< 2 Chronicles 20 >
1 Lẹ́yìn èyí, àwọn ọmọ Moabu àti àwọn ọmọ Ammoni àti díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Mehuni wá láti gbé ogun ti Jehoṣafati.
A hnukah tah Moab koca rhoek, Ammon koca neh amih taengkah Ammoni lamkah rhoek loh Jehoshaphat taengah caemtloek hamla pawk uh.
2 Àwọn díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin wá láti sọ fún Jehoṣafati, “Àwọn ọ̀pọ̀ ọ̀wọ́ ogun ń bọ̀ wá bá ọ láti apá kejì Òkun láti Siria. Ó ti wà ní Hasason Tamari náà” (èyí tí í ṣe En-Gedi).
Te dongah a pha uh neh Jehoshaphat taengla puen uh tih, “Nang taengah tuipuei rhalvangan lamkah, Aram lamkah hlangping muep ha pawk. Amih tah Engedi Hazezontamar ah om uh coeng ke,” a ti nah.
3 Nípa ìró ìdágìrì, Jehoṣafati pinnu láti wádìí lọ́wọ́ Olúwa, ó sì kéde àwẹ̀ kíákíá fún gbogbo Juda.
Tedae a rhih dongah BOEIPA te dawt hamla Jehoshaphat loh a maelhmai a hoi. Te phoeiah Judah pum hamla yaehnah hnin khaw a hoe pah.
4 Àwọn ènìyàn Juda sì kó ara wọn jọ pọ̀ láti wá ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa; pẹ̀lúpẹ̀lú, wọ́n wá láti gbogbo ìlú ní Juda láti wá a.
Te daengah BOEIPA lamkah te tlap hamla Judah rhoek coi uh thae tih Judah khopuei tom lamloh BOEIPA tlap hamla ha pawk.
5 Nígbà náà Jehoṣafati dìde dúró níwájú àpéjọ Juda àti Jerusalẹmu ní ilé Olúwa níwájú àgbàlá tuntun.
Jehoshaphat tah Jerusalem, BOEIPA im, vongup thai hmai kah Judah hlangping lakli ah pai.
6 O sì wí pé, “Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wa, ìwọ kì ha ṣe Ọlọ́run tí ń bẹ ní ọ̀run? Ìwọ ń ṣe alákòóso lórí gbogbo ìjọba àwọn orílẹ̀-èdè. Agbára àti ipá ń bẹ ní ọwọ́ rẹ, kò sì sí ẹnìkan tí ó lè kò ọ́ lójú.
Te vaengah, “A pa rhoek kah Pathen Yahweh, vaan kah Pathen khaw namah moenih a? Namah loh namtom ram boeih na taemrhai. Na kut ah thadueng neh thayung thamal om tih nang aka pai thil thai a om moenih.
7 Ìwọ ha kọ́ Ọlọ́run wa, tí o ti lé àwọn olùgbé ilẹ̀ yìí jáde níwájú àwọn ènìyàn Israẹli, tí o sì fi fún irú-ọmọ Abrahamu ọ̀rẹ́ rẹ láéláé?
Namah te kaimih kah Pathen moenih a? Khohmuen kah khosa rhoek he na pilnam Israel mikhmuh lamloh na haek tih na lungnah Abraham tiingan taengah kumhal duela na paek.
8 Wọ́n ti ń gbé nínú rẹ̀ wọ́n sì ti kọ́ sínú rẹ ibi mímọ́ fún orúkọ rẹ wí pé,
A khuiah kho a sak uh tih a khuiah namah ham neh na ming hamla rhokso a sak uh.
9 ‘Tí ibi bá wá sí orí wa, bóyá idà ìjìyà tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn àwọn yóò dúró níwájú rẹ níwájú ilé yìí tí ń jẹ́ orúkọ rẹ, àwa yóò sì sọkún jáde, ìwọ yóò sì gbọ́ wa. Ìwọ yóò sì gbà wá là?’
