< 2 Chronicles 15 >

1 Ẹ̀mí Ọlọ́run wá sórí Asariah ọmọ Odedi.
Gode Ea A: silibu da A: salaia (Oudede egefe) ema aligila sa: i. Amola e da hina bagade A: isa ba: musa: asi. E da amane wele sia: i. “Hina bagade A: isa! Amola Yuda fi amola Bediamini fi dunu huluane! Na sia: nabima! Dilia da Hina Godema noga: le fa: no bobogesea, E da dilima gamu. Dilia E hogosea, E ba: mu. Be dilia E baligi fa: sea, E da dili fisidigimu.
2 Ó jáde lọ bá Asa, ó sì wí fún un pé, “Tẹ́tí si mi Asa, àti gbogbo Juda àti Benjamini. Olúwa wà pẹ̀lú rẹ, nígbà tí ìwọ bá wà pẹ̀lú rẹ̀. Ti ìwọ bá wá a, ìwọ yóò rí i ní ẹ̀bá ọ̀dọ̀ rẹ ṣùgbọ́n tí ìwọ bá kọ̀ ọ́ sílẹ̀, òun yóò kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
3 Fún ọjọ́ pípẹ́ ni Israẹli ti wà láì sin Ọlọ́run òtítọ́, àti láìní àlùfáà ti ń kọ́ ni, àti láìní òfin.
Eso bagohame, Isala: ili fi da Godedafa hamedene, gobele salasu olelesu dunu hamedene, amola sema hamedenewane esalu.
4 Ṣùgbọ́n nínú ìpọ́njú wọn, wọ́n yí padà si Olúwa Ọlọ́run Israẹli, wọ́n sì wa kiri. Wọ́n sì ri i ní ẹ̀gbẹ́ wọn.
Be se nabasu da ilima doaga: loba, ilia da Isala: ili Hina Godema bu sinidigi. Ilia da E hogolalu, ba: i dagoi.
5 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ó léwu kí ènìyàn máa rìn ìrìnàjò kiri, nítorí tí gbogbo àwọn olùgbé ilẹ̀ náà wà nínú làálàá ńlá.
Amo esoga, dunu da hahawane halegale lalumu hamedei ba: i. Bai bidi hamosu amola wili gala: su, amo soge huluane ganodini ba: i.
6 Orílẹ̀-èdè kan ń run èkejì àti ìlú kan sí òmíràn nítorí Ọlọ́run ń yọ wọ́n lẹ́nu pẹ̀lú oríṣìíríṣìí ìpọ́njú.
Fi afae da fi eno amo banenesi. Moilai bai bagade da eno moilai bai bagade amo banenesi. Bai Gode da amo se nabasu ilima i dagoi.
7 Ṣùgbọ́n fun ìwọ, jẹ́ alágbára, kí ó má sì ṣe ṣàárẹ̀. Nítorí tí a ó fi èrè sí iṣẹ́ ẹ̀ rẹ.”
Be dilia da gasa fili, mae da: i dioma. Dilia hawa: hamobeba: le, bidi noga: i lamu.”
8 Nígbà tí Asa gbọ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí àti àsọtẹ́lẹ̀ Asariah ọmọ Odedi wòlíì, ó mú àyà rẹ̀ le. Ó sì mú gbogbo ohun ìríra kúrò ní gbogbo ilẹ̀ Juda àti Benjamini àti kúrò nínú àwọn ìlú tí ó ti fi agbára mú ní orí òkè Efraimu. Ó tún pẹpẹ Olúwa ṣe tí ó wà ní iwájú portiko ti ilé Olúwa.
A: isa da A: salaia (Oudede egefe) amo ea ba: la: lusu sia: nababeba: le, ea dogo denesi. E da ogogosu ‘gode’ loboga hamoi liligi huluane Yuda soge, Bediamini soge amola moilai bai bagade huluane e da Ifala: ime sogega susugui, amo ganodini dialu amo mugululi fasi. Amola e da Hina Gode oloda amo da Debolo Diasu gagoi ganodini dialu, amo bu dodoa: i.
9 Nígbà náà, ó pe gbogbo Juda àti Benjamini jọ àti àwọn ènìyàn láti Efraimu, Manase àti Simeoni tí ó ti ṣe àtìpó ní àárín wọn. Nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn ti wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ láti Israẹli nígbà tí wọ́n rí i wí pé Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ wà pẹ̀lú rẹ̀.
