< 2 Chronicles 16 >

1 Ní ọdún kẹrìndínlógójì ìjọba Asa, Baaṣa ọba Israẹli gòkè wá sí Juda ó sì kọlu Rama, láti ma bá a jẹ́ kí ẹnikẹ́ni lè jáde tàbí wọlé tọ Asa ọba Juda lọ.
Asa'ma 36si'a kafuma Juda vahe kinima nemanigeno'a, Israeli vahe kini ne' Basa'a Juda vahera hara eme huzmanteno, Rama kumate sondia vahe'amofo kumara eme kintege'za sondia vahe'mo'za mani'ne'za kegava hazageno, Juda kini ne' Asa mopafina mago vahe'mo'e huno ufrege, atiramigera osu'ne.
2 Nígbà náà ni Asa mú wúrà àti fàdákà jáde nínú ilé ìṣúra ilé Olúwa àti ààfin ọba ó sì ránṣẹ́ sí Beni-Hadadi ọba Siria, ẹni tí ń gbé ní Damasku, ó wí pé,
Ana'ma higeno'a Asa'a Ra Anumzamofo nompinti'ene agra nompintira goline mago'a silvanena erino Siria kini ne' Ben-Hadati'ma Damaskasima nemanirega atregeno nevigeno, amanage huno hu'ne,
3 “Májẹ̀mú kan wà láàrín èmi àti ìrẹ, bí ó ti wà láàrín baba mi àti baba rẹ. Ẹ wò ó, mo fi wúrà àti fàdákà ránṣẹ́ sí ọ; lọ, ba májẹ̀mú tí o bá Baaṣa ọba Israẹli dá jẹ́, kí ó lè lọ kúrò ní ọ̀dọ̀ mi.”
Amanahu nagesa nentahue, ko'ma nerfakema hu'na'aza huta mago trimpa huta maninu'a ke huvempa huta huhagerafinu'egu silvane golinena kagritega atregantogeno vie. Hagi vunka Israeli kini ne' Basa'enema huhagerafina'a nanekea ome vakanetregeno natreno vino.
4 Beni-Hadadi sì gbọ́ ti Asa ọba, ó sì rán àwọn olórí ogun rẹ̀ lọ sí àwọn ìlú Israẹli, wọ́n sì kọlu Ijoni, Dani, Abeli-Maimu, àti gbogbo ìlú ìṣúra Naftali.
Hagi Ben-Hadati'a Asa'ma hiankea nentahino, sondia vahe kva vahetami huzmantege'za Israeli rankumatmimpi vahetmina hara huzmante'za Ijoni rankuma'ma, Dani rankuma'ma, Abel-Maimi rankuma'enena e'nerino, ne'zama eritruma nehaza rankumatmima Naftali mopafima me'neana maka zamahe'za hanare'naze.
5 Nígbà tí Baaṣa gbọ́ èyí, ó sì dá kíkọ́ Rama dúró, ó sì dá iṣẹ́ rẹ̀ dúró.
Hagi ana nanekema Ba'asa'ma nentahino'a, Rama kuma'ma negia eri'zana atregeno anante me'ne.
6 Nígbà náà ní ọba Asa kó gbogbo àwọn ènìyàn Juda jọ, wọ́n sì kó òkúta àti igi Rama lọ èyí ti Baaṣa ń fi kọ́lé; ó sì fi kọ́ Geba àti Mispa.
Ana higeno kini ne' Asa'a maka Juda vahetaminku ke hige'za, Rama kuma'ma eri hanavetino kinaku'ma haveramine zafaraminema eri atruma hu'nea zantamina, eri'za vazageno ana havereti'ene zafareti Geba kuma'ene Mizpa kuma'enena eri hanavetino ki'ne.
7 Ní àkókò náà wòlíì Hanani wá sí ọ̀dọ̀ Asa ọba Juda, ó sì wí fún un pé, “Nítorí tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé ọba Siria, ìwọ kò sì gbẹ́kẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run rẹ, nítorí náà ni ogún ọba Siria ṣe bọ́ kúrò lọ́wọ́ rẹ.
Hagi ana kna zupa kasnampa ne' Hanani'a Juda kini ne' Asante eno amanage huno eme asmi'ne, Ra Anumzana kagri Anumzamofontera kamentintia osananki, atrenka Siria kini ne'mofonte kamentintia hankeno, Siria kini ne'mofo sondia vahe'mo'za katre'za fraze.
