< 2 Chronicles 12 >
1 Lẹ́yìn ìgbà tí a fi ìjọba Rehoboamu múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba, tí ó sì ti di alágbára, òun àti gbogbo Israẹli, pẹ̀lú rẹ̀ ni wọ́n pa òfin Olúwa tì.
Кынд с-а ынтэрит Робоам ын домние ши а кэпэтат путере, а пэрэсит Леӂя Домнулуй, ши тот Исраелул а пэрэсит-о ымпреунэ ку ел.
2 Nítorí tí wọn kò ṣọ òtítọ́ sí Olúwa. Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu ní ọdún karùn-ún ti ọba Rehoboamu.
Ын ал чинчиля ан ал домнией луй Робоам, Шишак, ымпэратул Еӂиптулуй, с-а суит ымпотрива Иерусалимулуй, пентру кэ пэкэтуисерэ ымпотрива Домнулуй.
3 Pẹ̀lú ẹgbàá mẹ́fà kẹ̀kẹ́ àti ọ̀kẹ́ mẹ́ta àwọn ọkùnrin ẹlẹ́ṣin àti àìníye ọ̀wọ́ ogun ti Libia, Sukki àti Kuṣi, tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ láti Ejibiti.
Авя о мие доуэ суте де каре ши шайзечь де мий де кэлэрець ши, ымпреунэ ку ел, а венит дин Еӂипт ун попор фэрэ нумэр, динтре либиень, сукиень ши етиопень.
4 Ó fi agbára mú àwọn ìlú ààbò ti Juda, pẹ̀lú wá sí Jerusalẹmu bí ó ti jìnnà tó.
А луат четэциле ынтэрите але луй Иуда ши а ажунс пынэ ла Иерусалим.
5 Nígbà náà, wòlíì Ṣemaiah wá sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu àti sí ọ̀dọ̀ àwọn olórí Juda tí wọ́n ti péjọ ní Jerusalẹmu nítorí ìbẹ̀rù Ṣiṣaki, ó sì wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ìwọ ti pa mí tì; nítorí náà èmi náà ti pa yín tì sí ọ̀dọ̀ Ṣiṣaki.”
Атунч, пророкул Шемая с-а дус ла Робоам ши ла кэпетенииле луй Иуда, каре се адунасерэ ын Иерусалим ла апропиеря луй Шишак, ши ле-а зис: „Аша ворбеште Домнул: ‘Вой М-аць пэрэсит; вэ пэрэсеск ши Еу ши вэ дау ын мыниле луй Шишак.’”
6 Àwọn olórí Israẹli àti ọba rẹ̀ ará wọn sílẹ̀, wọ́n sì wí pé, “Olódodo ni Olúwa.”
Кэпетенииле луй Исраел ши ымпэратул с-ау смерит ши ау зис: „Домнул есте дрепт!”
7 Nígbà tí Olúwa rí i pé, wọ́n ti rẹ̀ ara wọn sílẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa yí tọ Ṣemaiah lọ pé, “Níwọ́n ìgbà tí wọ́n ti rẹ ara wọn sílẹ̀, Èmi kì yóò pa wọ́n ṣùgbọ́n, yóò fún wọn ní ìtúsílẹ̀ tó bá yá. Ìbínú mi kì yóò dà sórí Jerusalẹmu ní ipasẹ̀ Ṣiṣaki.
Ши, дакэ а вэзут Домнул кэ с-ау смерит, кувынтул Домнулуй а ворбит астфел луй Шемая: „С-ау смерит, ну-й вой нимичи, ну вой зэбови сэ ле вин ын ажутор ши мыния Мя ну ва вени асупра Иерусалимулуй прин Шишак,
8 Bí ó ti wù kí ó rí, wọn yóò sìn ní abẹ́ rẹ̀, kí wọn kí ó lè mọ̀ ìyàtọ̀ láàrín sí sìn mí àti sí sin àwọn ọba ilẹ̀ mìíràn.”
дар ый вор фи супушь ши вор шти че ынсямнэ сэ-Мь служяскэ Мие сау сэ служяскэ ымпэрэциилор алтор цэрь.”
