< 2 Chronicles 20 >

1 Lẹ́yìn èyí, àwọn ọmọ Moabu àti àwọn ọmọ Ammoni àti díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Mehuni wá láti gbé ogun ti Jehoṣafati.
Kalpasan daytoy, immay a makigubat kenni Jehosafat dagiti tattao ti Moab ken Ammon agraman dagiti kakaduada a Meunita.
2 Àwọn díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin wá láti sọ fún Jehoṣafati, “Àwọn ọ̀pọ̀ ọ̀wọ́ ogun ń bọ̀ wá bá ọ láti apá kejì Òkun láti Siria. Ó ti wà ní Hasason Tamari náà” (èyí tí í ṣe En-Gedi).
Ket adda sumagmamano a nangipadamag kenni Jehosafat, a kunada, “Adda dakkel a bunggoy nga um-umay manipud iti ballasiw ti Natay a Baybay, manipud Aram tapno umaydaka rauten. Adtoy, addadan idiay Hazazontamar” (dayta ket, Engedi).
3 Nípa ìró ìdágìrì, Jehoṣafati pinnu láti wádìí lọ́wọ́ Olúwa, ó sì kéde àwẹ̀ kíákíá fún gbogbo Juda.
Nagbuteng ni Jehosafat ket sipapasnek a binirokna ni Yahweh. Imbilinna ti panagayunar iti entero a Juda.
4 Àwọn ènìyàn Juda sì kó ara wọn jọ pọ̀ láti wá ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa; pẹ̀lúpẹ̀lú, wọ́n wá láti gbogbo ìlú ní Juda láti wá a.
Naguummong ti Juda tapno dawatenda ti pammagbaga ni Yahweh; immayda manipud kadagiti amin a siudad ti Juda tapno dawatenda ti pammagbaga ni Yahweh.
5 Nígbà náà Jehoṣafati dìde dúró níwájú àpéjọ Juda àti Jerusalẹmu ní ilé Olúwa níwájú àgbàlá tuntun.
Timmakder ni Jehosafat iti taripnong ti Juda ken Jerusalem, iti balay ni Yahweh, iti sangoanan ti baro a paraangan.
6 O sì wí pé, “Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wa, ìwọ kì ha ṣe Ọlọ́run tí ń bẹ ní ọ̀run? Ìwọ ń ṣe alákòóso lórí gbogbo ìjọba àwọn orílẹ̀-èdè. Agbára àti ipá ń bẹ ní ọwọ́ rẹ, kò sì sí ẹnìkan tí ó lè kò ọ́ lójú.
Kinunana, “O Yahweh a Dios dagiti kapuonanmi, saan kadi a sika ti Dios ti langit? Ken saan kadi a sika ti mangiturturay kadagiti amin a pagarian kadagiti nasion? Adda kadagita imam ti bileg ken pannakabalin, isu nga awan ti siasinoman a makabael a bumusor kenka.
7 Ìwọ ha kọ́ Ọlọ́run wa, tí o ti lé àwọn olùgbé ilẹ̀ yìí jáde níwájú àwọn ènìyàn Israẹli, tí o sì fi fún irú-ọmọ Abrahamu ọ̀rẹ́ rẹ láéláé?
O Diosmi, saan kadi a pinapanawmo dagiti agnanaed iti daytoy a daga iti sangoanan dagiti tattaom nga Israel, ket intedmo daytoy kadagiti kaputotan ni Abraham iti agnanayon?
8 Wọ́n ti ń gbé nínú rẹ̀ wọ́n sì ti kọ́ sínú rẹ ibi mímọ́ fún orúkọ rẹ wí pé,
Nagnaedda iti daytoy ket nangipatakderda iti nasantoan a lugar para iti naganmo, a kunada,
9 ‘Tí ibi bá wá sí orí wa, bóyá idà ìjìyà tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn àwọn yóò dúró níwájú rẹ níwájú ilé yìí tí ń jẹ́ orúkọ rẹ, àwa yóò sì sọkún jáde, ìwọ yóò sì gbọ́ wa. Ìwọ yóò sì gbà wá là?’
