< 2 Chronicles 23 >
1 Ní ọdún keje, Jehoiada fi agbára rẹ̀ hàn. O dá májẹ̀mú pẹ̀lú àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún kan, Asariah ọmọ Jerohamu, Iṣmaeli ọmọ Jehohanani Asariah ọmọ Obedi, Maaseiah ọmọ Adaiah àti Elisafati ọmọ Sikri.
Na i te whitu o nga tau ka whakanuia e Iehoiara he kaha mona; i riro hoki i a ia nga rangatira rau, a Ataria tama a Ierohama, a Ihimaera tama a Iehohanana, a Ataria tama a Opere, a Maaheia tama a Araia, a Erihapata tama a Tikiri, hei hoa mona, me a rawa ki te kawenata.
2 Wọ́n lọ sí gbogbo Juda, wọ́n sì pe àwọn ará Lefi àti àwọn olórí àwọn ìdílé àwọn ará Israẹli láti gbogbo àwọn ìlú jọ. Nígbà tí wọ́n wá sí Jerusalẹmu.
Na haereerea ana e ratou a Hura a taka noa, huihuia ana e ratou nga Riwaiti i roto i nga pa katoa o Hura, ratou ko nga upoko o nga whare o nga matua o Iharaira, a haere ana ratou ki Hiruharama.
3 Gbogbo ìpéjọ náà dá májẹ̀mú pẹ̀lú ọba ní ilé Ọlọ́run. Jehoiada wí fún wọn pé, “Ọmọkùnrin ọba yóò jẹ ọba, bí Olúwa ti ṣèlérí nípa àwọn ìran Dafidi.
Na ka whakarite kawenata te whakaminenga katoa ki te kingi i roto i te whare o te Atua. I mea ano ia ki a ratou, Nana, hei kingi te tama a te kingi, hei pera me ta Ihowa i korero ai mo nga tama a Rawiri.
4 Nísinsin yìí èyí ni ohun tí ó yẹ kí ó ṣe, ìdámẹ́ta àlùfáà yín àti àwọn ará Lefi tí ó ń lọ fún iṣẹ́ ìsìn ní ọjọ́ ìsinmi ni kí ó bojútó àwọn ìlẹ̀kùn.
Ko tenei ta koutou e mea ai; ko te tuatoru o nga wehenga o koutou e haere mai ana i te hapati, ara o nga tohunga, o nga Riwaiti, hei kaitiaki mo nga kuwaha;
5 Ìdámẹ́ta yín níbi ààfin ọba àti ìdámẹ́ta níbi ẹnu odi ìdásílẹ̀ àti gbogbo ọkùnrin mìíràn ni kí ó wà ní àgbàlá ààfin ilé Olúwa.
Ko tetahi o nga wehenga e toru hei te whare o te kingi; ko tetahi o nga wehenga e toru hei te kuwaha o te turanga; ko te iwi katoa hoki hei nga marae o te whare o Ihowa.
6 Kò sí ẹnìkan tí ó gbọdọ̀ wọ inú ilé Olúwa yàtọ̀ sí àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi tí a rán ní iṣẹ́ ìsìn. Wọ́n lè wọlé nítorí tí a ti yà wọ́n sọ́tọ̀, ṣùgbọ́n gbogbo ọkùnrin mìíràn ni kí wọn ó sọ ohun tí Olúwa ti yàn fún wọn.
Kaua ia tetahi e tomo ki te whare o Ihowa, ko nga tohunga anake, ratou ko te hunga o nga Riwaiti e minita ana; ko ratou e haere ki roto, no te mea he tapu ratou. Ko te iwi katoa ia hei tiaki i nga mea a Ihowa.
7 Àwọn ará Lefi gbọdọ̀ wà ní ìdúró ṣinṣin yí ọba ká. Olúkúlùkù pẹ̀lú àwọn nǹkan ìjà ní ọwọ́ rẹ̀. Ẹnikẹ́ni tí ó bá wọ ilé Olúwa ni kí ẹ pa. Ẹ dúró ti ọba níbikíbi tí ó bá lọ.”
Na me karapoti te kingi e nga Riwaiti a tawhio noa; hei tona ringa ano te patu a tenei, a tenei; a ki te tomo tetahi ki te whare, me whakamate. Hei te taha tonu koutou o te kingi i tona haerenga mai, i tona haerenga atu.