8 Àwa kì í ṣe ará Etiopia àti àwọn ará Libia àwọn alágbára ogun pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ kẹ̀kẹ́ àti àwọn ẹlẹ́ṣin? Síbẹ̀ nígbà tí ìwọ bá gbẹ́kẹ̀lé Olúwa yóò sì fi wọ́n lé ọwọ́ rẹ.
Hagi Itiopia vahe'ene Libia vahemo'zanena rama'a sondia vahe nezmante'za rama'a karisine hosifima mani'ne'zama ha'ma hu vahera rama'a zamante'naze. Hianagi kagra Ra Anumzamofonte kamentinti hu'nanku, Ra Anumzamo zamavare kazampina zamante'genka hara huzmagatere'nane.
9 Nítorí ojú Olúwa yí gbogbo ayé ká láti fi agbára fún àwọn ẹni tí ó ní ọkàn pípé sí i. Ìwọ ti ṣe ohun aṣiwèrè, láti ìsinsin yìí lọ, ìwọ yóò wà lójú ogun.”
Na'ankure Ra Anumzamo'a ama mopafina maka kaziga avua anteno omege emege nehuno, i'zano agu'amo'a knare huno Agrite'ma rutragote'nesia vahe zamaza nehuno zamazeri hanavetinaku tro huno mani'ne. Hagi kagra neginagi'za hananki'za, ha' vahe'mo'za hara eme huramante vava hu'za vugahaze.
10 Asa sì bínú pẹ̀lú sí wòlíì nítorí èyí, ó sì mú un bínú gidigidi tí ó sì fi mú un sínú túbú. Ní àkókò náà Asa sì ni díẹ̀ nínú àwọn ènìyàn náà lára.
Anage higeno Asa'a ana kasnampa nekura tusi rimpa ahenenteno, azerino kina nompi ante'ne. Na'ankure ana ke'arera tusi arimpa ahente'ne. Ana nehuno tusiza huno mago'a Juda vahetmina Asa'a zamazeri haviza hu'ne.
11 Àwọn iṣẹ́ ìjọba Asa, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin, ni akọ sínú ìwé ọba Juda àti Israẹli.
Hagi Asa'ma kinima mani'neno'ma hu'nea zantmimofo agenkea, agafama hu'nereti'ma vuno atumpare'ma uhanati'neana maka Juda kini vahe'ene Israeli kini vahetmimofo zamagenkema krenentaza avontafepi krente'naze.
12 Ní ọdún kọkàndínlógójì ìjọba rẹ̀, Asa sì ṣe àìsàn pẹ̀lú ààrùn nínú ẹsẹ̀ rẹ̀. Bi ó tilẹ̀ jẹ pé ààrùn rẹ̀ lágbára, síbẹ̀ kódà nínú àìsàn rẹ̀ kò wá ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa, ṣùgbọ́n lọ́dọ̀ àwọn oníṣègùn nìkan.
Hagi Asa'ma 39ni'a kafuma kinima nemanino'a, agafi kria efore higeno ana kri'amo'a ome ra hu'ne. Hagi ana krimo'ma ome rama nehigeno'a, Ra Anumzamofona antahigeno azahu zana e'orineanki, dota vahetegatike zmantahigeno azama hu zana eri'ne.
13 Nígbà náà tí ó pé ọdún kọ́kànlélógójì rẹ̀, Asa kú, ó sì sùn pẹ̀lú àwọn ìjọba baba rẹ̀,
Ana nehuno Asa'a 41ni'a kafu kinia maniteno frige'za afahe'ima asezmante'nazafi asente'naze.
14 wọ́n sì sin ín sínú isà òkú tí ó ti gbẹ́ jáde fún ara rẹ̀ ní ìlú Dafidi. Wọ́n sì tẹ sí orí àkéte tí ó fi òórùn dídùn kún, àti onírúurú tùràrí tí a fi ọgbọ́n pèsè, wọ́n sì da iná ńlá nítorí rẹ̀.
Hagi anama asemante'nazana agra'a hanagatinte'nea havegampi Deviti rankumapi Jerusalemi asente'naze. Hagi havegampina mnanentake'za atre'za eri mana nevu'za megi'a tusi teve hugre'za mani'neza zamasunkura hu'naze.

< 2 Chronicles 16 >