< 2 Chronicles 15 >

1 Ẹ̀mí Ọlọ́run wá sórí Asariah ọmọ Odedi.
Cathut e Muitha teh Oded capa Azariah koe a pha teh,
2 Ó jáde lọ bá Asa, ó sì wí fún un pé, “Tẹ́tí si mi Asa, àti gbogbo Juda àti Benjamini. Olúwa wà pẹ̀lú rẹ, nígbà tí ìwọ bá wà pẹ̀lú rẹ̀. Ti ìwọ bá wá a, ìwọ yóò rí i ní ẹ̀bá ọ̀dọ̀ rẹ ṣùgbọ́n tí ìwọ bá kọ̀ ọ́ sílẹ̀, òun yóò kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
Asa dawn hanelah a cei teh, ahni koevah, Asa Judahnaw abuemlah hoi Benjaminnaw ka lawk thai awh haw. BAWIPA na kampangkhai awh pawiteh, ahni ni na kampangkhai van han. Ahni na tawng awh pawiteh na hmu awh han. Ahni na pahnawt awh pawiteh, na pahnawt awh van han.
3 Fún ọjọ́ pípẹ́ ni Israẹli ti wà láì sin Ọlọ́run òtítọ́, àti láìní àlùfáà ti ń kọ́ ni, àti láìní òfin.
Tueng moikasawlah Cathut katang tawn awh hoeh. Vaihmanaw cangkhainae hoi kâlawk tawn laipalah ao awh.
4 Ṣùgbọ́n nínú ìpọ́njú wọn, wọ́n yí padà si Olúwa Ọlọ́run Israẹli, wọ́n sì wa kiri. Wọ́n sì ri i ní ẹ̀gbẹ́ wọn.
Rucatnae a kâhmo awh toteh, BAWIPA Isarel Cathut koelah bout a ban awh. A tawng awh teh bout a hmu awh.
5 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ó léwu kí ènìyàn máa rìn ìrìnàjò kiri, nítorí tí gbogbo àwọn olùgbé ilẹ̀ náà wà nínú làálàá ńlá.
Hatnae tueng dawk kâennae hoi tâconae dawk roumnae awm hoeh. Ram thung kho ka sak e pueng koe lungpuen tâsuenae hoi doeh a kawi.
6 Orílẹ̀-èdè kan ń run èkejì àti ìlú kan sí òmíràn nítorí Ọlọ́run ń yọ wọ́n lẹ́nu pẹ̀lú oríṣìíríṣìí ìpọ́njú.
Ram buet touh hoi buet touh kho buet touh hoi buet touh a kâ raphoe awh. Bangkongtetpawiteh, Cathut ni runae phunkuep hoi tarannaw kut dawk a kâhmo sak.
7 Ṣùgbọ́n fun ìwọ, jẹ́ alágbára, kí ó má sì ṣe ṣàárẹ̀. Nítorí tí a ó fi èrè sí iṣẹ́ ẹ̀ rẹ.”
Hatei, nangmouh teh tha kâlat awh nateh na kut hno awh hanh. Na sak awh e patetlah tawkphu na hmu awh han telah atipouh.
8 Nígbà tí Asa gbọ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí àti àsọtẹ́lẹ̀ Asariah ọmọ Odedi wòlíì, ó mú àyà rẹ̀ le. Ó sì mú gbogbo ohun ìríra kúrò ní gbogbo ilẹ̀ Juda àti Benjamini àti kúrò nínú àwọn ìlú tí ó ti fi agbára mú ní orí òkè Efraimu. Ó tún pẹpẹ Olúwa ṣe tí ó wà ní iwájú portiko ti ilé Olúwa.
Asa ni hote lawk hoi profet Oded e sutdeilawk a thai navah, taran bout ahawi teh, Judah ram hoi Benjamin ram pueng Ephraim mon dawk e a la e khonaw e panuetthopounge naw pueng koung a tâkhawng teh, BAWIPA e im hmalah kaawm e BAWIPA thuengnae khoungroe bout a pathoup.
9 Nígbà náà, ó pe gbogbo Juda àti Benjamini jọ àti àwọn ènìyàn láti Efraimu, Manase àti Simeoni tí ó ti ṣe àtìpó ní àárín wọn. Nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn ti wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ láti Israẹli nígbà tí wọ́n rí i wí pé Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ wà pẹ̀lú rẹ̀.
