< 2 Chronicles 25 >

1 Amasiah jẹ́ ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jehoadani, ó wá láti Jerusalẹmu.
Амация а ажунс ымпэрат ла вырста де доуэзечь ши чинч де ань ши а домнит доуэзечь ши ноуэ де ань ла Иерусалим. Мама са се кема Иоадан, дин Иерусалим.
2 Ó ṣe ohun tí ó dára lójú Olúwa, ṣùgbọ́n kì í ṣe tọkàntọkàn.
Ел а фэкут че есте бине ынаинтя Домнулуй, дар ку о инимэ каре ну ера ын тотул датэ Луй.
3 Lẹ́yìn tí ìjọba ti wà ní ìdarí rẹ̀, ó pa àwọn oníṣẹ́ tí ó pa baba rẹ̀ ọba.
Кынд с-а ынтэрит домния ын мыниле луй, а оморыт пе служиторий каре учисесерэ пе ымпэратул, татэл сэу.
4 Síbẹ̀ kò pa àwọn ọmọ wọn, ṣùgbọ́n ó ṣe ní ìbámu pẹ̀lú ohun tí a kọ nínú òfin nínú ìwé Mose, níbi tí Olúwa ti paláṣẹ pé, “A kò gbọdọ̀ pa àwọn baba fún àwọn ọmọ wọn tàbí àwọn ọmọ fún baba wọn, olúkúlùkù ni kí ó kú fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.”
Дар н-а оморыт пе фиий лор, кэч а лукрат потривит ку чея че есте скрис ын леӂе, ын картя луй Мойсе, унде Домнул дэ порунка ачаста: „Сэ ну се омоаре пэринций пентру копий ши сэ ну се омоаре копиий пентру пэринць, чи фиекаре сэ фие оморыт пентру пэкатул луй.”
5 Amasiah, pe gbogbo àwọn ènìyàn Juda pọ̀, ó sì fi iṣẹ́ lé wọn lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn sí àwọn alákòóso ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún fún gbogbo Juda àti Benjamini, ó sì gbá iye wọn láti ẹni ogún ọdún àti jù bẹ́ẹ̀ lọ jọ, ó sì rí i pé ọ̀kẹ́ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún àwọn ọkùnrin ni ó ti múra fún ìsìn ogun, tí ó lè gbá ọ̀kọ̀ àti àpáta mú.
Амация а стрынс пе оамений дин Иуда ши й-а пус дупэ каселе пэринтешть, кэпетений песте мий ши кэпетений песте суте, пентру тот Иуда ши Бениамин. Ле-а фэкут нумэрэтоаря де ла вырста де доуэзечь де ань ын сус ши а гэсит трей суте де мий де оамень алешь, ын старе сэ поарте армеле, мынуинд сулица ши скутул.
6 Ó sì yá ọ̀kẹ́ márùn-ún àwọn ọkùnrin oníjà láti Israẹli fún ọgọ́rùn-ún àwọn tálẹ́ǹtì fàdákà.
А май токмит ку платэ дин Исраел о сутэ де мий де витежь, ку о сутэ де таланць де арӂинт.
7 Ṣùgbọ́n ènìyàn Ọlọ́run kan tọ̀ ọ́ wá ó sì wí pé, “Ọba, àwọn ọ̀wọ́ ogun láti Israẹli kò gbọdọ̀ yan pẹ̀lú rẹ, nítorí tí Olúwa kò wà pẹ̀lú Israẹli kì í ṣe pẹ̀lú ẹnìkankan láti Efraimu.
Ун ом ал луй Думнезеу а венит ла ел ши а зис: „Ымпэрате, сэ ну мяргэ ку тине оастя луй Исраел, кэч Домнул ну есте ку Исраел, ну есте ку тоць ачешть фий ай луй Ефраим.
8 Àní, tí ẹ bá lọ jà pẹ̀lú ìmúláyàle ní ojú ogun, Ọlọ́run yóò bì ọ́ ṣubú níwájú àwọn ọ̀tá, nítorí Ọlọ́run ní agbára láti ràn ọ́ lọ́wọ́ àti láti bì ọ́ ṣubú.”