'No adda didigra nga umay kadakami-ti gubat, wenno sakit, wenno bisin-tumakderkami iti sangoanan daytoy a balay, ken iti sangoanam (ta ti naganmo ket adda iti daytoy a balay), ket umasogkami kenka iti panagrigatmi, ket denggennakami ket isalakannakami.'
10 “Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, àwọn ọkùnrin nìyí láti Ammoni, Moabu àti òkè Seiri, agbègbè ibi ti ìwọ kò ti gba àwọn ọmọ Israẹli láyè láti gbóguntì nígbà tí wọn wá láti Ejibiti, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n yípadà kúrò ní ọ̀dọ̀ wọn, wọn kò sì pa wọ́n run.
Kitaem ita, adda ditoy dagiti tattao ti Ammon, Moab, ken Bantay Seir, a saanmo nga impalubos a sakupen ti Israel, idi rimmuarda iti daga ti Egipto; ngem ketdi, naglikaw ti Israel ket saanda ida a dinadael.
11 Sì kíyèsi i, bí wọ́n ti san án padà fún wa; láti wá lé wa jáde kúrò nínú ìní rẹ, tí ìwọ ti fi fún wa láti ní.
Kitaem no kasano ti panangsupapakda kadakami; um-umayda a mangpapanaw kadakami iti dagam nga intedmo kadakami a tawidenmi.
12 Ọlọ́run wa, ṣé ìwọ kò ní ṣe ìdájọ́ fún wọn? Nítorí àwa kò ní agbára láti dojúkọ àwọn ọ̀pọ̀ ogun ńlá yìí tí ń bọ̀ wá kó wa. Àwa kò mọ̀ ohun tó yẹ ká ṣe, ṣùgbọ́n ojú wa wà ní ọ̀dọ̀ rẹ.”
O Diosmi, saanmo kadi nga ukomen ida? Ta awan bilegmi a mangsaranget iti daytoy a nakadakdakkel nga armada nga um-umay a mangraut kadakami.” Saanmi nga ammo ti aramidenmi, ngem dumawdawatkami iti tulongmo.”
13 Gbogbo àwọn ọkùnrin Juda, pẹ̀lú àwọn aya wọn àti ọmọ wọn àti àwọn kéékèèké, dúró níbẹ̀ níwájú Olúwa.
Nagtakder ti amin a Juda iti sangoanan ni Yahweh, a kadduada dagiti ubbingda, assawada, ken annakda.
14 Nígbà náà, ẹ̀mí Olúwa sì bà lé Jahasieli ọmọ Sekariah, ọmọ Benaiah, ọmọ Jeieli, ọmọ Mattaniah ọmọ Lefi àti ọmọ Asafu, gẹ́gẹ́ bí ó ṣe dìde dúró láàrín àpéjọ ènìyàn.
Ket iti tengnga ti taripnong, immay ti Espiritu ni Yahweh kenni Jahaziel a putot a lalaki ni Zacarias a putot a lalaki ni Benaias a putot a lalaki ni Jeiel a putot a lalaki ni Matanaias a Levita, maysa kadagiti putot a lalaki ni Asap.
15 Ó sì wí pé, “Ẹ tẹ́tí sílẹ̀, ọba Jehoṣafati àti gbogbo àwọn tí ń gbé ní Juda àti Jerusalẹmu! Èyí ní ohun tí Olúwa sọ wí pé kí a ṣe: ‘Ẹ má ṣe bẹ̀rù tàbí fòyà nítorí ọ̀pọ̀ ogun ńlá yìí. Nítorí ogun náà kì í ṣe tiyín, ṣùgbọ́n ti Ọlọ́run ni.
Kinuna ni Jahaziel, “Dumngegkayo, amin a Juda ken dakayo nga agnanaed iti Jerusalem, ken Ari a Jehosafat: “Kastoy ti kuna ni Yahweh kadakayo: 'Saankayo nga agbuteng; saankayo a maupay gapu iti daytoy a dakkel nga armada. Ta ti gubat ket saan a para kadakayo, ngem iti Dios.
