha rawhiti,
5 Ó sì wí pé, “Ẹ gbọ́ tèmi, ẹ̀yin ọmọ Lefi! Ẹ ya ara yín sí mímọ́ nísinsin yìí kí ẹ sì ya ilé Olúwa Ọlọ́run sí mímọ́, kí ẹ sì kó ohun àìmọ́ baba mi jáde kúrò ní ibi mímọ́.
A ka mea ia ki a ratou, Whakarongo mai, e nga Riwaiti, whakatapua koutou aianei, whakatapua hoki te whare o Ihowa, o te Atua o o koutou matua, maua atu hoki te mea poke i roto i te wahi tapu.
6 Àwọn baba wa jẹ́ aláìṣòótọ́; wọ́n sì ṣe ohun àìtọ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run wa, wọ́n sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀. Wọ́n sì yí ojú wọn padà kúrò ní ibùgbé Olúwa, wọ́n sì pa ẹ̀yìn wọn dà sí i.
I he hoki o tatou matua, i mahi i te kino i te titiro a Ihowa, a to tatou Atua. Whakarerea ake ia e ratou, tahuri ke ana o ratou aroaro i te tapenakara o Ihowa; hurihia ake e ratou ko o ratou tuara.
7 Wọ́n sì tún ti ìlẹ̀kùn ìloro náà pẹ̀lú, wọ́n sì pa fìtílà. Wọn kò sì sun tùràrí tàbí pèsè ẹbọ sísun si ibi mímọ́ si Ọlọ́run Israẹli.
Ko nga tatau ano o te whakamahau, i tutakina e ratou; tineia iho nga rama, kihai hoki he whakakakara i tahuna e ratou; a kahore he tahunga tinana i whakaekea i te wahi tapu ki te Atua o Iharaira.
8 Nítorí náà, ìbínú Olúwa ti ru sókè wá sórí Juda àti Jerusalẹmu ó sì ti fi wọ́n ṣe ohun èlò fún wàhálà, àti ìdààmú àti ẹ̀sín, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe fi ojú rẹ̀ rí i.
Koia te riri o Ihowa i anga ai ki a Hura, ki Hiruharama, a tukua ana ratou e ia kia whiuwhiua, hei miharo me ta o koutou kanohi e kite nei.
9 Ìdí nìyí tí àwọn baba wa ṣe ṣubú nípa idà àti ìdí tí àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin àti àwọn aya wa tiwọn kó wọ́n ní ìgbèkùn.
Nana, kua hinga nei o tatou matua i te hoari; ko te mea ano tenei i whakaraua ai a tatou tama, a tatou tamahine, a tatou wahine.
10 Nísinsin yìí ó wà ní ọkàn mi láti bá Olúwa Ọlọ́run Israẹli dá májẹ̀mú. Bẹ́ẹ̀ ni kí ìbínú rẹ̀ kíkan kí ó lè yípadà kúrò lọ́dọ̀ wa.
Na ko ta toku ngakau tenei, kia whakaritea he kawenata ki a Ihowa, ki te Atua o Iharaira, kia tahuri atu ai i a tatou tona riri e mura nei.
11 Àwọn ọmọ mi, ẹ má ṣe jáfara nísinsin yìí, nítorí tí Olúwa ti yàn yín láti dúró níwájú rẹ̀ láti sin, kí ẹ sì máa ṣe ìránṣẹ́ níwájú rẹ̀ àti láti sun tùràrí.”
E aku tama, kaua koutou e mangere: he mea whiriwhiri nei hoki koutou na Ihowa hei tu ki tona aroaro, hei mahi ki a ia, hei minita ki a ia, hei tahu whakakakara.
12 Nígbà náà àwọn ọmọ Lefi wọ̀nyí múra láti ṣe iṣẹ́: nínú àwọn ọmọ Kohati, Mahati ọmọ Amasai: àti Joẹli ọmọ Asariah; nínú àwọn ọmọ Merari, Kiṣi ọmọ Abdi àti Asariah ọmọ Jehaleeli; nínú àwọn ọmọ Gerṣoni, Joah, ọmọ Simma àti Edeni ọmọ Joah;
Katahi ka whakatika nga Riwaiti, a Mahata tama a Amahai, a Hoera tama a Ataria, no nga tama a nga Kohati: a, o nga tama a Merari, ko Kihi tama a Apari, ko Ataria tama a Ieharereere: o nga Kerehoni hoki, ko Ioaha tama a Tima, ko Erene tama a Ioah a:
13 nínú àwọn ọmọ Elisafani, Ṣimri àti Jeieli; nínú àwọn ọmọ Asafu, Sekariah àti Mattaniah;
A, o nga tama a Eritapana, ko Himiri, ko Teiere: o nga tama a Ahapa, ko Hakaraia, ko Matania;
14 nínú àwọn ọmọ Hemani, Jehieli àti Ṣimei; nínú àwọn ọmọ Jedutuni, Ṣemaiah àti Usieli.