8 Àwọn ará Lefi àti gbogbo ọkùnrin Juda ṣe gẹ́gẹ́ bí Jehoiada àlùfáà ti paláṣẹ. Olúkúlùkù mú àwọn ọkùnrin rẹ̀, àwọn tí wọ́n lọ fún iṣẹ́ ìsìn ní ọjọ́ ìsinmi àti àwọn tí wọ́n ń kúrò ní ibi iṣẹ́. Nítorí Jehoiada àlùfáà kò ì tí tú ìpín kankan sílẹ̀.
Na ka meatia e nga Riwaiti, e Hura katoa nga mea katoa i whakahaua e Iehoiara tohunga; a ka mau ratou ki ana tangata, ki ana tangata, ki nga mea e haere ana ki roto i te hapati, ki te hunga ano e haere atu ana ki waho i te hapati; kihai hoki a Ie hoiara tohunga i tuku i nga wehenga kia haere.
9 Jehoiada àlùfáà, sì fi ọ̀kọ̀ àti asà, àti àpáta wọ̀n-ọn-nì, tí ó jẹ́ ti ọba Dafidi tí wọn wà ní ilé Ọlọ́run, fún àwọn balógun ọ̀rọ̀ọ̀rún.
A i homai e Iehoiara tohunga ki nga rangatira rau nga tao, nga pukupuku, me nga whakapuru tao a Kingi Rawiri; i roto hoki era i te whare o te Atua.
10 Ó sì to gbogbo àwọn ènìyàn ti ọba káàkiri, olúkúlùkù pẹ̀lú ohun ìjà rẹ̀ ní ọwọ́ rẹ̀, láti apá ọ̀tún ilé náà títí dé apá òsì ilé náà, lẹ́bàá pẹpẹ àti lẹ́bàá ilé náà.
I whakaturia ano e ia te iwi katoa, me a ratou patu i te ringa o tenei, o tenei, i te koki ki matau o te whare, tae noa ki te koki ki maui o te whare, ki nga taha o te aata, o te whare, hei karapoti mo te kingi.
11 Jehoiada àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ mú ọmọkùnrin ọba jáde wá wọ́n sì gbé adé sórí rẹ̀; wọ́n mú ẹ̀dà májẹ̀mú kan fún un. Wọ́n sì kéde rẹ̀ lọ́ba. Wọ́n fi àmì òróró yàn án, wọ́n sì kígbe pé, “Kí ọba kí ó pẹ́!”
Katahi ka whakaputaina e ratou te tama a te kingi, potaea iho ki a ia te karauna; a homai ana te whakaaturanga ki a ia, na whakakingitia ana ia e ratou; a na Iehoiara ratou ko ana tama ia i whakawahi, me ta ratou karanga, Kia ora te kingi.
12 Nígbà tí Ataliah gbọ́ igbe àwọn ènìyàn tí wọ́n ń sáré tí wọ́n ń kígbe ọba, ó lọ sí ọ̀dọ̀ wọn ní ilé Olúwa.
A, no te rongonga o Ataria i te nge o te iwi e rere ana, e whakamoemiti ana ki te kingi, ka haere ia ki te iwi, ki te whare o Ihowa.
13 Ó sì wò, sì kíyèsi, ọba dúró ní ibùdó rẹ̀ ní ẹ̀bá ẹnu-ọ̀nà, àti àwọn balógun àti àwọn afùnpè lọ́dọ̀ ọba, gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà sì yọ̀, wọ́n sì fọn ìpè, àti àwọn akọrin pẹ̀lú ohun èlò ìyìn. Nígbà náà ni Ataliah fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì kégbe wí pé, “Ọ̀tẹ̀! Ọ̀tẹ̀!”
A ka titiro ia, na ko te kingi e tu ana i te taha o tona pou i te tomokanga, ko nga rangatira ano me nga tetere i te taha o te kingi; a ko te iwi katoa o te whenua e koa ana, e whakatangi ana i nga tetere; ko nga kaiwaiata hoki e whakatangi ana i nga mea rangi waiata, e arahi ana i te waiata whakamoemiti. Katahi ka haehae a Ataria i ona kakahu, ka karanga, He he, he he, te whakatakotoria nei!