Hahoi Judah ram hoi Benjamin ram thung e tami pueng ahni koe kho ka sak e Ephraim, Manasseh hoi Simeon ram thung e tami pueng koung a kaw. Bangkongtetpawiteh, BAWIPA Cathut ahni koelah ao e a hmu navah Isarel ram thung e tami moikapap ahni koe a tho awh.
10 Wọ́n péjọ sí Jerusalẹmu ní oṣù kẹta ọdún kẹ́ẹ̀dógún ti ìjọba Asa.
Hottelah Asa ni a uknae kum 15, thapa yung pâthum navah Jerusalem kho dawk a kamkhueng awh.
11 Ní àkókò yìí, wọ́n rú ẹbọ sí Olúwa ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin akọ màlúù àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin àgùntàn àti àwọn ewúrẹ́ láti ibi ìkógun tí wọ́n ti kó padà.
Hatnae hnin dawk a lawp e maitotan 700, tu 7000 touh hoi BAWIPA koe thuengnae a sak awh.
12 Wọ́n sì tún dá májẹ̀mú láti wá Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn tinútinú wọn àti tọkàntọkàn wọn.
A lungthin hoi a hringnae abuemlah mintoenaw e BAWIPA Cathut tawng hane hoi,
13 Pé ẹnikẹ́ni tí kò bá wá Olúwa Ọlọ́run Israẹli, pípa ni á ó pa á láti ẹni kékeré dé orí ẹni ńlá àti ọkùnrin àti obìnrin.
Isarelnaw e BAWIPA Cathut ka tawng ngaihoeh e tami bangpatethai thoseh, tami kathoung kalen, napui tongpa abuemlah koung thei hanelah lawkkamnae a sak awh.
14 Wọ́n sì búra ní ohùn rara fún Olúwa àti pẹ̀lú ìhó ńlá àti pẹ̀lú ìpè àti pẹ̀lú fèrè.
BAWIPA min lahoi hote lawkkamnae tarawi hanelah mongka hoi tuki kacaipounglah a ueng awh teh, thoebonae lahoi a hramki awh.
15 Gbogbo Juda yọ̀ nípa ìbúra náà nítorí wọ́n ti búra tinútinú wọn wọ́n sì fi gbogbo ìfẹ́ inú wọn wá a, wọ́n sì rí i, Olúwa sì fún wọn ní ìsinmi yí káàkiri.
Judahnaw abuemlah hoi hote lawkkamnae dawk a lunghawi awh teh, lungthin abuemlah hoi lawkkamnae a sak awh teh a hringnae abuemlah hoi ama a tawng awh. Hahoi ama a hmu awh teh, BAWIPA ni hmuen tangkuem koe roumnae a poe.
16 Ọba Asa sì mú Maaka ìyá ńlá rẹ̀ kúrò láti máa ṣe ayaba, nítorí tí ó yá ère kan fún Aṣerah òrìṣà rẹ̀. Asa sì ké ère náà lulẹ̀, ó sì jó o ní àfonífojì Kidironi.
Siangpahrang Asa e manu Maakah hai panuettho e meikaphawk Asherah a sak kecu dawkvah, siangpahrangnu dawk hoi a kâhat sak. Meikaphawk teh Asa ni koung ka rawm lah a hem teh, a raphoe hnukkhu, Kidron palang teng vah hmai a sawi.
17 Ṣùgbọ́n a kò mú àwọn ibi gíga náà kúrò ní Israẹli; síbẹ̀síbẹ̀ ọkàn Asa wà ní pípé ní ọjọ́ rẹ̀ gbogbo.
Hatei, Isarel ram dawk e hmuenrasangnaw teh takhoe lah awm hoeh rah. Asa e lungthin teh a bawi nathung yuemkamcu e lah ao.
18 Ó sì mú àwọn ohun mímọ́ náà ti baba rẹ̀ àti àwọn ohun mímọ́ ti òun tìkára rẹ̀ tirẹ̀ wá sínú ilé Ọlọ́run, wúrà àti fàdákà àti àwọn ohun èlò náà.
A na pa ni a poe e hnopainaw, ama ni a poe e hnopainaw sui hoi ngunnaw teh Cathut e im dawk a hruek.
19 Kò sí ogun mọ́ títí fún ọdún márùndínlógójì ti ìjọba Asa.
Asa siangpahrang kum 35 touh a tawk. A tawk nathung tarankâtuknae banghai awm hoeh.

< 2 Chronicles 15 >