< 2 Chronicles 24 >
1 Joaṣi jẹ́ ọmọ ọdún méje nígbà tí ó jẹ ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ogójì ọdún. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Sibia ti Beerṣeba.
E whitu nga tau o Ioaha i a ia i kingi ai; a e wha tekau nga tau i kingi ai ia ki Hiruharama. A ko te ingoa o tona whaea, ko Tipia, no Peerehepa.
2 Joaṣi ṣe ohun tí ó dára ní ojú Olúwa ní gbogbo àkókò Jehoiada àlùfáà.
Na he tika nga mahi a Ioaha ki te titiro a Ihowa i nga ra katoa o te tohunga, o Iehoiara.
3 Jehoiada yan ìyàwó méjì fún un, ó sì ní àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin.
A i tangohia e Iehoiara he wahine mana, tokorua; a ka whanau ana tama, ana tamahine.
4 Ní àkókò kan, Joaṣi pinnu láti tún ilé Olúwa ṣe.
I muri i tenei ka whai ngakau a Ioaha ki te whakahou i te whare o Ihowa.
5 Ó pe àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi jọ, ó wí fún wọn pé, “Ẹ lọ sí àwọn ìlú Juda, kí ẹ sì gba owó ìtọ́sí láti ọwọ́ gbogbo Israẹli láti fi tún ilé Ọlọ́run yín ṣe.” Ṣùgbọ́n àwọn ará Lefi kò ṣe é lẹ́ẹ̀kan náà.
A ka oti nga tohunga me nga Riwaiti te huihui e ia, ka mea ia ki a ratou, Haere ki nga pa o Hura, ki te kohikohi moni mai i a Iharaira katoa hei whakahou i te whare o to koutou Atua, i tenei tau, i tenei tau; ma koutou hoki e whakahohoro taua mah i. Heoi kihai i hohoro i nga Riwaiti.
6 Nítorí náà ọba pa á láṣẹ fún Jehoiada olórí àlùfáà ó sì wí fún un pé, “Kí ni ó dé tí o kò béèrè lọ́wọ́ àwọn ará Lefi láti mú wá láti Juda àti Jerusalẹmu, owó orí tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti fi lélẹ̀ àti nípasẹ̀ àpéjọ gbogbo Israẹli fún àgọ́ ẹ̀rí?”
Na ka karanga te kingi ki a Iehoiara, ko te upoko hoki ia, a ka mea ki a ia, He aha koe te mea ai ki nga Riwaiti kia mauria mai i a Hura, i Hiruharama, te mea i kohikohia, ta Mohi pononga a Ihowa me ta te whakaminenga o Iharaira mo te tapenakara o te whakaaturanga?
7 Nísinsin yìí, àwọn ọmọkùnrin obìnrin búburú ni Ataliah ti fọ́ ilé Ọlọ́run, ó sì ti lo àwọn nǹkan ìyàsọ́tọ̀ fún àwọn Baali.
Na nga tama hoki a taua wahine kino a Ataria i wahi te whare o te Atua; a ko nga mea tapu katoa o te whare o Ihowa, meinga ana e ratou mo nga Paara.
8 Nípasẹ̀ ọba, wọn ṣe àpótí wọ́n sì gbé e sí ìta, ní ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa.
Heoi ka korero te kingi, a ka hanga he pouaka e ratou, whakaturia ana ki waho, ki te kuwaha o te whare o Ihowa.
9 A ṣe ìkéde ní Juda àti Jerusalẹmu wí pé wọ́n gbọdọ̀ mú wá fún Olúwa, owó orí tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti béèrè lọ́wọ́ Israẹli ní aginjù.
Na, ka pa te karanga puta noa i a Hura, i Hiruharama, kia kawea mai ki a Ihowa te kohikohi i whakaritea e Mohi, e ta te Atua pononga, ki a Iharaira i te koraha.
10 Gbogbo àwọn ìjòyè àti gbogbo àwọn ènìyàn sì yọ̀, wọ́n sì mú un wá, wọ́n ń jù ú sínú àpótí títí tí ó fi kún.
Na koa tonu nga rangatira katoa me te iwi katoa, a kawea ana mai e ratou, maka ana ki roto ki te pouaka a rite noa.
11 Nígbàkígbà tí a bá gbé àpótí wọlé láti ọwọ́ àwọn ará Lefi sí ọwọ́ àwọn ìjòyè ọba, tí wọ́n bá sì rí wí pe owó ńlá wà níbẹ̀ àwọn akọ̀wé ọba àti ìjòyè olórí àlùfáà yóò wá láti kó owó rẹ̀ kúrò, wọn yóò sì dá a padà sí ààyè rẹ̀. Wọ́n ṣe èyí déédé, wọ́n sì kó iye owó ńlá.