“Kaimih soah tholhphu yoethae cunghang, duektahaw, khokha a pai atah he im hmai ah ka pai uh tih, he im kah namah mikhmuh ah na ming neh ka pai uh ni. Kaimih kah citcai khuiah nang te kang khue uh vaengah na yaak vetih nan khang ni.
10 “Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, àwọn ọkùnrin nìyí láti Ammoni, Moabu àti òkè Seiri, agbègbè ibi ti ìwọ kò ti gba àwọn ọmọ Israẹli láyè láti gbóguntì nígbà tí wọn wá láti Ejibiti, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n yípadà kúrò ní ọ̀dọ̀ wọn, wọn kò sì pa wọ́n run.
Tedae Ammon koca, Moab neh Seir tlang ke ne. Egypt khohmuen lamloh na coe uh vaengah amih taengla kun ham Israel te na paek moenih. Amih taeng lamloh a nong uh dongah khaw amih te a mitmoeng uh moenih.
11 Sì kíyèsi i, bí wọ́n ti san án padà fún wa; láti wá lé wa jáde kúrò nínú ìní rẹ, tí ìwọ ti fi fún wa láti ní.
Te phoeiah amih loh kaimih haek ham neh kaimih taengah ha pawk hamla n'thuung uh coeng he. Te te na rho khui lamkah ni kaimih nan pang sak.
12 Ọlọ́run wa, ṣé ìwọ kò ní ṣe ìdájọ́ fún wọn? Nítorí àwa kò ní agbára láti dojúkọ àwọn ọ̀pọ̀ ogun ńlá yìí tí ń bọ̀ wá kó wa. Àwa kò mọ̀ ohun tó yẹ ká ṣe, ṣùgbọ́n ojú wa wà ní ọ̀dọ̀ rẹ.”
Kaimih kah Pathen aw, amih taengah lai na tloek mahpawt nim? Kaimih taengla aka pawk hlangping he yet mikhmuh ah kaimih he thadueng tal coeng. Kaimih loh metla ka saii uh ham ka ming pawt dae kaimih mik loh namah taengla hooi uh,” a ti.
13 Gbogbo àwọn ọkùnrin Juda, pẹ̀lú àwọn aya wọn àti ọmọ wọn àti àwọn kéékèèké, dúró níbẹ̀ níwájú Olúwa.
Te vaengah Judah boeih neh camoe rhoek khaw, a yuu rhoek khaw a ca rhoek khaw BOEIPA mikhmuh ah pai uh.
14 Nígbà náà, ẹ̀mí Olúwa sì bà lé Jahasieli ọmọ Sekariah, ọmọ Benaiah, ọmọ Jeieli, ọmọ Mattaniah ọmọ Lefi àti ọmọ Asafu, gẹ́gẹ́ bí ó ṣe dìde dúró láàrín àpéjọ ènìyàn.
Zekhariah capa Jahaziel, Benaiah capa, Jeiel capa, Asaph koca lamkah Levi Mattaniah capa khaw pai. BOEIPA mueihla tah hlangping lakli ah anih soah a om pah.
15 Ó sì wí pé, “Ẹ tẹ́tí sílẹ̀, ọba Jehoṣafati àti gbogbo àwọn tí ń gbé ní Juda àti Jerusalẹmu! Èyí ní ohun tí Olúwa sọ wí pé kí a ṣe: ‘Ẹ má ṣe bẹ̀rù tàbí fòyà nítorí ọ̀pọ̀ ogun ńlá yìí. Nítorí ogun náà kì í ṣe tiyín, ṣùgbọ́n ti Ọlọ́run ni.
Te dongah, “Judah boeih neh Jerusalem khosa rhoek neh manghai Jehoshaphat, hnatung uh lah. BOEIPA loh nangmih taengah he ni a. thui. Nangmih loh rhih uh boeh. Hlangping he yet mikhmuh ah rhihyawp uh boeh. Caemtloek he nangmih kah pawt tih Pathen hut ni.