Дакэ мерӂь ку ей, кяр дакэ ай фаче ла луптэ фапте де витежие, сэ штий кэ Думнезеу те ва фаче сэ казь ынаинтя врэжмашулуй. Кэч Думнезеу аре путере сэ те ажуте ши сэ те факэ сэ казь.”
9 Amasiah sì bi ènìyàn Ọlọ́run pé, “Ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì tí mo ti san fún àwọn ọ̀wọ́ ogun àwọn ọmọ Israẹli ń kọ́?” Ènìyàn Ọlọ́run dáhùn pé “Olúwa lè fún ọ ní èyí tí ó ju ìyẹn lọ.”
Амация а зис омулуй луй Думнезеу: „Дар че сэ фак ку чей о сутэ де таланць пе каре й-ам дат оастей луй Исраел?” Омул луй Думнезеу а рэспунс: „Домнул поате сэ-ць дя мулт май мулт декыт атыт.”
10 Bẹ́ẹ̀ ni Amasiah, tú àwọn ọwọ́ ogun tí ó ti wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ láti Efraimu ká. Ó sì rán wọn lọ ilé. Wọ́n kún fún ìbínú pẹ̀lú Juda, wọ́n sì padà lọ ilé pẹ̀lú ìbínú ńlá.
Атунч, Амация а деспэрцит чата каре-й венисе дин Ефраим ши а порунчит ка оамений ачештя сэ се ынтоаркэ акасэ. Дар ей с-ау мыният фоарте таре пе Иуда ши ау плекат акасэ ку маре фурие.
11 Nígbà náà, Amasiah ko ogun rẹ jọ àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ lọ sí àfonífojì iyọ̀, níbi tí ó ti pa ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá àwọn ọkùnrin Seiri.
Амация с-а ымбэрбэтат ши шь-а дус попорул ын Валя Сэрий, унде а бэтут зече мий де оамень дин фиий луй Сеир.
12 Àwọn ọkùnrin Juda pẹ̀lú fi agbára mú àwọn ọkùnrin ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá láààyè. Wọ́n mú wọn lọ sí orí òkè bèbè òkúta, wọ́n jù wọ́n sílẹ̀, kí gbogbo wọn sì fọ́ sí wẹ́wẹ́.
Ши фиий луй Иуда ау принс дин ей зече мий де иншь вий, пе каре й-ау дус пе вырфул уней стынчь, де унде й-ау прэвэлит ын вале, аша ынкыт тоць ау фост здробиць.
13 Ní báyìí àwọn ọ̀wọ́ ogun tí Amasiah ti rán lọ padà, tí wọn kò nípa nínú ogun gbógun sí àwọn ìlú Juda láti Samaria sí Beti-Horoni. Wọ́n pa ẹgbẹ̀rún mẹ́ta nínú wọn, wọ́n sì kó ọ̀pọ̀ ìkógun ńlá.
Ынсэ оамений дин чата кэрея ый дэдусе друмул ка сэ ну мяргэ ла рэзбой ку ел ау нэвэлит ын четэциле луй Иуда, де ла Самария пынэ ла Бет-Хорон, ау учис аколо трей мий де иншь ши ау луат мулте прэзь.
14 Nígbà tí Amasiah padà láti ibi pípa àwọn ará Edomu, ó mú àwọn ọlọ́run àwọn ènìyàn Seiri padà wá. Ó gbé wọn kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bi àwọn ọlọ́run tirẹ̀. Ó tẹríba fún wọn, ó sì rú ẹbọ fún wọn.
Кынд с-а ынторс Амация де ла ынфрынӂеря едомицилор, а адус пе думнезеий фиилор луй Сеир ши й-а пус думнезей пентру ел; с-а ынкинат ынаинтя лор ши ле-а адус тэмые.