16 Ní ọ̀la, ẹ sọ̀kalẹ̀ tọ̀ wọ́n lọ, wọn yóò gòkè pẹ̀lú, ẹ̀yin yóò sì rí wọn ní ìpẹ̀kun odò náà, níwájú aginjù Jerueli.
Sumalogkayo a mangsaranget kadakuada inton bigat. Kitaenyo, sumangsang-atda idiay bessang ti Ziz. Masarakanyo ida iti pungto ti tanap, sakbay iti let-ang ti Jeruel.
17 Ẹ̀yin kò ní láti bá ogun yìí jà. ẹ dúró ní ààyè yín; ẹ dúró jẹ́ẹ́ kí ẹ sì rí ìgbàlà Olúwa tí yóò fi fún yín, ìwọ Juda àti Jerusalẹmu. Ẹ má ṣe bẹ̀rù; ẹ má sì ṣe fòyà. Ẹ jáde lọ láti lọ dojúkọ wọ́n ní ọ̀la, Olúwa yóò sì wà pẹ̀lú yín.’”
Saanen a masapul a makirangetkayo iti daytoy a gubat. Agtalinaedkayo iti puestoyo, aguraykayo, ket kitaenyo ti panangispal ni Yahweh kadakayo, Juda ken Jerusalem. Saankayo nga agbuteng wenno maupay. Inkay makigubat kadakuada inton bigat, ta adda ni Yahweh kadakayo.”
18 Jehoṣafati tẹ orí rẹ̀ ba sílẹ̀ pẹ̀lú ojú rẹ̀, àti gbogbo àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu wólẹ̀ níwájú láti sin Olúwa.
Nagrukob ni Jehosafat iti daga. Nagrukob iti sangoanan ni Yahweh ti amin a Juda ken dagiti agnanaed iti Jerusalem, ket nagdaydayawda kenkuana.
19 Nígbà náà díẹ̀ lára àwọn ọmọ Lefi àti àwọn ọmọ Kohati àti àwọn ọmọ Kora sì dìde dúró wọ́n sì sin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, pẹ̀lú ohùn ariwo ńlá.
Timmakder dagiti Levita a kaputotan dagiti Koatitas ken Koreitas ket nagdaydayawda kenni Yahweh a Dios ti Israel iti nakapigpigsa a timek.
20 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù wọ́n jáde lọ sí aginjù Tekoa. Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ń jáde lọ, Jehoṣafati dìde dúró ó sì wí pé, “Ẹ gbọ́ mi, Juda àti ènìyàn Jerusalẹmu! Ẹ ní ìgbàgbọ́ nínú Olúwa Ọlọ́run yín ẹ̀yin yóò sì borí, ẹ ní ìgbàgbọ́ nínú àwọn wòlíì rẹ̀ ẹ̀yìn yóò sì ṣe rere.”
Bimmangonda a nasapa iti kabigatanna ket napanda iti let-ang ti Tekoa. Bayat a rumrummuarda, timmakder ni Jehosafat ket kinunana, “Dumngegkayo kaniak, Juda, ken dakayo nga agnanaed iti Jerusalem! Agtalekkayo kenni Yahweh a Diosyo, ket saranayennakayonto. Agtalekkayo kadagiti profetana, ket agballigikayonto.”
21 Lẹ́yìn ìgbà tí ó bá àwọn ènìyàn náà gbèrò tán, Jehoṣafati yàn wọ́n láti kọrin sí Olúwa àti láti fi ìyìn fún ẹwà ìwà mímọ́ gẹ́gẹ́ bí ó tì ń jáde lọ sí iwájú ogun ńlá náà, wí pé, “Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí àánú rẹ̀ dúró títí láéláé.”
Idi nakiuman isuna kadagiti tattao, dinutokanna dagiti agkanta kadagiti panangidaydayaw kenni Yahweh gapu iti nasantoan a dayagna, bayat a magmagnada iti sangoanan ti armada, kankantaenda, “Agyamankami kenni Yahweh; ta agnanayon ti kinapudnona iti tulagna.”
