< 2 Chronicles 22 >

1 Àwọn ènìyàn Jerusalẹmu mú Ahasiah, ọmọ Jehoramu tí ó kéré jùlọ, jẹ ọba ní ipò rẹ̀, láti ìgbà tí àwọn onísùnmọ̀mí, tí ó wá pẹ̀lú àwọn ará Arabia sínú ibùdó, tí wọn sì ti pa àwọn ọmọkùnrin àgbà. Bẹ́ẹ̀ ni Ahasiah ọmọ Jehoramu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba.
A: la: be fi dunu mogili da eno dunu Yuda fi doagala: musa: oule asili, hina bagade Yihoula: me egefe huluane medole legei. Be afae fawane hame medole legei, amo Yihoula: me ea ufi mano A: ihasaia. Amaiba: le, Yelusaleme fi dunu da Yihoula: me bagia, A:ihasaia hina bagade ilegei.
2 Ahasiah jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún kan. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Ataliah, ọmọ ọmọbìnrin Omri.
3 Ó mú ìrìn ní ọ̀nà ilé Ahabu. Nítorí tí ìyá rẹ̀ kì í láyà nínú ṣíṣe búburú.
E da lalelegele ode 22 agoane esalu, Yuda hina bagade hamoi. E da Yelusaleme moilai bai bagadega esala, ode afae fawane Yuda fi ouligilalu. Ea: me da A: dalaia (Isala: ili hina bagade A: iha: be idiwi amola Isala: ili hina bagade Omeli amo ea aowa). A: ihasaia ea ame da hina bagade A: iha: be idiwiba: le, e da A: iha: be ea sosogo fi defele, Hina Godema wadela: le hamoi. Bai A: dalaia amola Omeli da e wadela: i hou hamoma: ne, ema fada: i sia: ne i.
4 Ó ṣe búburú ní ojú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti ṣe, nítorí lẹ́yìn ikú baba a rẹ̀, wọ́n di olùgbani nímọ̀ràn rẹ̀ sí ṣíṣe rẹ̀.
E da Hina Godema wadela: le hamoi. Bai ea ada bogolalu, hina bagade A: iha: be ea fi dunu eno da ea fada: i sia: su dunu hamoi. Amola e da ilia fada: i sia: amoma fa: no bobegeiba: le, dafai dagoi.
5 Ó tẹ̀lé ìgbìmọ̀ wọn nígbà tí ó lọ pẹ̀lú Joramu ọmọ Ahabu ọba Israẹli láti gbógun ti Hasaeli ọba Aramu ní Ramoti Gileadi. Àwọn ará Aramu ṣá Joramu ní ọgbẹ́;
A: ihasaia da ilia fada: i sia: fa: no bobogeiba: le, e amola Isala: ili hina bagade Youla: me ela da gilisili, Silia hina bagade Ha: sa: ielema gegei. Ilia dadi gagui wa: i da La: imode moilai, Gilia: de soge ganodini, amogai migagadenene gegei. Youla: me da amogai gegenana, gala: i ba: i.
6 bẹ́ẹ̀ ni ó padà sí Jesreeli láti wo ọgbẹ́ rẹ̀ sàn tí wọ́n ti dá sí i lára ní Rama ní ojú ogun rẹ̀ pẹ̀lú Hasaeli ọba Siria. Nígbà náà, Ahasiah, ọmọ Jehoramu ọba Juda lọ sí Jesreeli láti lọ rí Joramu ọmọ Ahabu nítorí a ti ṣá a lọ́gbẹ́.
E da e gala: i fa: gi bahoma: ne, Yeseliele moilai bai bagadega buhagi. Amola A: ihasaia da amoga e ba: la asi.
7 Ní gbogbo ìgbà ìbẹ̀wò Ahasiah sí Joramu, Ọlọ́run mú ìṣubú Ahasiah wá. Nígbà tí Ahasiah dé, ó jáde lọ pẹ̀lú Jehoramu láti lọ bá Jehu ọmọ Nimṣi, ẹni tí Olúwa ti fi àmì òróró yàn láti pa ìdílé Ahabu run.