15 Ìbínú Olúwa ru sí Amasiah, ó sì rán wòlíì kan sí i, tí ó wí pé, “Kí ni ó dé tí ìwọ fi ń béèrè lọ́wọ́ àwọn ọlọ́run àwọn ènìyàn yìí, tí wọn kò le gba àwọn ènìyàn tiwọn kúrò lọ́wọ́ rẹ?”
Атунч, Домнул С-а апринс де мыние ымпотрива луй Амация ши а тримис ла ел пе ун пророк, каре й-а зис: „Пентру че ай кэутат пе думнезеий попорулуй ачестуя, кынд ей н-ау путут сэ-шь избэвяскэ попорул дин мына та?”
16 Bí ó ti n sọ̀rọ̀, ọba wí fún un pé, “Ṣé a yàn ọ́ ní olùgba ọba lámọ̀ràn ni? Dúró! Èéṣe tí a ó fi lù ọ́ bolẹ̀?” Bẹ́ẹ̀ ni, wòlíì náà dúró ṣùgbọ́n ó wí pé, “Èmi mọ̀ pé Ọlọ́run ti pinnu láti pa ọ́ run nítorí ìwọ ti ṣe èyí, ìwọ kò sì tẹ́tí sí ìmọ̀ràn mi.”
Пе кынд ворбя ел, Амация й-а зис: „Оаре те-ам фэкут сфетник ал ымпэратулуй? Плякэ! Пентру че врей сэ фий ловит?” Пророкул а плекат зикынд: „Штиу акум кэ Думнезеу а хотэрыт сэ те нимичяскэ, пентру кэ ай фэкут лукрул ачеста ши н-ай аскултат сфатул меу.”
17 Lẹ́yìn tí Amasiah ọba Juda ti béèrè lọ́wọ́ àwọn olùdámọ̀ràn, ó rán ìpèníjà yìí sí Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọmọ Jehu, ọba Israẹli pé, “Wá bá mi lójúkojú.”
Дупэ че с-а сфэтуит, Амация, ымпэратул луй Иуда, а тримис сэ спунэ луй Иоас, фиул луй Иоахаз, фиул луй Иеху, ымпэратул луй Исраел: „Вино сэ не ведем фацэ ын фацэ!”
18 Ṣùgbọ́n Jehoaṣi ọba Israẹli fèsì padà sí Amasiah ọba Juda pé, “Koríko kékeré kan ní Lebanoni rán iṣẹ́ sí igi kedari ní Lebanoni, fi ọmọbìnrin rẹ fún ọmọkùnrin mi ní ìgbéyàwó. Nígbà náà, ẹhànnà ẹranko ènìyàn ni Lebanoni wá, ó sì tẹ òṣùṣú náà lábẹ́ ẹsẹ̀.
Ши Иоас, ымпэратул луй Исраел, а тримис сэ спунэ луй Амация, ымпэратул луй Иуда: „Спинул дин Либан а тримис сэ спунэ чедрулуй дин Либан: ‘Дэ пе фийкэ-та де невастэ фиулуй меу!’ Ши фяреле сэлбатиче дин Либан ау трекут ши ау кэлкат ын пичоаре спинул.
19 Ìwọ wí fún ara à rẹ wí pé, ìwọ ti ṣẹ́gun Edomu àti nísinsin yìí ìwọ ní ìhàlẹ̀ àti ìgbéraga. Ṣùgbọ́n dúró ní ilé! Kí ni ó dé tí ìwọ fi ń wá wàhálà tí o sì fi ń fa ìṣubú rẹ àti ti Juda pẹ̀lú?”
Ту те гындешть кэ ай бэтут пе едомиць ши де ачея ци се ыналцэ инима ка сэ те мындрешть. Акум стай май бине акасэ. Пентру че сэ стырнешть ун рэу каре ць-ар адуче пеиря та ши а луй Иуда?”
20 Amasiah, bí ó tì wù kí ó rí kò tẹ́tí nítorí Ọlọ́run ṣe é kí ó lè gbé wọn lé Jehoaṣi lọ́wọ́: nítorí wọ́n wá àwọn ọlọ́run Edomu.