22 Bí wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí kọrin àti ìyìn, Olúwa rán ogun ẹ̀yìn sí àwọn ọkùnrin Ammoni àti Moabu àti òkè Seiri tí ó ń gbógun ti Juda, wọ́n sì kọlù wọ́n.
Idi rugianda ti agkanta ken agdayaw, pinagririnnanget ni Yahweh dagiti tattao ti Ammon, Moab ken Bantay Seir, nga um-umay a mangraut iti Juda. Naparmekda.
23 Àwọn ọkùnrin Ammoni àti Moabu dìde dúró sí àwọn ọkùnrin tí ń gbé òkè Seiri láti pa wọ́n run túútúú. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n sì ti pa àwọn ọkùnrin láti òkè Seiri, wọ́n sì ran ra wọn lọ́wọ́ láti pa ara wọn run.
Ta dagiti tattao ti Ammon ken Moab ket nakiranget kadagiti agnanaed iti Bantay Seir, tapno naan-anay a mapapatay ken madadaelda ida. Idi naparmekda dagiti tattao ti Bantay Seir, isudan ti nagraranget.
24 Nígbà tí àwọn ènìyàn Juda jáde sí ìhà ilé ìṣọ́ ní aginjù, wọn ń wo àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn, òkú nìkan ni wọ́n rí tí ó ṣubú sí ilẹ̀, kò sì sí ẹnìkan tí ó rí ààyè sá.
Idi nakadanon ti Juda iti lugar a matannawaganda ti let-ang, nakitada dagiti armada. Adtoy, nataydan, napasagda iti daga; awan iti nakalasat.
25 Bẹ́ẹ̀ ni Jehoṣafati àti àwọn ènìyàn rẹ̀ lọ láti kó ìkógun wọn, wọ́n sì rí lára wọn ọ̀pọ̀ iyebíye ọrọ̀ púpọ̀, ó sì ju èyí tí wọ́n lè kó lọ. Ọ̀pọ̀ ìkógun sì wà níbẹ̀, èyí tí ó gbà wọ́n ní ọjọ́ mẹ́ta láti gbà pọ̀.
Idi napan ni Jehosafat ken dagiti tattao tapno agsamsamda, nakasarakda kadagiti nakaad-adu a kinabaknang ken napapateg nga alahas, a sinamsamda para kadagiti bagbagida, ad-adu dagitoy ngem iti kabaelanda nga awiten. Tallo nga aldaw a binunagda dagiti samsam, nakaad-adu unay dagitoy.
26 Ní ọjọ́ kẹrin, wọn kó ara jọ pọ̀ ní àfonífojì ìbùkún, níbi tí wọ́n ti ń fi ìbùkún fún Olúwa. Ìdí nìyí tí wọ́n fi ń pe ibẹ̀ ní àfonífojì ìbùkún títí di òní.
Iti maika-uppat nga aldaw, naguummongda iti tanap ti Beraca. Indaydayawda sadiay ni Yahweh, isu a ti nagan dayta a lugar ket ti “tanap ti Beraca” agingga kadagitoy nga aldaw.
27 Nígbà náà wọ́n darí pẹ̀lú Jehoṣafati, gbogbo àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu padà pẹ̀lú ayọ̀ sí Jerusalẹmu, nítorí Olúwa ti fún wọn ní ìdí láti yọ̀ lórí àwọn ọ̀tá wọn.
Kalpasanna ket indauloan ida ni Jehosafat nga agsubli idiay Jerusalem nga addaan rag-o; ta pinagrag-o ida ni Yahweh kadagiti kabusorda.
28 Wọ́n sì wọ Jerusalẹmu, wọ́n sì lọ sí ilé Olúwa pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn àti dùùrù àti ìpè.
Simmangpetda idiay Jerusalem ket napanda iti balay ni Yahweh a nabuyogan iti uni dagiti lira, arpa ken trumpeta.
29 Ìbẹ̀rù Ọlọ́run wá si orí gbogbo ìjọba ilẹ̀ náà nígbà tí wọ́n gbọ́ bí Olúwa ti bá àwọn ọ̀tá Israẹli jà.
