< 2 Chronicles 13 >

1 Ní ọdún kejìdínlógún ìjọba Jeroboamu, Abijah di ọba Juda.
No te tekau ma waru o nga tau o Kingi Ieropoama i kingi ai a Apia ki a Hura.
2 Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́ta. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Mikaiah, ọmọbìnrin Urieli ti Gibeah. Ogun wà láàrín Abijah àti Jeroboamu.
A e toru nga tau i kingi ai ia ki Hiruharama. Ko te ingoa o tona whaea ko Mikaia, he tamahine na Uriere no Kipea. A he whawhai ta Apia raua ko Ieropoama ki a raua.
3 Abijah lọ sí ojú ogun pẹ̀lú àwọn ọmọ-ogun ogún ọ̀kẹ́ ọkùnrin alágbára, Jeroboamu kó ogun jọ pẹ̀lú ogójì ọ̀kẹ́ ọ̀wọ́ ogun tí ó lágbára.
Na ka whakatikaia e Apia nga ngohi o tana ope, he hunga maia mo te whawhai, e wha rau mano, he hunga whiriwhiri. I whakatikaia ano e Ieropoama ana ngohi hei whawhai ki a ia; e waru rau mano ana, he hunga whiriwhiri, he marohirohi, he toa.
4 Abijah dúró lórí òkè Semaraimu ní òkè orílẹ̀-èdè Efraimu, ó sì wí pé, Jeroboamu àti gbogbo Israẹli, ẹ gbọ́ mi!
Na ka tu a Apia i runga i Maunga Temaraima, i te whenua pukepuke o Eparaima, a ka mea, Whakarongo mai ki ahau, e Ieropoama, koutou ko Iharaira katoa;
5 Ṣé ẹ̀yin kò mọ̀ pé Olúwa Ọlọ́run Israẹli ti fún Dafidi àti àwọn àtẹ̀lé rẹ̀ ni oyè ọba títí láé nípasẹ̀ májẹ̀mú iyọ̀?
Kaua ranei koutou e mohio, he mea homai na Ihowa, na te Atua o Iharaira te kingitanga o Iharaira ki a Rawiri, he mea oti tonu ki a ia, ratou ko ana tama, i runga ano i te kawenata tote?
6 Síbẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, oníṣẹ́ Solomoni ọmọ Dafidi, ṣọ̀tẹ̀ sí ọ̀gá rẹ̀.
Otira i whakatika ake a Ieropoama tama a Nepata, pononga a Horomona tama a Rawiri, kei te whakakeke ki tona ariki.
7 Àwọn ènìyàn lásán sì kó ara wọn jọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, àwọn ọmọ ẹni búburú, wọ́n sì kẹ̀yìn sí Rehoboamu ọmọ Solomoni ní ìgbà tí ó sì kéré tí kò lè pinnu fúnra rẹ̀, tí kò lágbára tó láti takò wọ́n.
Na ko te huihuinga o etahi tangata wairangi, he tama na Periara, ki a ia, kua whakapakari i a ratou ki a Rehopoama tama a Horomona, i te mea he taitamariki a Rehopoama, he ngawari hoki tona ngakau, a kihai i kaha ki a ratou.
8 “Nísinsin yìí, ìwọ ṣètò láti kọ́ ìjọba Olúwa, tí ó wà lọ́wọ́ àwọn àtẹ̀lé Dafidi. Ìwọ jẹ́ ọmọ-ogun tí ó gbilẹ̀, ìwọ sì ní pẹ̀lú rẹ ẹgbọrọ màlúù wúrà ti Jeroboamu dà láti fi ṣe Ọlọ́run yín.
Na e mea na koutou ki te whakatenetene ki te kingitanga o Ihowa kei te ringa nei o nga tama a Rawiri; he huihui nui to koutou, a kei a koutou nga kuao kau koura i hanga na e Ieropoama hei atua mo koutou.
9 Ṣùgbọ́n ṣé ìwọ kò lé àwọn àlùfáà Olúwa jáde, àwọn ọmọ Aaroni àti àwọn ará Lefi. Tí ó sì ṣe àwọn àlùfáà ti ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àwọn ènìyàn ilẹ̀ mìíràn ti ṣe? Ẹnikẹ́ni tí ó bá wá láti ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ pẹ̀lú ọ̀dọ́ akọ màlúù àti àgbò méjì lè jẹ́ àlùfáà ohun tí kì í ṣe Ọlọ́run.
He teka ianei kua peia e koutou nga tohunga a Ihowa, nga tama a Arona, ratou ko nga Riwaiti; a whakatohungatia ana e koutou etahi tohunga, pera ana koutou me nga iwi o era atu whenua? Na, ko te tangata e haere ana ki te whakatohunga i a ia ki te puru, ki te tama a te kau, ki nga hipi toa e whitu, hei tohunga ia mo nga mea ehara nei i te atua.
10 “Ní ti àwa, Olúwa ni Ọlọ́run wa, àwa kò sì ti ì kọ̀ ọ́ sílẹ̀. Àwọn àlùfáà tí ó ń sin Olúwa jẹ́ àwọn ọmọ Aaroni àwọn ará Lefi sì ń ràn wọ́n lọ́wọ́.
Tena ko matou, ko Ihowa to matou Atua, kihai hoki matou i whakarere i a ia. Na he tohunga a matou e minita ana ki a Ihowa, ko nga tama a Arona, ko nga Riwaiti kei ta ratou mahi.