Дар Амация ну л-а аскултат, фииндкэ Думнезеу хотэрысе сэ-й дя ын мыниле врэжмашулуй, кэч кэутасерэ пе думнезеий Едомулуй.
21 Bẹ́ẹ̀ ni Jehoaṣi, ọba Israẹli: òun àti Amasiah ọba Juda dojúkọ ara wọn ní Beti-Ṣemeṣi ní Juda.
Ши Иоас, ымпэратул луй Исраел, с-а суит ши с-ау вэзут ын фацэ ел ши Амация, ымпэратул луй Иуда, ла Бет-Шемешул луй Иуда.
22 Àwọn ọmọ Israẹli da Juda rú, gbogbo olúkúlùkù ènìyàn sì sálọ sí ìlú rẹ̀.
Иуда а фост бэтут де Исраел, ши фиекаре а фуӂит ын кортул луй.
23 Jehoaṣi ọba Israẹli fi agbára mú Amasiah ọba Juda, ọmọ Joaṣi ọmọ Ahasiah ní Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà Joaṣi mú u wá sí Jerusalẹmu. Ó sì wó ògiri Jerusalẹmu lulẹ̀ láti ẹnu-ọ̀nà Efraimu sí igun ẹnu-ọ̀nà apá kan títí ń lọ sí irinwó ìgbọ̀nwọ́ ní gígùn.
Иоас, ымпэратул луй Исраел, а луат ла Бет-Шемеш пе Амация, ымпэратул луй Иуда, фиул луй Иоас, фиул луй Иоахаз. Л-а адус ла Иерусалим ши а фэкут о спэртурэ де патру суте де коць ын зидул Иерусалимулуй, де ла Поарта луй Ефраим пынэ ла Поарта Унгюлуй.
24 Ọba kó gbogbo wúrà àti fàdákà àti gbogbo ohun èlò tí wọ́n rí ni ilé Ọlọ́run tí ọ́ wà ní àbojútó Obedi-Edomu, lápapọ̀ pẹ̀lú àwọn ìṣúra ààfin àti àwọn ògo pẹ̀lú, ó sì padà lọ sí Samaria.
А луат тот аурул ши арӂинтул, ши тоате васеле каре се афлау ын Каса луй Думнезеу, ла Обед-Едом, ши вистиерииле касей ымпэратулуй. А луат ши остатичь ши с-а ынторс ла Самария.
25 Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda gbé fún ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún lẹ́yìn ikú Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọba Israẹli.
Амация, фиул луй Иоас, ымпэратул луй Иуда, а трэит чинчспрезече ань дупэ моартя луй Иоас, фиул луй Иоахаз, ымпэратул луй Исраел.
26 Fún ti iṣẹ́ mìíràn ti ìjọba Amasiah láti ìbẹ̀rẹ̀ dé ìparí, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé àwọn ọba Juda àti Israẹli?
Челелалте фапте але луй Амация, челе динтый ши челе де пе урмэ, ну сунт скрисе оаре ын картя ымпэрацилор луй Иуда ши Исраел?
27 Láti ìgbà tí Amasiah ti yípadà kúrò láti máa tẹ̀lé Olúwa, wọ́n dìtẹ̀ sí i ní Jerusalẹmu, ó sì sálọ sí Lakiṣi ṣùgbọ́n, wọ́n rán àwọn ọkùnrin tẹ̀lé e lọ sí Lakiṣi, wọ́n sì pa á síbẹ̀.
Де кынд с-а абэтут Амация де ла Домнул, с-а фэкут ымпотрива луй о унелтире ла Иерусалим, ши ел а фуӂит ла Лакис. Дар л-ау урмэрит ла Лакис ши л-ау оморыт.
28 A gbé e padà pẹ̀lú ẹṣin. A sì sin ín pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ ní ìlú ńlá ti Juda.
Л-ау адус пе кай ши л-ау ынгропат ку пэринций сэй ын четатя луй Иуда.

< 2 Chronicles 25 >