< 2 Chronicles 22 >
1 Àwọn ènìyàn Jerusalẹmu mú Ahasiah, ọmọ Jehoramu tí ó kéré jùlọ, jẹ ọba ní ipò rẹ̀, láti ìgbà tí àwọn onísùnmọ̀mí, tí ó wá pẹ̀lú àwọn ará Arabia sínú ibùdó, tí wọn sì ti pa àwọn ọmọkùnrin àgbà. Bẹ́ẹ̀ ni Ahasiah ọmọ Jehoramu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba.
HOOALII iho la ko Ierusalema ia Ahazia i kana keiki pokii, mahope ona; no ka mea, o ka poe koa, ka poe i hele pu me ko Arabia i kahi hoomoana'i, ua pepehi lakou i kana poe keiki mua a pau. Pela i noho alii ai o Ahazia ke keiki a Iehorama a ke alii o ka Iuda.
2 Ahasiah jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún kan. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Ataliah, ọmọ ọmọbìnrin Omri.
Hookahi kanaha makahiki a me kumamalua ko Ahazia i kona lilo ana i alii, a noho alii iho la ia i hookahi makahiki ma Ierusalema: a o ka inoa o kona makuwahine o Atalia ko kaikamahine a Omeri.
3 Ó mú ìrìn ní ọ̀nà ilé Ahabu. Nítorí tí ìyá rẹ̀ kì í láyà nínú ṣíṣe búburú.
A hele no hoi oia ma na aoao o ko ka hale o Ahaba; no ka mea, o kona makuwahine, ua oleloao mai la oia ia ia e hana hewa.
4 Ó ṣe búburú ní ojú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti ṣe, nítorí lẹ́yìn ikú baba a rẹ̀, wọ́n di olùgbani nímọ̀ràn rẹ̀ sí ṣíṣe rẹ̀.
A hana ino iho la oia imua o Iehova, e like me ko ka hale o Ahaba; no ka mea, o lakou ka i oleloao mai ia ia mahope o ka make ana o kona makuakane, a malaila oia i make ai.
5 Ó tẹ̀lé ìgbìmọ̀ wọn nígbà tí ó lọ pẹ̀lú Joramu ọmọ Ahabu ọba Israẹli láti gbógun ti Hasaeli ọba Aramu ní Ramoti Gileadi. Àwọn ará Aramu ṣá Joramu ní ọgbẹ́;
Hele no hoi ia mamoli o ka lakou oleloao, a hele pu oia me Iehorama, ke keiki a Ahaba ke alii o ka Iseraela e kaua aku ia Hazaela i ke alii o Saria, i Ramota-Gileada; a hoeha mai la ko Suria ia Iehorama.
6 bẹ́ẹ̀ ni ó padà sí Jesreeli láti wo ọgbẹ́ rẹ̀ sàn tí wọ́n ti dá sí i lára ní Rama ní ojú ogun rẹ̀ pẹ̀lú Hasaeli ọba Siria. Nígbà náà, Ahasiah, ọmọ Jehoramu ọba Juda lọ sí Jesreeli láti lọ rí Joramu ọmọ Ahabu nítorí a ti ṣá a lọ́gbẹ́.
A hoi mai ia i Iezereela e lapaauia no na eha ona i hoehaia mai ai ma Rama i kona kaua pu ana me Uazaela, ke alii o Suria: a iho aku la o Azaria ke keiki a Iehorama ke alii o ka Iuda e ike ia Iehorama, ke keiki a Ahaba ma Iezereela, no ka mea, ua mai ia.
7 Ní gbogbo ìgbà ìbẹ̀wò Ahasiah sí Joramu, Ọlọ́run mú ìṣubú Ahasiah wá. Nígbà tí Ahasiah dé, ó jáde lọ pẹ̀lú Jehoramu láti lọ bá Jehu ọmọ Nimṣi, ẹni tí Olúwa ti fi àmì òróró yàn láti pa ìdílé Ahabu run.
