< 2 Chronicles 16 >
1 Ní ọdún kẹrìndínlógójì ìjọba Asa, Baaṣa ọba Israẹli gòkè wá sí Juda ó sì kọlu Rama, láti ma bá a jẹ́ kí ẹnikẹ́ni lè jáde tàbí wọlé tọ Asa ọba Juda lọ.
I KA makahiki kanakolukumamaono o ke aupuni o Asa, pii mai la o Baasa ke alii o ka Iseraela, e ku e i ka Iuda, a kukulu iho la oia ia Rama, me ka manao, aole e puka iwaho kekahi, aole e komo iloko kekahi io Asa la ke alii o ka Iuda.
2 Nígbà náà ni Asa mú wúrà àti fàdákà jáde nínú ilé ìṣúra ilé Olúwa àti ààfin ọba ó sì ránṣẹ́ sí Beni-Hadadi ọba Siria, ẹni tí ń gbé ní Damasku, ó wí pé,
Alaila lawe ae la o Asa i ke kala a me ke gula mai loko mai o ka waihona waiwai o ka hale o Iehova, a me ka hale o ke alii, a hoouna aku la oia io Bene-hadada la, i ke alii o Suria, i kona noho ana ma Damaseko, i aku la,
3 “Májẹ̀mú kan wà láàrín èmi àti ìrẹ, bí ó ti wà láàrín baba mi àti baba rẹ. Ẹ wò ó, mo fi wúrà àti fàdákà ránṣẹ́ sí ọ; lọ, ba májẹ̀mú tí o bá Baaṣa ọba Israẹli dá jẹ́, kí ó lè lọ kúrò ní ọ̀dọ̀ mi.”
He berita no mawaena o'u a me oe, a mawaena o ko'u makua, a me kou makua; eia hoi, ke hoouka aku nei au ia oe i ke kala a me ke gula, e hooki oe i kau berita me Baasa ke alii o ka Iseraela, i hele ia mai o'u aku nei.
4 Beni-Hadadi sì gbọ́ ti Asa ọba, ó sì rán àwọn olórí ogun rẹ̀ lọ sí àwọn ìlú Israẹli, wọ́n sì kọlu Ijoni, Dani, Abeli-Maimu, àti gbogbo ìlú ìṣúra Naftali.
A hoolohe o Bene-hadada i ka Asa, ka ke alii, a hoouna mai la oia i na luna o na koa ona e ku e i na kulanakauhalo o ka Iseraela; a Iuku iho la lakou ia Iiona, a me Dana, a me Abelamaima, a me na kulanakauhale waiho ukana a pau o Napetali.
5 Nígbà tí Baaṣa gbọ́ èyí, ó sì dá kíkọ́ Rama dúró, ó sì dá iṣẹ́ rẹ̀ dúró.
A lohe iho la o Baasa, haalele ia i kona kukulu ana ia Rama, a hooki iho la ia i kana hana.
6 Nígbà náà ní ọba Asa kó gbogbo àwọn ènìyàn Juda jọ, wọ́n sì kó òkúta àti igi Rama lọ èyí ti Baaṣa ń fi kọ́lé; ó sì fi kọ́ Geba àti Mispa.
Alakai ae la o Asa i ka Inda a pau, halihali mai la lakou i na pohaku o Rama, a me na laau olaila, i ka mea a Baasa i kukulu ai; a kukulu iho la oia me ia mau mea ia Geba a me Mizepa.
7 Ní àkókò náà wòlíì Hanani wá sí ọ̀dọ̀ Asa ọba Juda, ó sì wí fún un pé, “Nítorí tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé ọba Siria, ìwọ kò sì gbẹ́kẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run rẹ, nítorí náà ni ogún ọba Siria ṣe bọ́ kúrò lọ́wọ́ rẹ.
Ia manawa, hele mai la o Hanani ke kaula io Asa la, i ke alii o ka Iuda, olelo mai la ia ia, No kou hilinai ana i ke alii o Suria, aole hoi i hilinai ia Iehova i kou Akua, no ia mea, e pakele ka poe koa o ke alii o Suria mai kou lima aku.