16 Ní ọ̀la, ẹ sọ̀kalẹ̀ tọ̀ wọ́n lọ, wọn yóò gòkè pẹ̀lú, ẹ̀yin yóò sì rí wọn ní ìpẹ̀kun odò náà, níwájú aginjù Jerueli.
Thangvuen ah amih te suntlak thil uh, amih tah Ziz kham ah cet uh coeng ke. Amih te Jeruel khosoek hmai kah soklong bawt ah na hmuh uh bitni.
17 Ẹ̀yin kò ní láti bá ogun yìí jà. ẹ dúró ní ààyè yín; ẹ dúró jẹ́ẹ́ kí ẹ sì rí ìgbàlà Olúwa tí yóò fi fún yín, ìwọ Juda àti Jerusalẹmu. Ẹ má ṣe bẹ̀rù; ẹ má sì ṣe fòyà. Ẹ jáde lọ láti lọ dojúkọ wọ́n ní ọ̀la, Olúwa yóò sì wà pẹ̀lú yín.’”
Tahae kah vathoh ham he nangmih hut moenih, na pai cak sak uh lamtah nangmih ham BOEIPA kah khangnah te hmu uh. Judah neh Jerusalem aw rhih uh boeh rhihyawp uh boeh. Thangvuen ah amih mikhmuh la cet uh, nangmih taengah BOEIPA om,” a ti nah.
18 Jehoṣafati tẹ orí rẹ̀ ba sílẹ̀ pẹ̀lú ojú rẹ̀, àti gbogbo àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu wólẹ̀ níwájú láti sin Olúwa.
Jehoshaphat loh diklai la a maelhmai a buluk vaengah Judah pum neh Jerusalem kah khosa rhoek khaw BOEIPA te bawk hamla BOEIPA mikhmuh ah ba kop uh.
19 Nígbà náà díẹ̀ lára àwọn ọmọ Lefi àti àwọn ọmọ Kohati àti àwọn ọmọ Kora sì dìde dúró wọ́n sì sin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, pẹ̀lú ohùn ariwo ńlá.
Te phoeiah Kohathi koca lamkah Levi rhoek neh Korah koca lamkah khaw Israel Pathen BOEIPA taengah thangthen hamla thoo uh tih ol a len la a huel hang uh.
20 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù wọ́n jáde lọ sí aginjù Tekoa. Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ń jáde lọ, Jehoṣafati dìde dúró ó sì wí pé, “Ẹ gbọ́ mi, Juda àti ènìyàn Jerusalẹmu! Ẹ ní ìgbàgbọ́ nínú Olúwa Ọlọ́run yín ẹ̀yin yóò sì borí, ẹ ní ìgbàgbọ́ nínú àwọn wòlíì rẹ̀ ẹ̀yìn yóò sì ṣe rere.”
Te phoeiah mincang ah thoo uh tih Tekoa khosoek la pawk uh. Amih a hlah uh vaengah Jehoshaphat te pai tih, “Judah neh Jerusalem khosa rhoek kai ol he hnatun uh. Na Pathen BOEIPA te tangnah. A tonghma rhoek te uepom la tangnah lamtah thaihtak uh lah,” a ti.
21 Lẹ́yìn ìgbà tí ó bá àwọn ènìyàn náà gbèrò tán, Jehoṣafati yàn wọ́n láti kọrin sí Olúwa àti láti fi ìyìn fún ẹwà ìwà mímọ́ gẹ́gẹ́ bí ó tì ń jáde lọ sí iwájú ogun ńlá náà, wí pé, “Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí àánú rẹ̀ dúró títí láéláé.”
Pilnam a uen phoeiah tah BOEIPA te aka hlai la, hmuencim kah rhuepomnah te aka thangthen la, aka pumcum uh kah a hmai ah cet tih, “A sitlohnah kumhal ham dongah BOEIPA te uem uh,” aka ti la a khueh.
