< 2 Chronicles 2 >

1 Solomoni pinnu láti kọ́ ilé fún orúkọ Olúwa àti ilé kan fún ìjọba rẹ̀
Hina bagade Soloumane da dunu ilia da Hina Godema nodone sia: ne gadoma: ne, Debolo Diasu gagumusa: ilegei. Amola hi amoga esaloma: ne, hi diasu gagumusa: ilegei.
2 Solomoni sì yan ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà àádọ́rin àwọn ọkùnrin láti ru ẹrù àti ọ̀kẹ́ mẹ́rin àwọn ọkùnrin gẹ́gẹ́ bi olùgé-òkúta ní àwọn òkè àti ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógójì gẹ́gẹ́ bí àwọn alábojútó lórí wọn.
Soloumane da 80,000 dunu enowane agolo sogega magufu damusu hawa: hamoma: ne asunasi. Amola dunu eno 70,000 agoane ilia da amo magufu damui gisima: ne asunasi. Amola ilia hawa: hamosu amo ouligima: ne, e da sesesu dunu 3,300 agoane asunasi.
3 Solomoni rán iṣẹ́ yìí sí Hiramu ọba Tire: “Rán àwọn igi kedari sí mi gẹ́gẹ́ bí o ti ṣe fún baba à mi Dafidi. Nígbà tí ó fi igi kedari ránṣẹ́ sí i láti kọ́ ààfin tí ó ń gbé.
Soloumane da Daia Soge hina bagade Haila: mema amane sia: si, “Di da na ada hina bagade Da: ibidima ea hina bagade diasu gaguma: ne, ema dolo ifa bidi lai. Wali, nama bidi lasu hamoma.
4 Nísinsin yìí, èmi n kọ́ ilé kan fún orúkọ Olúwa Ọlọ́run mi àti láti yà á sí mímọ́ fún un àti láti sun tùràrí olóòórùn dídùn níwájú rẹ̀, fún gbígbé àkàrà ìfihàn ìgbàkúgbà, àti fún ṣíṣe ẹbọ sísun ní gbogbo àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ àti ní ọjọọjọ́ ìsinmi àti oṣù tuntun àti ní àjọ̀dún tí a yàn ti Olúwa Ọlọ́run wa. Èyí ni àṣẹ fún Israẹli láéláé.
Wali na da na Hina Godema nodone sia: ne gadosu Debolo diasu gagumusa: ilegei dagoi Amo Debolo Diasu da hadigidafa diasu ba: mu. Amola amo ganodini, na amola na fi dunu da Ema nodomusa: , gabusiga: manoma gobele salimu, hadigi agi Ema imunu, amola hahabe, daeya, Sa: bade eso, Oubi Gaheabolo Lolo Nasu eso, amola eno Hina Godema nodone sia: ne gadosu eso huluane, amoha Wadela: i Hou Dabe Ima: ne gobele salasu hou hamomu.
5 “Ilé Olúwa tí èmi yóò kọ́ yóò tóbi, nítorí pé Ọlọ́run wa tóbi ju gbogbo àwọn ọlọ́run mìíràn lọ.
Na da Debolo Diasu noga: idafa gagumusa: ilegesa. Bai ninia Gode da bagadedafa. E da eno ‘gode’ liligi bagadewane baligisa.
6 Ṣùgbọ́n ta ni ó le è kọ́ ilé fún Olúwa, níwọ̀n ìgbà tí àwọn ọ̀run, àní ọ̀run àwọn ọ̀run tó ga jùlọ, kò le è gbà á? Ta ni èmi nígbà náà láti kọ́ ilé fún Olúwa, bí kò ṣe kìkì àti sun ẹbọ sun ẹbọ níwájú rẹ̀?