Nagbuteng iti Dios dagiti amin a pagarian kadagiti nasion idi nadamagda a nakiranget ni Yahweh kadagiti kabusor ti Israel.
30 Bẹ́ẹ̀ ni ìjọba Jehoṣafati sì wà ní àlàáfíà, nítorí Ọlọ́run rẹ̀ ti fún un ni ìsinmi ní gbogbo àyíká.
Natalna ngarud ti pagarian ni Jehosafat, ta inikkan ti Diosna isuna iti kappia iti aglawlawna.
31 Báyìí ni Jehoṣafati jẹ ọba lórí Juda. Ó sì jẹ́ ẹni ọdún márùndínlógójì. Nígbà tí ó di ọba Juda, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Asuba ọmọbìnrin Silihi.
Nagturay ni Jehosafat iti entero a Juda: agtawen isuna iti 35 idi nangrugi nga agturay, ket nagturay isuna idiay Jerusalem iti 25 a tawen. Azuba ti nagan ti inana, a putot a babai ni Silhi.
32 Ó sì rin ọ̀nà baba rẹ̀ Asa kò sì yà kúrò nínú rẹ̀, ó sì ṣe èyí tí ó tọ́ ní ojú Olúwa.
Sinurotna dagiti wagas ni Asa nga amana; saanna a tinallikudan dagitoy; inaramidna ti ummo iti imatang ni Yahweh.
33 Ní ibi gíga, pẹ̀lúpẹ̀lú, kò mu wọn kúrò, gbogbo àwọn ènìyàn náà kò sì fi ọkàn wọn fún Ọlọ́run àwọn baba wọn.
Nupay kasta, saan pay a naikkat dagiti lugar a pagdaydayawan, saan pay met a pimmasnek dagiti tattao iti panagdaydayawda iti Dios dagiti kapuonanda.
34 Ìyókù iṣẹ́ ìjọba Jehoṣafati, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin, ni a kọ sí inú ìwé ìtàn ti Jehu ọmọ Hanani, tí a kọ sí inú ìwé àwọn ọba Israẹli.
Dagiti dadduma a banbanag maipanggep kenni Jehosafat, manipud iti rugi agingga iti maudi, ket naisurat iti pakasaritaan ni Jehu a putot a lalaki ni Hanani, a nailanad iti Libro dagiti Ar-ari ti Israel.
35 Nígbà tí ó yá, Jehoṣafati ọba Juda da ara rẹ̀ pọ̀ pẹ̀lú Ahasiah, ọba Israẹli, ẹni tí ó jẹ̀bi ìwà búburú.
Kalpasan daytoy, nakitulag ni Jehosafat nga ari ti Juda kenni Ahazias nga ari ti Israel, nga adu a kinadakes ti inaramidna.
36 Ó sì gbà pẹ̀lú rẹ̀ láti kan ọkọ̀ láti lọ sí Tarṣiṣi, lẹ́yìn èyí wọ́n kan ọkọ̀ ní Esioni-Geberi.
Nakitulag isuna kenkuana nga agaramidda kadagiti barko nga aglayag iti taaw. Inaramidda dagiti barko idiay Eziongeber.
37 Elieseri ọmọ Dodafahu ti Meraṣa sọtẹ́lẹ̀ sí Jehoṣafati, wí pe, “Nítorí tí ìwọ ti da ara rẹ̀ pọ̀ mọ́ Ahasiah, Olúwa yóò pa ohun ti ìwọ ti ṣe run.” Àwọn ọkọ̀ náà sì fọ́, wọn kò sì le lọ sí ibi ìtajà.
Ket nangipadto ni Eliezer a putot a lalaki ni Dodavahu a taga-Maresias, iti maibusor kenni Jehosafat; kinunana, “Gapu ta nakitulagka kenni Ahazias, dinadael ni Yahweh dagiti inaramidyo.” Nadadael dagiti barko tapno saanda a makapaglayag.

< 2 Chronicles 20 >