O nga tama a Hemana, ko Tehiere, ko Himei; o nga tama e Ierutunu, ko Hemaia, ko Utiere.
15 Nígbà tí wọ́n sì ti kó ara wọn jọ pọ̀ pẹ̀lú àwọn arákùnrin wọn, wọ́n sì ya ara wọn sí mímọ́, wọ́n sì lọ láti gbá ilé Olúwa mọ́, gẹ́gẹ́ bí ọba ti pa á láṣẹ, ẹ tẹ̀lé ọ̀rọ̀ Olúwa.
Na huihuia ana e ratou o ratou tuakana, teina, kei te whakatapu ratou i a ratou, a haere ana ki roto ki ta te kingi i whakahau ai, ara ki ta Ihowa i ki ai, ki te pure i te whare o Ihowa.
16 Àwọn àlùfáà sì wọ inú ilé Olúwa lọ́hùn ún lọ láti gbá a mọ́. Wọ́n sì gbé e jáde sí inú àgbàlá ilé Olúwa gbogbo ohun àìmọ́ tí wọ́n rí nínú ilé Olúwa. Àwọn ọmọ Lefi sì mú u wọ́n sì gbangba odò Kidironi.
Na haere ana nga tohunga ki roto rawa i te whare o Ihowa ki te tahi i te poke, a whakaputaina ana e ratou ki waho nga mea poke katoa i kitea i roto i te temepara o Ihowa ki te marae o te whare o Ihowa. Na tangohia ana e nga Riwaiti, kawea ana ki waho ki te awa ki Kitirono.
17 Wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ ìyàsímímọ́ ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kìn-ín-ní, àti ní ọjọ́ kẹjọ oṣù náà wọ́n sì dé ìloro Olúwa. Fún ọjọ́ mẹ́jọ mìíràn sí i, wọ́n sì ya ilé Olúwa sí mímọ́ fúnra rẹ̀. Wọ́n sì parí ní ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù kìn-ín-ní.
No te ra tuatahi o te marama tuatahi i timata ai ratou te whakatapu, a no te waru o nga ra o te marama i tae ai ratou ki te whakamahau o Ihowa. Na whakatapua ana e ratou te whare o Ihowa, e waru nga ra; a no te tekau ma ono o nga ra o te marama tuatahi i oti ai.
18 Nígbà náà wọn sì lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Hesekiah láti lọ jábọ̀ fún un: “Àwa ti gbá ilé Olúwa mọ́, pẹpẹ ẹbọ sísun pẹ̀lú gbogbo ohun ẹbọ rẹ̀, àti tábìlì àkàrà ìfihàn, pẹ̀lú gbogbo ohun èlò.
Katahi ka haere ratou ki roto, kite kingi, ki a Hetekia, a ka mea, Kua tahia e matou te poke o te whare o Ihowa, o te aata tahunga tinana, o ona mea katoa, o te tepu taro aroaro, o ona mea katoa.
19 A ti pèsè a sì ti yà sí mímọ́ gbogbo ohun èlò tí ọba Ahasi ti sọ di aláìmọ́ nínú àìṣòótọ́ rẹ̀ nígbà tí ó jẹ́ ọba; nísinsin yìí, wọ́n wà níwájú pẹpẹ Olúwa.”
Ko nga oko katoa hoki i akiritia atu e Kingi Ahata i tona kingitanga, i a ia i he ra, kua oti i a matou te whakapai, te whakatapu. Nana, ko aua mea ra kei te aronga o te aata a Ihowa.
20 Ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ọba Hesekiah sì kó olórí àwọn ìjòyè jọ, ó sì lọ sókè ilé Olúwa.
Katahi ka maranga wawe a Kingi Hetekia i te ata, huihuia ana e ia nga rangatira o te pa, haere ana ia ki runga, ki te whare o Ihowa.
21 Wọ́n sì mú akọ màlúù méje wá, àti àgbò méje, àti ọ̀dọ́-àgùntàn méje àti òbúkọ méje gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ fún ìjọba, fún ibi mímọ́ àti fún Juda. Ọba pàṣẹ fun àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Aaroni, láti ṣe èyí lórí pẹpẹ Olúwa.