No ke Akua mai ka make ana o Ahazia i kona hele ana io Iorama la. A i kona hiki ana'ku, hele pu ra me Iehorama e ku e ia Iehu, ke keiki a Nimesi, ka mea a Iehova i poni ai e luku i ko ka hale o Ahaba.
8 Nígbà tí Jehu ń ṣe ìdájọ́ lórí ilé Ahabu, ó rí àwọn ọmọbìnrin ọba ti Juda àti àwọn ọmọkùnrin ìbátan Ahasi, tí ó ń tọ́jú Ahasiah, ó sì pa wọ́n.
A i ko Iehu luka ana i ko ka hale o Ahaba, ua loaa ia ia na'lii o Iuda, na keiki a na hoahanau o Ahazia, e hookauwa ana na Ahazia, a pepehi aku la oia ia lakou.
9 Ó lọ láti wá Ahasiah, àti àwọn ọkùnrin rẹ̀. Àwọn arákùnrin rẹ̀ ṣẹ́gun rẹ̀ nígbà tí ó sá pamọ́ ní Samaria. A gbé e wá sí ọ̀dọ̀ Jehu, a sì pa á. Wọ́n sin ín nítorí wọ́n wí pé, “Ọmọkùnrin Jehoṣafati ni, ẹni tí ó wá Olúwa pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹnìkan ní ilé Ahasiah tí ó lágbára láti gbé ìjọba náà dúró.
A imi iho la oia ia Ahazia, a hopuia oia, (no ka mea, ua hunaia oia ma Samaria, ) a lawe mai lakou ia ia io Iehu la, a pepehi iho la lakou ia ia, a kanu aku no hoi ia ia; no ka mea, olelo ae la lakou, O ke keiki ia a Iehosapata ka mea i imi ia Iehova me kona naau a pau. Aohe mea i koe o ka hale o Ahazia e hiki ai ke malama i ke aupuni.
10 Nígbà tí Ataliah ìyá Ahasiah rí i wí pé ọmọkùnrin rẹ̀ ti kú, ó tẹ̀síwájú láti pa gbogbo ìdílé ọba ti ilẹ̀ Juda run.
A ike o Atalia ka makuwahine o Ahazia, ua make kana keiki, ku ae la ia iluna, a luku aku i ka poe keiki alii a pau no ka hale o Iuda.
11 Ṣùgbọ́n Jehoṣeba ọmọbìnrin ọba Jehoramu mú Joaṣi, ọmọkùnrin Ahasiah ó sì jí gbé lọ kúrò láàrín àwọn ọmọbìnrin ọba, àwọn tí ó kù díẹ̀ kí wọn pa. Wọn gbé òun àti olùtọ́jú rẹ̀ sínú ìyẹ̀wù. Nítorí Jehoṣeba ọmọbìnrin ọba Jehoramu àti ìyàwó àlùfáà Jehoiada jẹ́ arábìnrin Ahasiah. Ó fi ọmọ náà pamọ́ kúrò fún Ataliah, kí ó má ba à pa á.
Aka, o Iehosabeata ke kaikamahine a ke alii, lawe ae la oia ia Ioasa i ke keiki a Ahazia, aihue iho la ia ia maiwaena aku o ka poe keiki alii e pepehiia ana, a huna ia ia, a me ka mea nana ia i hanai iloko o kahi keena moe; pela i huna iho ai o Iehosabeata ke kaikamahine a ke alii a Iehorama ka wahine a Iehoiada ke kahuna, i ua mea la mai ke alo o Atalia, i ole ia e pepehi mai ia ia, no ka mea, o ke kaikuwahine ia no Ahazia.
12 Ó wà ní ìpamọ́ pẹ̀lú wọn ni ilé Ọlọ́run fún ọdún mẹ́fà nígbà tí Ataliah ṣàkóso ilẹ̀ náà.
Aia no ia i hunaia'i me ka poe iloko o ka hale o ke Akua i na makahiki eono; a noho alii iho la o Atalia maluna o ka aina.