22 Bí wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí kọrin àti ìyìn, Olúwa rán ogun ẹ̀yìn sí àwọn ọkùnrin Ammoni àti Moabu àti òkè Seiri tí ó ń gbógun ti Juda, wọ́n sì kọlù wọ́n.
A tue te tamlung neh koehnah neh a tong uh. BOEIPA loh Moab kah Ammon koca rhoek neh Judah la aka pawk rhoek te Seir tlang ah rhongngol a khueh thil dongah yawk uh.
23 Àwọn ọkùnrin Ammoni àti Moabu dìde dúró sí àwọn ọkùnrin tí ń gbé òkè Seiri láti pa wọ́n run túútúú. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n sì ti pa àwọn ọkùnrin láti òkè Seiri, wọ́n sì ran ra wọn lọ́wọ́ láti pa ara wọn run.
Ammon koca rhoek neh Moab loh Seir tlang kah khosa rhoek te thup ham neh mitmoeng sak ham thoo uh. Seir khosa rhoek te a khah uh phoeiah tah hlang loh amah hui te kutcaihnah hamla bom uh thae.
24 Nígbà tí àwọn ènìyàn Juda jáde sí ìhà ilé ìṣọ́ ní aginjù, wọn ń wo àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn, òkú nìkan ni wọ́n rí tí ó ṣubú sí ilẹ̀, kò sì sí ẹnìkan tí ó rí ààyè sá.
Judah te khosoek kah rhaltoengim la pawk tih hlangping taengla mael. Tedae amih te diklai ah a rhok la tarha a yalh pah tih rhalyong om pawh.
25 Bẹ́ẹ̀ ni Jehoṣafati àti àwọn ènìyàn rẹ̀ lọ láti kó ìkógun wọn, wọ́n sì rí lára wọn ọ̀pọ̀ iyebíye ọrọ̀ púpọ̀, ó sì ju èyí tí wọ́n lè kó lọ. Ọ̀pọ̀ ìkógun sì wà níbẹ̀, èyí tí ó gbà wọ́n ní ọjọ́ mẹ́ta láti gbà pọ̀.
Te dongah Jehoshaphat neh a pilnam tah amih kah kutbuem te poelyoe hamla cet. Te vaengah amih taengah khuehtawn khaw rhok khaw, naikap hnopai khaw, a cungkuem la a hmuh uh tih hnophueih a tloel nah hil amamih ham a pit uh. Te te a yet dongah kutbuem a poelyoe uh te hnin thum koe uh.
26 Ní ọjọ́ kẹrin, wọn kó ara jọ pọ̀ ní àfonífojì ìbùkún, níbi tí wọ́n ti ń fi ìbùkún fún Olúwa. Ìdí nìyí tí wọ́n fi ń pe ibẹ̀ ní àfonífojì ìbùkún títí di òní.
A hnin li dongah tah Berakah kol ah tingtun uh tih BOEIPA te pahoi a uum uh. Te dongah te hmuen ming te tihnin hil Berakah kol la a khue uh.
27 Nígbà náà wọ́n darí pẹ̀lú Jehoṣafati, gbogbo àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu padà pẹ̀lú ayọ̀ sí Jerusalẹmu, nítorí Olúwa ti fún wọn ní ìdí láti yọ̀ lórí àwọn ọ̀tá wọn.
Te phoeiah Judah neh Jerusalem hlang boeih te mael uh. BOEIPA loh amih te a thunkha rhoek soah ko a hoe sak dongah Jehoshaphat tah amih hmai ah Jerusalem la kohoenah neh mael.
28 Wọ́n sì wọ Jerusalẹmu, wọ́n sì lọ sí ilé Olúwa pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn àti dùùrù àti ìpè.
Jerusalem la a kun vaengah thangpa neh, rhotoeng neh, olueng neh BOEIPA im la kunuh.