A, i nga wa e kawea mai ai e nga Riwaiti te pouaka ki te whare takoha o te kingi, a ka kitea kua rahi te moni, ka haere mai te kaituhituhi a te kingi raua ko te tangata a te tino tohunga, ka ringihia e raua nga mea i roto i te pouaka, na ka tang o raua, ka whakahoki ano ki tona wahi. Pena tonu ratou i ia ra, i ia ra, a nui atu te moni i kohikohia.
12 Ọba àti Jehoiada fi fún àwọn ọkùnrin náà tí ó sì ń ṣiṣẹ́ nínú ilé Olúwa. Wọ́n fi owó gba ẹni tí ń fi òkúta mọ ilé àti àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà láti kọ́ ilé Olúwa padà, àti àwọn òṣìṣẹ́ pẹ̀lú irin àti idẹ láti tún ilé Olúwa ṣe.
A hoatu ana e te kingi raua ko Iehoiara ki nga tangata i te mahi o nga mea mo te whare o Ihowa; a na ratou i utu nga kaimahi kohatu, nga kamura, hei whakahou i te whare o Ihowa, nga kaimahi hoki i te rino, i te parahi, hei whakaora mo te whare o Ihowa.
13 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ náà, sì lọ síwájú àti síwájú ní ọwọ́ wọn, wọ́n sì tún mú ilé Ọlọ́run dúró sí ipò rẹ̀, wọ́n mú un le.
Heoi ka mahi nga kaimahi, a ka oti te mahi i a ratou; na kua meinga e ratou kia rite ki to mua ahua te tu o te whare o te Atua, kia kaha hoki.
14 Nígbà tí wọ́n sì parí rẹ̀ tán, wọ́n mú owó ìyókù wá sí iwájú ọba àti Jehoiada, a sì fi ohun èlò fún ilé Olúwa, àní ohun èlò fún ìsìn àti fún ẹbọ pẹ̀lú ọpọ́n, àní ohun èlò wúrà àti fàdákà. Wọ́n sì ń rú ẹbọ sísun ní ilé Olúwa nígbà gbogbo ní gbogbo ọjọ́ Jehoiada.
A, ka oti i a ratou, ka kawea te toenga o te moni ki te aroaro o te kingi raua ko Iehoiara, a ka waiho hei hanga i etahi oko mo te whare o Ihowa, i nga oko minita, i nga mea mo nga patunga tapu, i nga koko, i nga oko koura, hiriwa; a he whakaeke tonu ta ratou i te tahunga tinana i te whare o Ihowa i nga ra katoa o Iehoiara.
15 Ṣùgbọ́n Jehoiada di arúgbó, ó sì kún fún ọjọ́, ó sì kú, ẹni àádóje ọdún ni nígbà tí ó kú.
Otiia kua koroheketia a Iehoiara, kua maha ona ra, a ka mate: kotahi rau e toru tekau ona tau i tona matenga.
16 Wọ́n sì sin ín ní ìlú Dafidi pẹ̀lú àwọn ọba, nítorí tí ó ṣe rere ní Israẹli, àti sí Ọlọ́run àti sí ilé rẹ̀.
A tanumia ana ia ki te pa o Rawiri ki te taha o nga kingi; he pai hoki no tana mahi ki a Iharaira, ki te Atua hoki, a ki tona whare.
17 Lẹ́yìn ikú Jehoiada, àwọn oníṣẹ́ Juda wá láti fi ìforíbalẹ̀ wọn hàn sí ọba. Ó sì fèsì sí wọn.
Na i muri i te matenga o Iehoiara ka haere mai nga rangatira o Hura, a ka piko ki te kingi. Na rongo tonu te kingi ki a ratou.
18 Wọ́n pa ilé Olúwa tì, Ọlọ́run baba a wọn. Wọ́n sì ń sin àwọn ère Aṣerah àti àwọn òrìṣà. Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn yìí, ìbínú Ọlọ́run dé sórí Juda àti Jerusalẹmu.
Na whakarerea ake e ratou te whare o Ihowa, o te Atua o o ratou matua, mahi ana ratou ki nga Aherimi, ki nga whakapakoko. Na kua pa he riri ki a Hura, ki Hiruharama, mo tenei he o ratou.
19 Bí ó ti wù kí ó rí, Olúwa rán àwọn wòlíì sí àwọn ènìyàn láti mú wọn padà sí ọ̀dọ̀ rẹ̀. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé, wọ́n jẹ́rìí nípa wọn, wọn kì yóò gbọ́.
Heoi unga ana e ia nga poropiti ki a ratou hei whakahoki i a ratou ki a Ihowa, a whakawa ana ratou i a ratou: otiia kihai i rongo.
20 Nígbà náà, Ẹ̀mí Ọlọ́run wá sórí Sekariah ọmọ Jehoiada wòlíì, ó dúró níwájú àwọn ènìyàn ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Kí ni ó dé tí ẹ̀yin kò fi tẹ̀lé àṣẹ Olúwa? Ìwọ kì yóò ṣe rere. Nítorí tí ìwọ ti kọ Olúwa sílẹ̀, òun pẹ̀lú ti kọ̀ yín sílẹ̀.’”
