< 2 Chronicles 19 >
1 Nígbà tí Jehoṣafati ọba Juda padà ní àlàáfíà sí ilé rẹ̀ ní Jerusalẹmu,
Hina bagade Yihosiafa: de da se mae nabawane, ea Yelusaleme diasua hahawane buhagi.
2 Jehu aríran, ọmọ Hanani jáde lọ láti lọ pàdé rẹ̀, ó sì wí fún ọba pé, “Ṣé ìwọ yóò máa ran ènìyàn búburú lọ́wọ́, kí o sì fẹ́ràn àwọn tí ó kórìíra Olúwa? Nítorí èyí, ìbínú Olúwa wà lórí wa.
Balofede dunu ea dio amo Yihiu, da e ba: musa: asili, ema amane sia: i, “Di adi dawa: bela: ? Di da wadela: i hamosu dunu fidimu amola dunu amo da Hina Gode higasa, amo ilima gamu da defeala: ? Dia hamobeba: le, Hina Gode da dima ougisa.
3 Bí ó ti wù kí ó rí, ohun rere wà nínú rẹ, nítorí tí ìwọ ti mú àwọn ilé àwọn ère òrìṣà Aṣerah kúrò, tí o sì múra ọkàn rẹ láti wá Ọlọ́run.”
Be dia hou amo ganodini da fonobahadi noga: i hou gala. Bai di da uda ogogosu ‘gode’ Asila ema sia: ne gadoma: ne loboga hamoi liligi huluane gugunufinisi dagoi. Amola di da Gode Ea hanai hou amo fa: no bobogemusa: logo hogosu.”
4 Jehoṣafati sì ń gbé ní Jerusalẹmu ó sì jáde lọ padà láàrín àwọn ènìyàn láti Beerṣeba dé òkè ìlú Efraimu, ó sì mú wọn padà sọ́dọ̀ Olúwa Ọlọ́run baba wọn.
Yihosiafa: de da Yelusalemega esalu. Be e da eso bagohame amoga Yuda soge ganodini, ea fi dunu ba: musa: sofe ahoasu. Ea soge da ga (south) Biasiba moilai bai bagade asili Ifala: ime soge ga (north) gala. E da ea fi dunu ilia aowalalia Hina Godema bu sinidigima: ne ilima sia: i.
5 Ó sì yan àwọn onídàájọ́ sí ilẹ̀ náà, ní olúkúlùkù ìlú olódi Juda.
E da Yuda gagili sali moilai bai bagade afae afae amo ganodini fofada: su dunu ilegei.
6 Ó sì wí fun wọ́n pé, “Ẹ kíyèsi ohun tí ẹ̀yin ń ṣe, nítorí ìwọ kò ṣe ìdájọ́ fun ènìyàn ṣùgbọ́n fún Olúwa, ẹni tí ó wà pẹ̀lú rẹ ní ìdájọ́.
E da ilima amane hamoma: ne sia: i, “Dilia gebewane amola dawa: iwane fofada: su hou hamoma. Dilia da osobo bagade dunu ilegeiba: le, hame fofada: sa. Be dilia da Hina Gode Ea ilegeiba: le, fofada: sa. Amola dilia da fofada: sea, Hina Gode da dili esala.
7 Nísinsin yìí jẹ́ kí ìbẹ̀rù Olúwa kí ó wá sí ọkàn rẹ̀. Ṣe ìdájọ́ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́, nítorí pẹ̀lú Olúwa Ọlọ́run kò sí àìṣedéédéé tàbí ojúsàájú tàbí gbígba àbẹ̀tẹ́lẹ̀.”
Hina Godema nodoma amola dawa: iwane hamoma! Bai ninia Hina Gode da ogogosu hou amola hano suligi hou amola hina: fima baligili asigi hou, amo huluane Gode Ea higa: i hodosa.”
8 Ní Jerusalẹmu pẹ̀lú, Jehoṣafati yan díẹ̀ lára àwọn Lefi, àwọn àlùfáà àti àwọn olórí ìdílé Israẹli si pípa òfin Olúwa mọ́ àti láti ṣe ìdájọ́. Wọn sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Yihosiafa: de da Yelusaleme ganodini fofada: su hawa: hamoma: ne, Lifai fi dunu, gobele salasu dunu amola eno mimogo dunu, ilegei. Yuda dunu da Hina Gode Ea Sema wadela: beba: le o soge sia: ga gegeiba: le, amo dunu da fofada: su hou hamosu.
9 Ó sì kìlọ̀ fún wọn wí pé. “Ìwọ gbọdọ̀ sìn pẹ̀lú òtítọ́ àti pẹ̀lú ọkàn pípé ní ìbẹ̀rù Olúwa.
Yihosiafa: de da ilima amane hamoma: ne sia: i, “Dilia Hina Godema nodonewane hawa: hamoma. Dilia hawa: hamosu huluane amo ganodini, Ea hamoma: ne sia: i noga: le fa: no bobogema.
10 Ní gbogbo ẹjọ́ tí ó bá wà níwájú rẹ láti ọ̀dọ̀ àwọn arákùnrin yín tí ń gbé ìlú wọn bóyá ẹ̀jẹ̀ tí ń sàn tàbí ìyókù òfin pẹ̀lú, pa á láṣẹ ìlànà àti ẹ̀tọ́, ìwọ gbọdọ̀ kìlọ̀ fún wọn láti má ṣe dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ìbínú yóò sì wá sórí yín, àti sórí àwọn arákùnrin. Ṣe èyí, ìwọ kì yóò sì jẹ̀bi.
Dilia fi dunu da medole legesu hou o eno Gode Ea Sema giadofasu hou dilima fofada: musa: masea, ilia Hina Godema wadela: le hamosa: besa: le, ilia fofada: su ganodini hou noga: idafa hamoma: ne, ilima olelema. Dilia agoane hame hamosea, Hina Gode Ea ougidafa hou ba: mu. Be dilia hawa: dawa: iwane hamosea, se hame nabimu.
11 “Amariah àlùfáà ni yóò jẹ́ olórí yín nínú gbogbo ọ̀ràn tí ó jẹ́ ti Olúwa, àti Sebadiah ọmọ Iṣmaeli alákòóso ìdílé Juda, ní yóò jẹ́ olórí ní gbogbo ọ̀rọ̀ tí ọba, àti àwọn ará Lefi pẹ̀lú yin yóò sìn gẹ́gẹ́ bí ìjòyè níwájú yín. Ẹ ṣe é pẹ̀lú ìmọ́kànle, Olúwa yóò sì wà pẹ̀lú àwọn tó bá ń ṣe rere.”
Gobele salasu ouligisudafa, A:malaia da Godema sia: ne gadosu fofada: su amola Gode Ea Sema amoma fofada: su amo huluane ouligimu. Amola Yuda fi eagene ouligisudafa, Sebadaia (Isiama: iele egefe), e da dunudafa ilia osobo bagade fofada: su hou ouligimu. Amola Lifai fi dunu, da fofada: su ganodini sia: i liligi huluane didili hamoma: ne ouligimu. Mae beda: iwane, amo hamoma: ne sia: i liligi didili hamoma! Amola Hina Gode da moloidafa hou amoma gama: mu.”