< 2 Chronicles 16 >
1 Ní ọdún kẹrìndínlógójì ìjọba Asa, Baaṣa ọba Israẹli gòkè wá sí Juda ó sì kọlu Rama, láti ma bá a jẹ́ kí ẹnikẹ́ni lè jáde tàbí wọlé tọ Asa ọba Juda lọ.
Na rĩrĩ, mwaka wa mĩrongo ĩtatũ na ĩtandatũ wa wathani wa Asa, Baasha mũthamaki wa Isiraeli nĩambatire akarũe na Juda, na akĩirigĩra Rama na rũthingo rwa hinya nĩguo arigĩrĩrie gũtikagĩe mũndũ ũkuuma kana atoonye bũrũri wa Asa mũthamaki wa Juda.
2 Nígbà náà ni Asa mú wúrà àti fàdákà jáde nínú ilé ìṣúra ilé Olúwa àti ààfin ọba ó sì ránṣẹ́ sí Beni-Hadadi ọba Siria, ẹni tí ń gbé ní Damasku, ó wí pé,
Nake Asa akĩoya betha na thahabu kuuma igĩĩna-inĩ cia hekarũ ya Jehova o na kuuma nyũmba-inĩ yake ya ũthamaki, na agĩcitũmĩra Beni-Hadadi mũthamaki wa Suriata ũrĩa wathamakaga Dameski.
3 “Májẹ̀mú kan wà láàrín èmi àti ìrẹ, bí ó ti wà láàrín baba mi àti baba rẹ. Ẹ wò ó, mo fi wúrà àti fàdákà ránṣẹ́ sí ọ; lọ, ba májẹ̀mú tí o bá Baaṣa ọba Israẹli dá jẹ́, kí ó lè lọ kúrò ní ọ̀dọ̀ mi.”
Akĩmwĩra atĩrĩ, “Reke hakorwo harĩ na kĩrĩĩko giitũ nawe o ta ũrĩa haarĩ kĩrĩĩko gatagatĩ ka baba na thoguo. Ta kĩone, nĩndagũtũmĩra betha na thahabu. Rĩu tharia kĩrĩĩko kĩanyu na Baasha, mũthamaki wa Isiraeli nĩguo atigane na niĩ.”
4 Beni-Hadadi sì gbọ́ ti Asa ọba, ó sì rán àwọn olórí ogun rẹ̀ lọ sí àwọn ìlú Israẹli, wọ́n sì kọlu Ijoni, Dani, Abeli-Maimu, àti gbogbo ìlú ìṣúra Naftali.
Beni-Hadadi agĩĩtĩkĩra ũhoro wa Mũthamaki Asa, agĩtũma anene a ikundi cia thigari ciake makahũũre matũũra ma Isiraeli. Nao magĩtooria Ijoni, na Dani, na Abeli-Maimu, na matũũra manene mothe marĩa maarĩ makũmbĩ ma kũu Nafitali.
5 Nígbà tí Baaṣa gbọ́ èyí, ó sì dá kíkọ́ Rama dúró, ó sì dá iṣẹ́ rẹ̀ dúró.
Hĩndĩ ĩrĩa Baasha aiguire ũhoro ũcio, agĩtiga gwaka Rama na agĩtiganĩria wĩra wake.
6 Nígbà náà ní ọba Asa kó gbogbo àwọn ènìyàn Juda jọ, wọ́n sì kó òkúta àti igi Rama lọ èyí ti Baaṣa ń fi kọ́lé; ó sì fi kọ́ Geba àti Mispa.
Ningĩ Mũthamaki Asa akĩrehe andũ othe a Juda, nao magĩkuua mahiga na mbaũ kuuma Rama iria Baasha aatũmagĩra gwaka. Indo icio nĩcio Asa aatũmĩrire gwaka Geba na Mizipa.
7 Ní àkókò náà wòlíì Hanani wá sí ọ̀dọ̀ Asa ọba Juda, ó sì wí fún un pé, “Nítorí tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé ọba Siria, ìwọ kò sì gbẹ́kẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run rẹ, nítorí náà ni ogún ọba Siria ṣe bọ́ kúrò lọ́wọ́ rẹ.
Hĩndĩ ĩyo Hanani ũrĩa muoni-maũndũ agĩũka kũrĩ Asa mũthamaki wa Juda, akĩmwĩra atĩrĩ, “Tondũ nĩwehokire mũthamaki wa Suriata ũkĩaga kwĩhoka Jehova Ngai waku, mbũtũ cia ita cia mũthamaki wa Suriata nĩciũrĩte ikoima moko-inĩ maku.