8 Àwa kì í ṣe ará Etiopia àti àwọn ará Libia àwọn alágbára ogun pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ kẹ̀kẹ́ àti àwọn ẹlẹ́ṣin? Síbẹ̀ nígbà tí ìwọ bá gbẹ́kẹ̀lé Olúwa yóò sì fi wọ́n lé ọwọ́ rẹ.
O ko Aitiopa a me ka Luba, aole anei he nui loa lakou me na hale kaa, a me na holohololio he lehulehu? Aka, i kou hilinai ana ia Iehova, haawi mai oia ia lakou iloko o kou lima.
9 Nítorí ojú Olúwa yí gbogbo ayé ká láti fi agbára fún àwọn ẹni tí ó ní ọkàn pípé sí i. Ìwọ ti ṣe ohun aṣiwèrè, láti ìsinsin yìí lọ, ìwọ yóò wà lójú ogun.”
No ka mea, e holoholo ana na maka o Iehova ma ka honua a pau e hoike ana i kona mau a i ka poe i pono ia ia ko lakou naau: ua hana naaupo oe i keia mea; a ma keia hope aku e kauaia ana oe.
10 Asa sì bínú pẹ̀lú sí wòlíì nítorí èyí, ó sì mú un bínú gidigidi tí ó sì fi mú un sínú túbú. Ní àkókò náà Asa sì ni díẹ̀ nínú àwọn ènìyàn náà lára.
Alaila, huhu o Asa i ke kaula, a hoolei oia ia ia iloko o ka hale paahao; no ka mea, ua wela kona huhu ia ia no keia mea: a ia manawa hoi hookaumaha o Asa i kekahi poe kanaka.
11 Àwọn iṣẹ́ ìjọba Asa, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin, ni akọ sínú ìwé ọba Juda àti Israẹli.
Aia hoi, o na mea a Asa i hana'i, ka mua, a me ka hope, ua kakauia ia mau mea iloko o ka palapala o na'lii o ka luda a me ka Iseraela.
12 Ní ọdún kọkàndínlógójì ìjọba rẹ̀, Asa sì ṣe àìsàn pẹ̀lú ààrùn nínú ẹsẹ̀ rẹ̀. Bi ó tilẹ̀ jẹ pé ààrùn rẹ̀ lágbára, síbẹ̀ kódà nínú àìsàn rẹ̀ kò wá ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa, ṣùgbọ́n lọ́dọ̀ àwọn oníṣègùn nìkan.
A i ka makahiki kanakolukumamaiwa o kona aupuni, loaa iho la ia Asa ka mai ma kona mau wawae, a pii iluna kona mai; a i kona wa mai, aole ia i imi ia Iehova, aka, i ka poe kahuna lapaau.
13 Nígbà náà tí ó pé ọdún kọ́kànlélógójì rẹ̀, Asa kú, ó sì sùn pẹ̀lú àwọn ìjọba baba rẹ̀,
A hiamoe iho la o Asa me kona poe kupuna, a make ia i ka makahiki kanahakumamakahi o kona noho alii ana.
14 wọ́n sì sin ín sínú isà òkú tí ó ti gbẹ́ jáde fún ara rẹ̀ ní ìlú Dafidi. Wọ́n sì tẹ sí orí àkéte tí ó fi òórùn dídùn kún, àti onírúurú tùràrí tí a fi ọgbọ́n pèsè, wọ́n sì da iná ńlá nítorí rẹ̀.
A kanu lakou ia ia iloko o kona lua kahi ana i eli ai nona iho, ma ke kulanakauhale o Davida, a waiho lakou ia ia iloko o kona wahi moe, kahi i piha ai i na mea ala, a me na mea miko i hoomakaukauia ma ke akamai o na kahuna lapaau, a pupuhi aku lakou i ke ahi nona a nui loa.