A ka kawea mai e ratou e whitu nga puru, e whitu nga hipi toa, e whitu nga reme, e whitu nga koati toa, hei whakahere hara mo te kingitanga, mo te wahi tapu, a mo Hura. Na whakahaua atu ana e ia kia whakaekea e nga tohunga, e nga tama a Arona ki runga ki te aata a Ihowa.
22 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì pa akọ màlúù, àwọn àlùfáà mú ẹ̀jẹ̀ náà, wọ́n sì fi wọ́n ara pẹpẹ. Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni nígbà tí wọ́n pa àgbò, wọ́n sì fi ẹ̀jẹ̀ wọ́n orí pẹpẹ. Nígbà náà wọ́n sì pa ọ̀dọ́-àgùntàn, wọ́n sì fi ẹ̀jẹ̀ wọn ara pẹpẹ.
Heoi patua ana e ratou nga kau, a ka riro nga toto i nga tohunga, tauhiuhia atu ana e ratou ki te aata. I patua ano e ratou nga hipi toa, tauhiuhia atu ana nga toto ki te aata. Patua ana ano e ratou nga reme, a tauhiuhia ana nga toto ki te aata.
23 Òbúkọ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni wọ́n gbé wá síwájú ọba àti ìjọ ènìyàn, wọ́n sì gbé ọwọ́ lé wọn.
Na ka whakatataia mai e ratou nga koati toa hei whakahere hara i te aroaro o te kingi ratou ko te whakaminenga; pokia iho ana o ratou ringa ki runga ki a ratou.
24 Àwọn àlùfáà wọn sì pa òbúkọ, wọ́n sì gbé ẹ̀jẹ̀ kalẹ̀ lórí pẹpẹ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún gbogbo Israẹli, nítorí ọba ti pàṣẹ kí a ṣe ẹbọ sísun àti ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ fún gbogbo Israẹli.
Na ka patua e nga tohunga, whakaherea ana o ratou toto mo nga hara ki runga ki te aata, hei whakamarie mo Iharaira katoa: na te kingi hoki i ki mo Iharaira katoa te tahunga tinana me te whakahere hara.
25 Ó sì mú àwọn Lefi dúró nínú ilé Olúwa pẹ̀lú Kimbali, ohun èlò orin olókùn àti dùùrù ní ọ̀nà tí a ti paláṣẹ fún wọn láti ọ̀dọ̀ Dafidi àti Gadi aríran ọba àti Natani wòlíì. Èyí ni a pàṣẹ láti ọ̀dọ̀ Olúwa láti ọwọ́ àwọn wòlíì rẹ̀.
I whakaturia ano e ia nga Riwaiti ki te whare o Ihowa, he himipora a ratou, he hatere, he hapa; ko ta Rawiri hoki ia i whakahau ai, ratou ko Kara matakite a te kingi, ko Natana poropiti: na Ihowa hoki te whakahau, ara na ana poropiti.
26 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Lefi sì dúró pẹ̀lú ohun èlò orin Dafidi, àti àwọn àlùfáà pẹ̀lú ìpè wọn.
Tu ana tera nga Riwaiti, me nga mea whakatangi a Rawiri, me nga tohunga ano, mau tetere ana.
27 Hesekiah sì pa á láṣẹ láti rú ẹbọ sísun lórí pẹpẹ, bí ẹbọ sísun náà ti bẹ̀rẹ̀, orin sí Olúwa bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ìpè àti pẹ̀lú ohun èlò orin Dafidi ọba Israẹli.
Na ka whakahau a Hetekia kia whakaekea te tahunga tinana ki runga ki te aata. Na i te wa i timata ai te tahunga tinana, ka timataia ano te waiata a Ihowa, me nga tetere, me nga mea whakatangi a Rawiri kingi o Iharaira.
28 Gbogbo ìjọ ènìyàn náà sì wólẹ̀ sìn, àwọn akọrin kọrin, àwọn afùnpè sì fọn ìpè, gbogbo wọ̀nyí sì wà bẹ́ẹ̀ títí ẹbọ sísun náà fi parí tán.
Na koropiko katoa ana te whakaminenga, waiata ana nga kaiwaiata, whakatangihia ana nga tetere: i mahia katoa tenei a mutu noa te tahunga tinana.
29 Nígbà tí wọ́n sì ṣe ìparí ẹbọ rírú, ọba àti gbogbo àwọn tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ tẹ ara wọn ba, wọ́n sì sìn.