29 Ìbẹ̀rù Ọlọ́run wá si orí gbogbo ìjọba ilẹ̀ náà nígbà tí wọ́n gbọ́ bí Olúwa ti bá àwọn ọ̀tá Israẹli jà.
Israel kah thunkha taengah BOEIPA loh a vathoh thil te a yaak vaengah diklai ram boeih te Pathen taengah birhihnah om.
30 Bẹ́ẹ̀ ni ìjọba Jehoṣafati sì wà ní àlàáfíà, nítorí Ọlọ́run rẹ̀ ti fún un ni ìsinmi ní gbogbo àyíká.
Te dongah a Pathen loh anih te a kaepvai taengah a duem sak tih Jehoshaphat ram khaw mong.
31 Báyìí ni Jehoṣafati jẹ ọba lórí Juda. Ó sì jẹ́ ẹni ọdún márùndínlógójì. Nígbà tí ó di ọba Juda, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Asuba ọmọbìnrin Silihi.
Te dongah Jehoshaphat te sawmthum kum nga a lo ca vaengah Judah ah manghai coeng. A manghai vaengah Jerusalem ah kum kum kul neh kum nga manghai tih a manu ming tah Shilhi canu Azubah ni.
32 Ó sì rin ọ̀nà baba rẹ̀ Asa kò sì yà kúrò nínú rẹ̀, ó sì ṣe èyí tí ó tọ́ ní ojú Olúwa.
A napa Asa kah longpuei ah pongpa tih te lamkah te phael pawh. BOEIPA mikhmuh ah a thuem a saii.
33 Ní ibi gíga, pẹ̀lúpẹ̀lú, kò mu wọn kúrò, gbogbo àwọn ènìyàn náà kò sì fi ọkàn wọn fún Ọlọ́run àwọn baba wọn.
Tedae hmuensang te khoe uh pawh. Pilnam loh a thinko te a napa rhoek kah Pathen taengah a cikngae mueh la om pueng.
34 Ìyókù iṣẹ́ ìjọba Jehoṣafati, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin, ni a kọ sí inú ìwé ìtàn ti Jehu ọmọ Hanani, tí a kọ sí inú ìwé àwọn ọba Israẹli.
Jehoshaphat kah ol noi khaw a kung neh a dong khaw Hanani capa Jehu kah olka khuiah a daek uh coeng ke. Te te Israel manghai rhoek kah cabu khuiah khaw a hlum.
35 Nígbà tí ó yá, Jehoṣafati ọba Juda da ara rẹ̀ pọ̀ pẹ̀lú Ahasiah, ọba Israẹli, ẹni tí ó jẹ̀bi ìwà búburú.
Tedae a hnukah tah Judah manghai Jehoshaphat te Israel manghai Ahaziah neh cong uh rhoi tih a saii khaw poehlip.
36 Ó sì gbà pẹ̀lú rẹ̀ láti kan ọkọ̀ láti lọ sí Tarṣiṣi, lẹ́yìn èyí wọ́n kan ọkọ̀ ní Esioni-Geberi.
Te vaengah amah neh amah te sangpho sak ham neh Tarshish la caeh ham patai uh rhoi tih Eziongeber ah sangpho a saii rhoi.
37 Elieseri ọmọ Dodafahu ti Meraṣa sọtẹ́lẹ̀ sí Jehoṣafati, wí pe, “Nítorí tí ìwọ ti da ara rẹ̀ pọ̀ mọ́ Ahasiah, Olúwa yóò pa ohun ti ìwọ ti ṣe run.” Àwọn ọkọ̀ náà sì fọ́, wọn kò sì le lọ sí ibi ìtajà.
Te vaengah Mareshah lamkah Dodavahu capa Eliezer loh Jehoshaphat te a tonghma thil tih, “Ahaziah neh na patai uh rhoi dongah na bibi te BOEIPA loh a phae ni,” a ti nah. Te dongah sangpho te rhek tih Tarshish la caeh ham coeng rhoi voel pawh.