Be osobo bagade dunu da dafawane Godema debolo gagumu hamedei ba: sa. Bai E da bagadedafaba: le mu bagadedafa da Ema fonobahadi agoai ba: sa. Amaiba: le, na da E amo ganodini esaloma: ne, habodane Debolo Diasu gaguma: bela: ? Na gagumu liligi da Ema gabusiga: gobele salasu diasu fawane ba: mu gala.
7 “Nítorí náà, rán ọkùnrin kan sí mi, tí a kọ́ láti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú wúrà àti fàdákà àti idẹ àti irin, àti ní àwọ̀ àlùkò àti àwọ̀ pupa fòò àti ní àwọ̀ ojú ọ̀run, tí ó jẹ́ onímọ̀ nínú iṣẹ́ igi gbígbẹ́ láti ṣiṣẹ́ ní Juda àti Jerusalẹmu pẹ̀lú àwọn onímọ̀ oníṣọ̀nà tí baba à mi Dafidi pèsè.
Defea! Wali di dunu amo da gouli, silifa, balase, amola gula amoga dedesu hou noga: le dawa: , amola haisewe, oga: iyei, amola yoi abula amunasu hou noga: le dawa: - amo dunu nama asunasima. E amola Yuda amola Yelusaleme hawa: hamosu dunu amo na ada Da: ibidi ilegei, ilia da gilisili hawa: hamomu.
8 “Fi ìtì igi kedari, junifa àti algumu ránṣẹ́ sí mi, láti Lebanoni, nítorí tí mo mọ̀ pé àwọn ọkùnrin rẹ ní ìmọ̀ nínú gígé igi rírẹ́. Àwọn ọkùnrin mi yóò ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ọkùnrin rẹ.
Na dawa: Dia dunu ilia ifa abusa: su bagade dawa: Amaiba: le, dolo, saibalase amola yunibe ifa Lebanone sogega abusale, nama iasima. Na da na hawa: hamosu dunu, dia fi dunuma fidima: ne asunasimu.
9 Láti pèsè ọ̀pọ̀ igi rírẹ́ fún mi, nítorí ilé Olúwa tí mo kọ́ gbọdọ̀ tóbi kí o sì lógo púpọ̀.
Ninia da ifa bagohame momagela: di. Bai Debolo Diasu na gagumu ilegei da bagade amola noga: idafa ba: mu.
10 Èmi yóò fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ọkùnrin agégi tí ó ń gé ìtì igi náà ni ogún ẹgbẹ̀rún, alikama ilẹ̀ àti ogún ẹgbẹ̀rún, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ti barle; ogún ẹgbẹ̀rún, bati ọtí wáìnì àti ogún ẹgbẹ̀rún bati òróró olifi.”
Na da widi gala: ine 2,000 danese, bali gala: ine 2,000 ‘danese’ agoane, waini hano 400,000 lida agoane, amola olife susuligi noga: idafa 400,000 lida agoane, dia hawa: hamosu dunu ili moma: ne, dima iasimu.”
11 Hiramu ọba Tire fèsì padà nípasẹ̀ ìwé sí Solomoni: “Nítorí tí Olúwa fẹ́ràn àwọn ènìyàn rẹ̀, ó ti ṣe ọ́ ní ọba wọn.”
12 Hiramu fi kún un pe, “Ìyìn ni fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí ó dá ọ̀run òun ayé! O ti fún ọba Dafidi ní ọmọ tí ó gbọ́n, tí ó kún fún ìmọ̀ àti òye, tí yóò kọ́ ilé fún Olúwa àti ààfin fún ara rẹ̀.
Hina bagade Haila: me da Soloumanema meloa agoane dedene iasi, “Wali eso, Hina Gode, mu amola osobo bagade Hahamosu Dunu, Ema nodoma! Bai E da Da: ibidima bagade dawa: su mano i dagoi. Amola e da wali Hina Gode Ea Debolo Diasu amola hina bagade diasu gagumusa: ilegei dagoi.
13 “Èmi ń rán Huramu-Abi, ọkùnrin tí ó kún fún ìmọ̀ àti òye sí ọ.