11 Ní àràárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́, wọ́n gbé ẹbọ sísun àti tùràrí olóòórùn dídùn síwájú Olúwa. Wọ́n gbé àkàrà jáde sórí tábìlì àsè mímọ́, wọ́n sì tan iná sí àwọn fìtílà lórí ìdúró ọ̀pá fìtílà wúrà ní gbogbo ìrọ̀lẹ́. A ń pa àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wa mọ́. Ṣùgbọ́n ìwọ ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
A e tahu tinana ana ratou ki a Ihowa, e tahu kakara reka ana i te ata, i te ahiahi: me te taro aroaro e whakatakotoria ana ki te tepu parakore; me te turanga rama koura me ona rama, hei tahu i nga ahiahi. E mau ana hoki i a matou nga mea a Ihowa, a to matou Atua; ko koutou ia kua whakarere i a ia.
12 Ọlọ́run wà pẹ̀lú wa; òun ni olórí wa. Àwọn àlùfáà rẹ̀ pẹ̀lú fèrè wọn yóò fọn ìpè ogun sí i yín. Ẹyin ọkùnrin Israẹli, ẹ má ṣe dojú ìjà kọ Olúwa Ọlọ́run baba yín nítorí ẹ̀yin kì yóò yege.”
Na, tena, kei a matou te Atua hei rangatira, me ana tohunga, me nga tetere tangi nui, hei whakatangi i te whawhai ki a koutou. E nga tama a Iharaira, kaua e whawhai ki a Ihowa, ki te Atua o o koutou matua; e kore hoki e taea e koutou.
13 Nísinsin yìí, Jeroboamu ti rán àwọn ọ̀wọ́ ogun lọ yíká láti jagun ẹ̀yìn. Kí ó lè jẹ́ pé, tí òun bá wà níwájú Juda, bíba ní bùba á wà ní ẹ̀yìn wọn.
Otira i whakataka e Ieropoama he pehipehi kia haere awhio atu i muri i a ratou: na ko ratou ki te aroaro o Hura, ko te pehipehi ki muri i a ratou.
14 Nígbà tí Juda sì bojú wo ẹ̀yìn, sì kíyèsi i, ogun ń bẹ níwájú àti lẹ́yìn, wọn sì ké pe Olúwa, àwọn àlùfáà sì fun ìpè.
A, i te tahuritanga o Hura, na e tauria ana a mua, a muri, o ratou. Na karanga ana ratou ki a Ihowa, a whakatangi ana nga tohunga i nga tetere.
15 Olúkúlùkù, ọkùnrin Juda sì fún ìpè ogun, ó sì ṣe, bí àwọn ọkùnrin Juda sì ti fun ìpè ogun, ni Ọlọ́run kọlu Jeroboamu àti gbogbo Israẹli níwájú Abijah àti Juda.
Katahi ka hamama nga tangata o Hura. A, no te hamamatanga o nga tangata o Hura, na patua iho e te Atua a Ieropoama ratou ko Iharaira katoa i te aroaro o Apia ratou ko Hura.
16 Àwọn ọmọ Israẹli sálọ kúrò níwájú Juda, Ọlọ́run sì fi wọ́n lé wọn lọ́wọ́.
Na rere ana nga tama a Iharaira i te aroaro o Hura, a homai ana ratou e te Atua ki o ratou ringa.
17 Abijah àti àwọn arákùnrin rẹ̀ fi ìdààmú ńlá jẹ wọ́n ní ìyà, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀kẹ́ mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ọkùnrin tí a yàn ṣubú ní pípa nínú Israẹli.
Patua iho ratou e Apia ratou ko tona iwi, he nui te parekura. Na hinga ana o Iharaira, he mea patu, e rima rau mano, he hunga whiriwhiri.
18 Báyìí ni a rẹ àwọn ọmọ Israẹli sílẹ̀ ní àkókò náà, àwọn ọmọ Juda sì borí nítorí tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn.
Heoi kua riro ki raro nga tama a Iharaira i taua wa; a ka kaha nga tama a Hura, no ratou i okioki ki a Ihowa, ki te Atua o o ratou matua.
19 Abijah sì lépa Jeroboamu, ó sì gba ìlú lọ́wọ́ rẹ̀, Beteli pẹ̀lú àwọn ìlú rẹ̀, àti Jeṣana pẹ̀lú àwọn ìlú rẹ̀, àti Efroni pẹ̀lú àwọn ìlú rẹ̀.
Na ka whaia a Ieropoama e Apia, a ka riro etahi o ona pa i a ia, a Peteere me ona pa ririki, a Tehana me ona pa ririki, a Eperaina me ona pa ririki.
20 Bẹ́ẹ̀ ní Jeroboamu kò sì tún ní agbára mọ́ ní ọjọ́ Abijah. Olúwa sì lù ú ó sì kú.
A kihai a Ieropoama i whai kaha ano i nga ra o Apia, a patua ana ia e Ihowa, mate ake.
21 Abijah sì di alágbára, ó sì gbé obìnrin mẹ́tàlá ní ìyàwó, ó sì bi ọmọkùnrin méjìlélógún, àti ọmọbìnrin mẹ́rìndínlógún.
Otiia ka kaha haere a Apia. I tangohia ano e ia etahi wahine mana kotahi tekau ma wha, a whanau ake, e rua tekau ma rua nga tama, kotahi tekau ma ono nga kotiro.
22 Àti ìyókù ìṣe Abijah, àti ìwà rẹ̀, àti iṣẹ́ rẹ̀, a kọ wọ́n sínú ìwé ìtumọ̀, wòlíì Iddo.
Na, ko era atu meatanga a Apia, me ona ara, me ana kupu, kei te tuhituhi i roto i nga korero a Iro poropiti.

< 2 Chronicles 13 >