< 2 Chronicles 19 >

1 Nígbà tí Jehoṣafati ọba Juda padà ní àlàáfíà sí ilé rẹ̀ ní Jerusalẹmu,
UJehoshafathi inkosi yakoJuda wathi esebuyela eJerusalema esigodlweni sakhe ephephile,
2 Jehu aríran, ọmọ Hanani jáde lọ láti lọ pàdé rẹ̀, ó sì wí fún ọba pé, “Ṣé ìwọ yóò máa ran ènìyàn búburú lọ́wọ́, kí o sì fẹ́ràn àwọn tí ó kórìíra Olúwa? Nítorí èyí, ìbínú Olúwa wà lórí wa.
uJehu umboni, indodana kaHanani, waphuma ukuba ayomhlangabeza wasesithi enkosini, “Kufanele yini ukuba uncedise ababi njalo uthande abamzondayo uThixo? Ngenxa yalokho, ulaka lukaThixo luphezu kwakho.
3 Bí ó ti wù kí ó rí, ohun rere wà nínú rẹ, nítorí tí ìwọ ti mú àwọn ilé àwọn ère òrìṣà Aṣerah kúrò, tí o sì múra ọkàn rẹ láti wá Ọlọ́run.”
Kodwa-ke kukhona okuhle ngawe, ngoba uziqedile elizweni lonke izinsika zikankulunkulukazi u-Ashera, inhliziyo yakho wayimisela ukudinga uNkulunkulu.”
4 Jehoṣafati sì ń gbé ní Jerusalẹmu ó sì jáde lọ padà láàrín àwọn ènìyàn láti Beerṣeba dé òkè ìlú Efraimu, ó sì mú wọn padà sọ́dọ̀ Olúwa Ọlọ́run baba wọn.
UJehoshafathi wayehlala eJerusalema, waphuma wahambela abantu kusukela eBherishebha kusiya elizweni lamaqaqa lako-Efrayimi wabaphendula ukuba bamkhonze uThixo, uNkulunkulu wabokhokho babo.
5 Ó sì yan àwọn onídàájọ́ sí ilẹ̀ náà, ní olúkúlùkù ìlú olódi Juda.
Wakhetha abehluleli elizweni, kuwo wonke amadolobho abiyelweyo akoJuda.
6 Ó sì wí fun wọ́n pé, “Ẹ kíyèsi ohun tí ẹ̀yin ń ṣe, nítorí ìwọ kò ṣe ìdájọ́ fun ènìyàn ṣùgbọ́n fún Olúwa, ẹni tí ó wà pẹ̀lú rẹ ní ìdájọ́.
Wabatshela wathi: “Linanzelele elikwenzayo, ngoba kalehluleli umuntu kodwa lehlulela uThixo, yena uzalisiza ekwahluleleni.
7 Nísinsin yìí jẹ́ kí ìbẹ̀rù Olúwa kí ó wá sí ọkàn rẹ̀. Ṣe ìdájọ́ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́, nítorí pẹ̀lú Olúwa Ọlọ́run kò sí àìṣedéédéé tàbí ojúsàájú tàbí gbígba àbẹ̀tẹ́lẹ̀.”
Ngakho mesabeni uThixo linanzelele elikwenzayo, yahlulelani ngonanzelelo ngoba kuThixo uNkulunkulu wethu kakukho ukwehlulela kubi loba ubandlululo loba ukufumbathisana.”
8 Ní Jerusalẹmu pẹ̀lú, Jehoṣafati yan díẹ̀ lára àwọn Lefi, àwọn àlùfáà àti àwọn olórí ìdílé Israẹli si pípa òfin Olúwa mọ́ àti láti ṣe ìdájọ́. Wọn sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Lakhona eJerusalema, uJehoshafathi wabeka abaLevi abathile labaphristi lezinhloko zezindlu zabako-Israyeli ukuba balawule umthetho kaThixo balamule lemibango. Babehlala eJerusalema.
9 Ó sì kìlọ̀ fún wọn wí pé. “Ìwọ gbọdọ̀ sìn pẹ̀lú òtítọ́ àti pẹ̀lú ọkàn pípé ní ìbẹ̀rù Olúwa.
Wabanika iziqondiso ezithi: “Kumele lethembeke ngokumesaba uThixo, ngobuqotho langenhliziyo nye epheleleyo.
10 Ní gbogbo ẹjọ́ tí ó bá wà níwájú rẹ láti ọ̀dọ̀ àwọn arákùnrin yín tí ń gbé ìlú wọn bóyá ẹ̀jẹ̀ tí ń sàn tàbí ìyókù òfin pẹ̀lú, pa á láṣẹ ìlànà àti ẹ̀tọ́, ìwọ gbọdọ̀ kìlọ̀ fún wọn láti má ṣe dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ìbínú yóò sì wá sórí yín, àti sórí àwọn arákùnrin. Ṣe èyí, ìwọ kì yóò sì jẹ̀bi.
Wonke amacala eza kini evela ezihlotsheni zenu kuwo wonke amadolobho elihlala kiwo loba kungamacala okuchitha igazi loba awokwephula umthetho, imilayo, izimiso loba iziqondiso, baxwayiseni ukuba bangoni kuThixo, funa ulaka lwakhe lwehlele phezu kwenu labafowenu. Lingenza lokho aliyikwenza isono.
11 “Amariah àlùfáà ni yóò jẹ́ olórí yín nínú gbogbo ọ̀ràn tí ó jẹ́ ti Olúwa, àti Sebadiah ọmọ Iṣmaeli alákòóso ìdílé Juda, ní yóò jẹ́ olórí ní gbogbo ọ̀rọ̀ tí ọba, àti àwọn ará Lefi pẹ̀lú yin yóò sìn gẹ́gẹ́ bí ìjòyè níwájú yín. Ẹ ṣe é pẹ̀lú ìmọ́kànle, Olúwa yóò sì wà pẹ̀lú àwọn tó bá ń ṣe rere.”
U-Amariya umphristi omkhulu nguye ozalikhangela emsebenzini wonke kaThixo, kuthi uZebhadiya indodana ka-Ishumayeli, umkhokheli wesizwe sakoJuda alikhokhele ezintweni eziqondane lenkosi, abaLevi labo bazakuba yizikhulu zenu. Yenzani ngesibindi, njalo sengathi uThixo angaba lalabo abazakwenza ngobuqotho.”

< 2 Chronicles 19 >