Na da bagade dawa: su hawa: hamosu dunu ea dio amo Hiula: me, amo dima asunasimu.
14 Ọmọbìnrin kan nínú àwọn ọmọbìnrin Dani àti tí baba a rẹ̀ wá láti Tire tí ó gbọ́ngbọ́n àti ṣiṣẹ́ ní wúrà àti ní fàdákà, ní idẹ, ní irin, ní òkúta àti ní ìtì igi, ní èse-àlùkò, ní aláró, àti ní ọ̀gbọ̀ tí ó dára, àti òdòdó, láti gbẹ́ onírúurú ohun gbígbẹ́ pẹ̀lú, àti láti ṣe àwárí ìmọ̀ ẹ̀rọ irú ẹ̀yàkẹ́yà tí a ó fún un ṣe. Òun yóò ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ọlọ́gbọ́n rẹ̀, àti pẹ̀lú àwọn ọlọ́gbọ́n olúwa mi, Dafidi baba a rẹ.
Ea ame da Da: ne fi uda amola ea ada da Daia sogega esalu dunu. E da gouli, silifa, balase, amola gula amoga dedesu hou noga: le dawa: , amola haisewe, oga: iyei, amola yoi abula amunasu hou noga: le dawa: Dia da ema sia: sea, e da dia sia: i defele, amo liligiga hawa: hamomu. E amola dia medenegi hawa: hamosu dunu amo ilia dia ada Da: ibidi olelei, ilia gilisili hawa: hamomu da defea.
15 “Nísinsin yìí, jẹ́ kí olúwa mi rán àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ní alikama àti barle àti òróró Olifi náà àti ọtí tí ó ti ṣe ìlérí.
Amaiba: le, widi, bali, waini hano, amola olife susuligi, di ninima imunusa: ilegele sia: i liligi, amo ninima iasima.
16 Àwa yóò sì gé gbogbo àwọn ìtí igi láti Lebanoni tí ìwọ yóò lò pẹ̀lú a ó gbé wọn fò lójú omi òkun lọ sí Joppa. Lẹ́yìn náà ìwọ lè kó wọn gòkè lọ sí Jerusalẹmu.”
Ninia da Lebanone goumi sogeganini, dolo ifa dia hanai defele abusa: le, hano wayabo bagade amogudu hiougilala dafia: le, simi amunawene, amalu hanoba: le sua: sa sa: ili, hano bega: moilai Yoba amogawi doaga: mu. Amogawi, na dunu ilia da liligi simiga fadegale, dia dunu ilia da amo ifa Yelusalemega gaguli masunu.”
17 Solomoni ka iye àwọn àjèjì tí ó wà ní Israẹli lẹ́yìn kíka iye wọn tí baba a rẹ̀ Dafidi ti ṣe; a sì ka iye wọn sí ọ̀kẹ́ mẹ́jọ ó dín egbèjìlélọ́gbọ̀n.
Hina bagade Soloumane da ea ada Da: ibidi ea musa: hamoi defele, ga fi dunu Isala: ili soge ganodini esalu, amo ilia dio idili dedei. Ilia idi da 153,600 agoane.
18 Ó sì yan ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà àádọ́rin nínú wọn láti ru ẹrù, àti ọ̀kẹ́ mẹ́rin láti ṣe àgọ́ òkúta lórí òkè, àti egbèjìdínlógún alábojútó láti kó àwọn ènìyàn ṣiṣẹ́.
E da amo dunu mogili, hawa: hamosu ilima agoane ilegei: - E da dunu 70,000 agoane da ifa amola eno liligi gaguli masa: ne ilegei. E da dunu 80,000 agoane da agolo sogega, magufu damusu hawa: hamoma: ne ilegei. Amola ilia hawa: hamosu amo noga: le ouligima: ne, e da sesesu dunu 3,300 agoane ilegei.

< 2 Chronicles 2 >