Gode da amo sofe mabe ganodini, A:ihasaia ea dafamu ilegei. A: ihasaia da amogawi esaloba, dunu ea dio amo Yihiu (Nimisiai egefe) da Youla: me doagala: i. Hina Gode da Yihiu amo A: iha: be ea wadela: i hina bagade fi gugunufinisimusa: ilegei dagoi.
8 Nígbà tí Jehu ń ṣe ìdájọ́ lórí ilé Ahabu, ó rí àwọn ọmọbìnrin ọba ti Juda àti àwọn ọmọkùnrin ìbátan Ahasi, tí ó ń tọ́jú Ahasiah, ó sì pa wọ́n.
Yihiu da Gode ema ilegei hawa: hamosu hamonanoba, e da Yuda fi ouligisu dunu amola A: ihasaia ea ayama mogili ba: i dagoi. Ilia da A: ihasaia sigi misi. Yihiu da ili huluane medole legei.
9 Ó lọ láti wá Ahasiah, àti àwọn ọkùnrin rẹ̀. Àwọn arákùnrin rẹ̀ ṣẹ́gun rẹ̀ nígbà tí ó sá pamọ́ ní Samaria. A gbé e wá sí ọ̀dọ̀ Jehu, a sì pa á. Wọ́n sin ín nítorí wọ́n wí pé, “Ọmọkùnrin Jehoṣafati ni, ẹni tí ó wá Olúwa pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹnìkan ní ilé Ahasiah tí ó lágbára láti gbé ìjọba náà dúró.
Yihiu ea fidisu dunu da A: ihasaia ea esalebe sogebi hogole, e Samelia soge ganodini wamoaligili esalebe ba: i. Ilia e Yihiuma hiouginana asili, amola e medole legei. Be ilia da ea da: i hodo ulidogonesi. Bai ilia da ea aowa Yihosiafa: de da hanaiwane Hina Gode Ea hawa: hamonanu, amo ilia bu dawa: i galu. A: ihasaia ea fi dunu afae amo Yuda fi ouligimu da hamedafa ba: i.
10 Nígbà tí Ataliah ìyá Ahasiah rí i wí pé ọmọkùnrin rẹ̀ ti kú, ó tẹ̀síwájú láti pa gbogbo ìdílé ọba ti ilẹ̀ Juda run.
Hina bagade A: ihasaia ea ame A: dalaia da egefe da medole legei nababeba: le, e da hina bagade ea sosogo fi dunu huluane medole legema: ne sia: si.
11 Ṣùgbọ́n Jehoṣeba ọmọbìnrin ọba Jehoramu mú Joaṣi, ọmọkùnrin Ahasiah ó sì jí gbé lọ kúrò láàrín àwọn ọmọbìnrin ọba, àwọn tí ó kù díẹ̀ kí wọn pa. Wọn gbé òun àti olùtọ́jú rẹ̀ sínú ìyẹ̀wù. Nítorí Jehoṣeba ọmọbìnrin ọba Jehoramu àti ìyàwó àlùfáà Jehoiada jẹ́ arábìnrin Ahasiah. Ó fi ọmọ náà pamọ́ kúrò fún Ataliah, kí ó má ba à pa á.
A: ihasaia egefe Youa: sie e fawane da hame medole legei ba: i. Ilia da e amola eno sosogo fi dunu fane legemusa: misini, ea awa Yihosiba (hina bagade Yihoula: me idiwi amola A: ihasaia ea dalusi) e da Youa: sie gei. E da Youa: sie amola ea ouligisu uda amo dia ahoasu sesei Debolo ganodini amoga oule asili, amola A: dalaia ea mae ba: ma: ne, ela wamolegei. Amalalu, ilia da Youa: sie hame medole legei.
12 Ó wà ní ìpamọ́ pẹ̀lú wọn ni ilé Ọlọ́run fún ọdún mẹ́fà nígbà tí Ataliah ṣàkóso ilẹ̀ náà.
Yihosiba da ode gafeyale agoanega Youa: sie ouligi. A: dalaia da Yuda fi ouligilaloba, Youa: sie da Debolo diasu ganodini wamoaligili esalebe ba: i, amola Yihosiba da e ouligi.

< 2 Chronicles 22 >