A, no te mutunga o te whakaeke, ka tuohu te kingi me ona hoa katoa i reira, a koropiko ana.
30 Pẹ̀lúpẹ̀lú Hesekiah ọba, àti àwọn ìjòyè pàṣẹ fún àwọn ọmọ Lefi, láti fi ọ̀rọ̀ Dafidi àti ti Asafu aríran, kọrin ìyìn sí Olúwa: wọ́n sì fi inú dídùn kọrin ìyìn, wọ́n sì tẹrí wọn ba, wọ́n sì sìn.
I whakahau ano a Kingi Hetekia me nga rangatira ki nga Riwaiti kia whakamoemiti ki a Ihowa; hei nga kupu ano a Rawiri raua ko Ahapa matakite. Na kei te whakamoemiti ratou; me te koa; tuohu ana ratou, koropiko ana ano.
31 Nígbà náà ni Hesekiah dáhùn, ó sì wí pé, nísinsin yìí, ọwọ́ yín kún fún ẹ̀bùn fún Olúwa, ẹ súnmọ́ ìhín, kí ẹ sì mú ẹbọ àti ọrẹ-ọpẹ́ wá sínú ilé Olúwa. Ìjọ ènìyàn sì mú ẹbọ àti ọrẹ-ọpẹ́ wá; àti olúkúlùkù tí ọkàn rẹ̀ fẹ́, mú ẹbọ sísun wá.
Katahi a Hetekia ka oho, ka mea, Na kua whakatapua nei koutou ki a Ihowa, neke mai, kawea mai nga patunga tapu, me nga whakawhetai ki te whare o Ihowa. Na kei te kawe mai te whakaminenga i nga patunga tapu, i nga whakawhetai, a he tahunga tinana ano ta nga ngakau hihiko katoa.
32 Iye ẹbọ sísun, tí ìjọ ènìyàn mú wá, sì jẹ́ àádọ́rin akọ màlúù, àti ọgọ́rùn-ún àgbò, àti igba ọ̀dọ́-àgùntàn, gbogbo wọ̀nyí sì ni fún ẹbọ sísun sí Olúwa.
Na, ko te maha o nga tahunga tinana i kawea nei e te whakaminenga, e whitu tekau kau, kotahi rau hipi toa, e rua rau reme. Ko enei katoa hei tahunga tinana ki a Ihowa.
33 Àwọn ohun ìyàsímímọ́ sì jẹ́ ẹgbẹ̀ta màlúù, àti ẹgbẹ̀rún mẹ́ta àgùntàn.
Na, ko nga mea i whakatapua, e ono rau kau, e toru mano hipi.
34 Ṣùgbọ́n àwọn àlùfáà kò pọ̀ tó, wọn kò sì le bó gbogbo àwọn ẹran ẹbọ sísun náà: nítorí náà àwọn arákùnrin wọn, àwọn Lefi ràn wọ́n lọ́wọ́, títí iṣẹ́ náà fi parí, àti títí àwọn àlùfáà ìyókù fi yà wọ́n sí mímọ́: nítorí àwọn ọmọ Lefi ṣe olóòtítọ́ ní ọkàn ju àwọn àlùfáà lọ láti ya ara wọn sí mímọ́.
Otiia he torutoru rawa nga tohunga, kihai i kaha ki te tihore i nga tahunga tinana katoa. Na ka pikitia ratou e o ratou teina, e nga Riwaiti, a oti noa te mahi, kia oti ra ano te whakatapu a nga tohunga i a ratou; engari hoki nga Riwaiti i nga t ohunga, i tika o ratou ngakau ki te whakatapu i a ratou.
35 Àti pẹ̀lú, àwọn ẹbọ sísun pàpọ̀jù, pẹ̀lú ọ̀rá ẹbọ àlàáfíà, pẹ̀lú ẹbọ ohun mímu fún ẹbọ sísun. Bẹ́ẹ̀ ni a sì tún bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìsìn ilé Olúwa.
A he tini nga tahunga tinana, me te ngako o nga whakahere mo te pai, me nga ringihanga ano mo nga tahunga tinana. Heoi kua oti te mahi o te whare o Ihowa te whakatika.
36 Hesekiah sì yọ̀, àti gbogbo ènìyàn pé, Ọlọ́run ti múra àwọn ènìyàn náà sílẹ̀, nítorí lójijì ni a ṣe nǹkan náà.
Na koa tonu a Hetekia ratou ko te iwi katoa, mo ta te Atua i whakarite ai ma te iwi; he mea oho tata hoki tenei.

< 2 Chronicles 29 >