9 Nígbà tí Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu, ó gbé àwọn ìṣúra ilé Olúwa, àti àwọn ìṣúra ààfin ọba. Ó gbé gbogbo rẹ̀, pẹ̀lú àwọn àpáta wúrà tí Solomoni dá.
Шишак, ымпэратул Еӂиптулуй, с-а суит ымпотрива Иерусалимулуй. А луат вистиерииле Касей Домнулуй ши вистиерииле касей ымпэратулуй, а луат тот. А луат скутуриле де аур пе каре ле фэкусе Соломон.
10 Bẹ́ẹ̀ ni, ọba Rehoboamu dá àwọn àpáta idẹ láti fi dípò wọn, ó sì fi èyí lé àwọn alákòóso àti olùṣọ́ tí ó wà ní ẹnu iṣẹ́ ní àbáwọlé ẹnu-ọ̀nà ààfin ọba lọ́wọ́.
Ымпэратул Робоам а фэкут ын локул лор ниште скутурь де арамэ ши ле-а дат ын грижа кэпетениилор алергэторилор, каре пэзяу интраря касей ымпэратулуй.
11 Ìgbàkígbà tí ọba bá lọ sí ilé Olúwa, àwọn olùṣọ́ n lọ pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n ń gbé àwọn àpáta náà àti lẹ́yìn, wọ́n dá wọn padà sí yàrá ìṣọ́.
Орь де кыте орь се дучя ымпэратул ла Каса Домнулуй, алергэторий веняу ши ле пуртау ынаинтя луй, апой ле адучяу ярэшь ын одая алергэторилор.
12 Nítorí ti Rehoboamu rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, ìbínú Olúwa yí padà kúrò lórí rẹ̀, a kò sì pa á run pátápátá. Nítòótọ́, ìre díẹ̀ wà ní Juda.
Пентру кэ Робоам се смерисе, Домнул Шь-а абэтут мыния де ла ел ши ну л-а нимичит де тот. Ши тот май ера чева бун ын Иуда.
13 Ọba Rehoboamu fi ara rẹ̀ lélẹ̀ gidigidi ní Jerusalẹmu, ó sì tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí ọba. Ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógójì nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba fún ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ní Jerusalẹmu, ìlú ńlá tí Olúwa ti yàn jáde kúrò nínú gbogbo àwọn ẹ̀yà Israẹli ní èyí tí ó fẹ́ fi orúkọ rẹ̀ síbẹ̀. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Naama, ará Ammoni.
Ымпэратул Робоам с-а ынтэрит ын Иерусалим ши а домнит. Авя патрузечь ши уну де ань кынд а ажунс ымпэрат ши а домнит шаптеспрезече ань ла Иерусалим, четатя пе каре о алесесе Домнул дин тоате семинцииле луй Исраел ка сэ-Шь пунэ Нумеле ын еа. Мама са се нумя Наама, Амонита.
14 O sì ṣe búburú, nítorí tí kò múra nínú ọkàn rẹ̀ láti wá Olúwa.
Ел а фэкут лукрурь реле, пентру кэ ну шь-а пус инима сэ кауте пе Домнул.
15 Fún tí iṣẹ́ ìjọba Rehoboamu láti ìbẹ̀rẹ̀ dé ìparí, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé ìrántí ti Ṣemaiah wòlíì àti ti Iddo, aríran tí ó ní ṣe pẹ̀lú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá? Ìtẹ̀síwájú ogun jíjà sì wà láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu.
Фаптеле луй Робоам, челе динтый ши челе де пе урмэ, ну сунт скрисе оаре ын картя пророкулуй Шемая ши а пророкулуй Идо, ын кэрциле спицелор де ням? Тотдяуна а фост рэзбой ынтре Робоам ши Иеробоам.
16 Rehoboamu sun pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sin ín sínú ìlú ńlá ti Dafidi. Abijah ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Робоам а адормит ку пэринций сэй ши а фост ынгропат ын четатя луй Давид. Ши, ын локул луй, а домнит фиул сэу Абия.