14 Jehoiada àlùfáà mú àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún, tí ó wà ní àbojútó àwọn ọ̀wọ́ ogun, ó sì wá wí fún wọn pé, “Mú un jáde wá láàrín àwọn ọgbà, kí a sì fi idà pa ẹnikẹ́ni tí ó bá tẹ̀lé.” Nítorí tí àlùfáà ti wí pé, “Má ṣe pa á nínú ilé Olúwa.”
Na ka whakaputaina e Iehoiara tohunga nga rangatira rau, nga kaitohutohu ope ki waho, a ka mea ia ki a ratou, Mauria mai ia ki waenganui i nga rarangi; a ko te tangata e whai i muri i a ia, whakamatea ki te hoari; i mea hoki te tohunga, Kaua ia e whakamatea i roto i te whare o Ihowa.
15 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n fi ipá mú un kí ó tó dé ẹnu-ọ̀nà àbáwọlé ẹṣin ti ilé ọba, wọ́n sì ti pa á níbẹ̀.
Heoi whakawateatia ana he haerenga mona; na ka tae ia ki te tomokanga o te kuwaha hoiho i te taha o te whare o te kingi, whakamatea iho ki reira.
16 Nígbà náà ni Jehoiada, dá májẹ̀mú pé òun àti àwọn ènìyàn àti ọba yóò jẹ́ ènìyàn Olúwa.
Na ka whakaritea e Iehoiara he kawenata, he mea nana, na te iwi katoa, ratou ko te kingi, kia meinga ratou hei iwi ma Ihowa.
17 Gbogbo àwọn ènìyàn lọ sí ilé Baali, wọ́n sì fà á ya lulẹ̀. Wọ́n fọ́ àwọn pẹpẹ àti àwọn òrìṣà, wọ́n sì pa Mattani àlùfáà Baali níwájú àwọn pẹpẹ.
Na haere ana te iwi katoa ki te whare o Paara, wahia iho e ratou; mongamonga noa i a ratou ana aata, ona ahua; patua iho hoki e ratou a Matana tohunga o Paara ki mua i nga aata.
18 Nígbà náà, Jehoiada tẹ àwòrán ilé Olúwa sí ọwọ́ àwọn àlùfáà tí wọ́n jẹ́ ará Lefi ẹni tí Dafidi ti fi ṣe iṣẹ́ ní ilé Olúwa láti tẹ ẹbọ sísun ti Olúwa bí a ti kọ ọ́ nínú òfin Mose, pẹ̀lú ayọ̀ àti orin kíkọ, gẹ́gẹ́ bí Dafidi ti pàṣẹ.
I whakarite kaitirotiro ano a Iehoiara mo te whare o Ihowa, he mea wehea nei e Rawiri ki roto ki te whare o Ihowa hei whakaeke i nga tahunga tinana a Ihowa, ko te mea hoki ia i tuhituhia i roto i te ture a Mohi; me te koa ano ratou, me te waiata; ko ta Rawiri hoki ia i whakarite ai.
19 Ó mú àwọn olùṣọ́nà wà ni ipò ìdúró ní ẹnu odi ilé Olúwa kí ẹni aláìmọ́ nínú ohunkóhun kó má ba à wọlé.
I whakaturia ano e ia he kaitiaki kuwaha mo nga kuwaha o te whare o Ihowa, kei haere ki roto te tangata e poke ana i tetahi mea.
20 Ó mú pẹ̀lú rẹ̀ àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún, àwọn ẹni ọlá, àwọn olórí àwọn ènìyàn àti gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà. Ó sì mú ọba sọ̀kalẹ̀ wá láti ilé Olúwa. Wọ́n lọ sínú ààfin láti ẹnu òde ti òkè. Wọ́n sì fi ọba jókòó lórí ìtẹ́.
Na tikina ana e ia nga rangatira rau, nga tangata nunui, ratou ko nga kawana o te iwi, ko te iwi katoa ano hoki o te whenua, a mauria iho ana e ratou te kingi i te whare o Ihowa ki raro; na haere ana ratou na to runga kuwaha ki te whare o te kin gi, a whakanohoia ana te kingi ki te torona o te kingitanga.
21 Gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà sì yọ̀, ìlú náà sì dákẹ́ rọ́rọ́. Nítorí a pa Ataliah pẹ̀lú idà.
Heoi koa tonu te iwi katoa o te whenua, a marire noa iho te pa: a patua ana e ratou a Ataria ki te hoari.