Ifala: ime, Ma: na: se amola Simione fi dunu bagohame da Isala: ili fisili, A:isama gai. Bai ilia Hina Gode da A: isama gai ba: i. A: isa da ili huluane, amola Yuda amola Bediamini fi dunu ema misa: ne sia: i.
10 Wọ́n péjọ sí Jerusalẹmu ní oṣù kẹta ọdún kẹ́ẹ̀dógún ti ìjọba Asa.
Ili huluane da oubi osoda amola ode 15 A: isa ea ouligibi galu, Yelusalemega gilisi.
11 Ní àkókò yìí, wọ́n rú ẹbọ sí Olúwa ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin akọ màlúù àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin àgùntàn àti àwọn ewúrẹ́ láti ibi ìkógun tí wọ́n ti kó padà.
Amo esoga, ilia da ilia susugui liligi mogili, Hina Godema gobele salasu hamoi. Ilia da bulamagau 700 agoane amola sibi 7,000 agoane gobele sali.
12 Wọ́n sì tún dá májẹ̀mú láti wá Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn tinútinú wọn àti tọkàntọkàn wọn.
Ilia aowalalia Hina Godema ilia asigi dawa: su huluane, amola ilia a: silibu huluane, amoga Ema nodone sia: ne gadolaloma: ne, ilegele sia: i dagoi.
13 Pé ẹnikẹ́ni tí kò bá wá Olúwa Ọlọ́run Israẹli, pípa ni á ó pa á láti ẹni kékeré dé orí ẹni ńlá àti ọkùnrin àti obìnrin.
Nowa da ayeligi o da: i hamoi, dunu o uda, amo da Hina Godema nodone sia: ne gadomu hihisia, ilia da amo medole legema: ne sia: i.
14 Wọ́n sì búra ní ohùn rara fún Olúwa àti pẹ̀lú ìhó ńlá àti pẹ̀lú ìpè àti pẹ̀lú fèrè.
Ilia da Hina Gode Ea Dioba: le, amo ilegele sia: su noga: le ouligima: ne wele sia: i. Amalalu, ilia ha: giwane wele sisia: sa, dalabede fulabosu.
15 Gbogbo Juda yọ̀ nípa ìbúra náà nítorí wọ́n ti búra tinútinú wọn wọ́n sì fi gbogbo ìfẹ́ inú wọn wá a, wọ́n sì rí i, Olúwa sì fún wọn ní ìsinmi yí káàkiri.
Yuda dunu huluane da amo ilegele sia: su (gousa: su) noga: le hamoiba: le, hahawane bagade ba: i. Ilia da Hina Godema nodone sia: ne gadobeba: le, hahawane bagade ba: i. Hina Gode da ili lale sali, amola Ea hamobeba: le, ili sisiga: le fi da ili hame doagala: i.
16 Ọba Asa sì mú Maaka ìyá ńlá rẹ̀ kúrò láti máa ṣe ayaba, nítorí tí ó yá ère kan fún Aṣerah òrìṣà rẹ̀. Asa sì ké ère náà lulẹ̀, ó sì jó o ní àfonífojì Kidironi.
Hina bagade A: isa da ea aiya: Ma: iaga amo sefasi. Bai e da ogogosu uda ‘gode’ Asila, ema nodone sia: ne gadoma: ne, wadela: idafa ‘gode’ liligi ea loboga hamoi. A: isa da amo loboga hamoi ‘gode’ aba sasalili, Gidalone Fagoga ulagisi.
17 Ṣùgbọ́n a kò mú àwọn ibi gíga náà kúrò ní Israẹli; síbẹ̀síbẹ̀ ọkàn Asa wà ní pípé ní ọjọ́ rẹ̀ gbogbo.
A: isa da ea esalusu huluane ganodini, Hina Godema madelagili esalebe ba: i. Be ogogosu ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadosu sogebi mogili, e da hame gugunufinisi.
18 Ó sì mú àwọn ohun mímọ́ náà ti baba rẹ̀ àti àwọn ohun mímọ́ ti òun tìkára rẹ̀ tirẹ̀ wá sínú ilé Ọlọ́run, wúrà àti fàdákà àti àwọn ohun èlò náà.
E da noga: i liligi amo ea eda Abaidia da Godema modale ligiagale i, amola gouli amola silifa amo hisu da modale ligiagale i, amo huluane Debolo Diasu ganodini lidili legei.
19 Kò sí ogun mọ́ títí fún ọdún márùndínlógójì ti ìjọba Asa.
Isala: ili fi da olofole esalu, amogainini A: isa ea ouligibi ode 35 da doaga: i.

< 2 Chronicles 15 >