Na kua tau te wairua o te Atua ki te tohunga, ki a Hakaraia tama a Iehoiara; a ka tu ia ki runga ake i te iwi, ka mea ki a ratou, Ko te kupu tenei a te Atua, he aha koutou ka takahi ai i nga whakahau a Ihowa? ma konei hoki ka kore ai koutou e ka ke. Kua whakarerea nei e koutou a Ihowa na kua whakarerea hoki koutou e ia.
21 Ṣùgbọ́n wọ́n dìtẹ̀ sí i, àti nípa àṣẹ ọba, wọ́n sọ ọ́ lókùúta pa nínú àgbàlá ààfin ilé Olúwa.
Na ka whakatupuria e ratou he he mona, a akina ia ki te kohatu, na te kingi i whakahau, ki te marae o te whare o Ihowa.
22 Ọba Joaṣi kò rántí inú rere tí Jehoiada baba Sakariah ti fihàn án ṣùgbọ́n, ó pa ọmọ rẹ̀, tí ó wí bí ó ti ń kú lọ pé, “Kí Olúwa kí ó rí èyí kí ó sì pè ọ́ sí ìṣirò.”
Heoi kihai a Kingi Ioaha i mahara ki te aroha i whakaputaina e tona papa, e Iehoiara, ki a ia: heoi patua ana e ia tana tama. A i tona matenga, ka mea ia, Ma Ihowa e titiro, e rapu utu.
23 Ní òpin ọdún, àwọn ọmọ-ogun Aramu yàn láti dojúkọ Joaṣi; wọ́n gbógun ti Juda àti Jerusalẹmu, wọ́n sì pa gbogbo àwọn aṣáájú àwọn ènìyàn. Wọ́n rán gbogbo àwọn ìkógun sí ọba wọn ní Damasku.
Na taka rawa ake te tau, ka whakaekea ia e te taua o Hiria; a haere ana mai ratou ki a Hura, ki Hiruharama, whakangaromia ana e ratou nga rangatira katoa o te iwi i roto i te iwi, tukua ana e ratou o ratou taonga katoa kia kawea ki te kingi o Ra mahiku.
24 Bí ó ti wù kí ó rí, àwọn ọmọ-ogun Aramu ti wá pẹ̀lú àwọn ọkùnrin díẹ̀ Olúwa sì fi ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ-ogun lé wọn lọ́wọ́, nítorí tí Juda ti kọ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn sílẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ṣe ìdájọ́ Joaṣi.
He tokoiti hoki nga tangata o te taua o nga Hiriani i haere mai nei; a hoatu ana e Ihowa te ope nui rawa ki o ratou ringa, mo ratou i whakarere i a Ihowa, i te Atua o o ratou matua. Heoi tutuki ana i a ratou he whakawa mo Ioaha.
25 Nígbà tí àwọn ará Aramu kúrò, wọ́n fi Joaṣi sílẹ̀ pẹ̀lú ọ̀pọ̀ ọgbẹ́. Àwọn oníṣẹ́ rẹ̀ dìtẹ̀ si fún pípa ọmọ Jehoiada àlùfáà, wọ́n sì pa á ní orí ibùsùn rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ó sì kú, a sì sin ín sínú ìlú ńlá ti Dafidi, ṣùgbọ́n kì í ṣe nínú àwọn ibojì àwọn ọba.
A, no to ratou haerenga atu i a ia, i mahue iho hoki ia i a ratou he nui ona mate, ka whakatupuria e ana tangata he he mona, mo nga toto o nga tama a Iehoiara tohunga, a patua ana ia e ratou, ki runga ki tona moenga, a mate iho: na tanumia ana i a e ratou ki te pa o Rawiri, otiia kahore ki nga tanumanga o nga kingi.
26 Àwọn tí ó dìtẹ̀ sì jẹ́ Sabadi, ọmọ Ṣimeati arábìnrin Ammoni àti Jehosabadi ọmọ Ṣimiriti arábìnrin Moabu.
Na ko nga tangata nana i whakatupu te he mona; ko Tapara, tama a tetahi wahine o Amona, a Himeata, ko Iehotapara, tama a tetahi wahine o Moapa, a Timiriti.
27 Àkọsílẹ̀ àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀, àti àkọsílẹ̀ ti ìmúpadà sípò ilé Ọlọ́run ní a kọ sínú ìwé ìtumọ̀ ti àwọn ọba. Amasiah ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Na, ko ana tama, me te nui o nga taimaha i utaina ki runga ki a ia, me te hanganga i te whare o te Atua, nana, kei te tuhituhi ena i roto i nga korero o te pukapuka o nga kingi; a ko tana tama, ko Amatia, te kingi i muri i a ia.