8 Àwa kì í ṣe ará Etiopia àti àwọn ará Libia àwọn alágbára ogun pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ kẹ̀kẹ́ àti àwọn ẹlẹ́ṣin? Síbẹ̀ nígbà tí ìwọ bá gbẹ́kẹ̀lé Olúwa yóò sì fi wọ́n lé ọwọ́ rẹ.
Githĩ Akushi na Alubi, matiarĩ mbũtũ nene ya ita, na makagĩa na ngaari cia ita nyingĩ na andũ arĩa maathiiaga mahaicĩte mbarathi? No rĩrĩ, rĩrĩa wehokire Jehova, nĩamaneanire moko-inĩ maku.
9 Nítorí ojú Olúwa yí gbogbo ayé ká láti fi agbára fún àwọn ẹni tí ó ní ọkàn pípé sí i. Ìwọ ti ṣe ohun aṣiwèrè, láti ìsinsin yìí lọ, ìwọ yóò wà lójú ogun.”
Nĩgũkorwo maitho ma Jehova morũũraga thĩ yothe gwĩkĩra hinya arĩa maheanĩte ngoro ciao biũ kũrĩ we. Nĩwĩkĩte ũndũ wa ũrimũ, na kuuma rĩu nĩũgũcooka kũgĩa na mbaara.”
10 Asa sì bínú pẹ̀lú sí wòlíì nítorí èyí, ó sì mú un bínú gidigidi tí ó sì fi mú un sínú túbú. Ní àkókò náà Asa sì ni díẹ̀ nínú àwọn ènìyàn náà lára.
Asa akĩrakarĩra Hanani ũrĩa muoni-maũndũ nĩ ũndũ wa ũhoro ũcio; akĩmũrakarĩra mũno o nginya akĩmũikia njeera. O hĩndĩ ĩyo, Asa akĩambĩrĩria kũhinyĩrĩria andũ amwe atarĩ na tha.
11 Àwọn iṣẹ́ ìjọba Asa, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin, ni akọ sínú ìwé ọba Juda àti Israẹli.
Maũndũ ma wathani wa Asa kuuma kĩambĩrĩria nginya mũthia, nĩmandĩkĩtwo mbuku-inĩ ya athamaki a Juda na Isiraeli.
12 Ní ọdún kọkàndínlógójì ìjọba rẹ̀, Asa sì ṣe àìsàn pẹ̀lú ààrùn nínú ẹsẹ̀ rẹ̀. Bi ó tilẹ̀ jẹ pé ààrùn rẹ̀ lágbára, síbẹ̀ kódà nínú àìsàn rẹ̀ kò wá ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa, ṣùgbọ́n lọ́dọ̀ àwọn oníṣègùn nìkan.
Mwaka wa mĩrongo ĩtatũ na kenda wa wathani wake, Asa nĩarũarire magũrũ. O na gũtuĩka mũrimũ ũcio nĩwamũhatĩrĩirie mũno, o na ndwari-inĩ yake-rĩ, ndaigana kũmaatha ũteithio kuuma kũrĩ Jehova, no aacaririe ũteithio kuuma kũrĩ mandagĩtarĩ.
13 Nígbà náà tí ó pé ọdún kọ́kànlélógójì rẹ̀, Asa kú, ó sì sùn pẹ̀lú àwọn ìjọba baba rẹ̀,
Na mwaka wa mĩrongo ĩna na ũmwe wa wathani wake, Asa agĩkua na akĩhurũka hamwe na maithe make.
14 wọ́n sì sin ín sínú isà òkú tí ó ti gbẹ́ jáde fún ara rẹ̀ ní ìlú Dafidi. Wọ́n sì tẹ sí orí àkéte tí ó fi òórùn dídùn kún, àti onírúurú tùràrí tí a fi ọgbọ́n pèsè, wọ́n sì da iná ńlá nítorí rẹ̀.
Nao makĩmũthika mbĩrĩra-inĩ ĩrĩa eethondekeire o kũu Itũũra inene rĩa Daudi, makĩmũigĩrĩra gĩtanda-inĩ gĩa kũmũtwara mbĩrĩra kĩhumbĩrĩtwo na mahuti manungi wega na maguta mĩtukanio mĩingĩ marĩa manungi wega, nao magĩakia mwaki mũnene nĩ ũndũ wa kũmũtĩĩa.