< 2 Chronicles 12 >

1 Lẹ́yìn ìgbà tí a fi ìjọba Rehoboamu múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba, tí ó sì ti di alágbára, òun àti gbogbo Israẹli, pẹ̀lú rẹ̀ ni wọ́n pa òfin Olúwa tì.
Ket napasamak nga idi natalgeden ti panagturay ni Rehoboam ken nabiligen isuna, tinallikudanna agraman dagiti amin nga Israelita a kaduana ti linteg ni Yahweh.
2 Nítorí tí wọn kò ṣọ òtítọ́ sí Olúwa. Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu ní ọdún karùn-ún ti ọba Rehoboamu.
Ket napasamak nga iti maikalima a tawen ni Ari Rehoboam, rinaut ni Sisak nga ari ti Egipto ti Jerusalem, gapu ta saan a napudno dagiti tattao kenni Yahweh.
3 Pẹ̀lú ẹgbàá mẹ́fà kẹ̀kẹ́ àti ọ̀kẹ́ mẹ́ta àwọn ọkùnrin ẹlẹ́ṣin àti àìníye ọ̀wọ́ ogun ti Libia, Sukki àti Kuṣi, tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ láti Ejibiti.
Inkuyogna ti sangaribu ket dua a gasut a karuahe ken innem a pulo a ribu a kumakabalio. Saan a mabilang dagiti kakuyogna a soldado manipud iti Egipto: Dagiti taga-Libia, taga-Suk ken taga-Etiopia.
4 Ó fi agbára mú àwọn ìlú ààbò ti Juda, pẹ̀lú wá sí Jerusalẹmu bí ó ti jìnnà tó.
Sinakupna dagiti nasarikedkedan a siudad a sakup ti Juda ket napan isuna idiay Jerusalem.
5 Nígbà náà, wòlíì Ṣemaiah wá sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu àti sí ọ̀dọ̀ àwọn olórí Juda tí wọ́n ti péjọ ní Jerusalẹmu nítorí ìbẹ̀rù Ṣiṣaki, ó sì wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ìwọ ti pa mí tì; nítorí náà èmi náà ti pa yín tì sí ọ̀dọ̀ Ṣiṣaki.”
Ita, napan ni profeta Semaias kenni Rehoboam ken kadagiti panguloen ti Juda a naguummong idiay Jerusalem gapu kenni Sisak. Kinuna ni Semaias kadakuada, “Kastoy ti kuna ni Yahweh: 'Tinallikudandak, isu nga inyawatkayo met kenni Sisak.”'
6 Àwọn olórí Israẹli àti ọba rẹ̀ ará wọn sílẹ̀, wọ́n sì wí pé, “Olódodo ni Olúwa.”
Ket nagpakumbaba dagiti prinsipe ti Israel ken ti ari ket kinunada, “Nalinteg ni Yahweh.”
7 Nígbà tí Olúwa rí i pé, wọ́n ti rẹ̀ ara wọn sílẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa yí tọ Ṣemaiah lọ pé, “Níwọ́n ìgbà tí wọ́n ti rẹ ara wọn sílẹ̀, Èmi kì yóò pa wọ́n ṣùgbọ́n, yóò fún wọn ní ìtúsílẹ̀ tó bá yá. Ìbínú mi kì yóò dà sórí Jerusalẹmu ní ipasẹ̀ Ṣiṣaki.
Idi nakita ni Yahweh a nagpakumbabada, immay ti sao ni Yahweh kenni Semaias; kinunana, “Nagpakumbabada. Saanko ida a dadaelen; ispalekto ida manipud iti naan-anay a pannakadadael, ken saanto a maibukbok ti pungtotko iti Jerusalem babaen iti ima ni Sisak.
8 Bí ó ti wù kí ó rí, wọn yóò sìn ní abẹ́ rẹ̀, kí wọn kí ó lè mọ̀ ìyàtọ̀ láàrín sí sìn mí àti sí sin àwọn ọba ilẹ̀ mìíràn.”
Nupay kasta, agbalindanto nga adipenna, tapno maawatanda ti nagdumaan ti panagserbi kaniak ken ti panagserbi kadagiti mangiturturay kadagiti dadduma a pagilian.”
9 Nígbà tí Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu, ó gbé àwọn ìṣúra ilé Olúwa, àti àwọn ìṣúra ààfin ọba. Ó gbé gbogbo rẹ̀, pẹ̀lú àwọn àpáta wúrà tí Solomoni dá.
Rinaut ngarud ni Sisak nga ari ti Egipto ti Jerusalem ket innalana dagiti gameng iti balay ni Yahweh ken dagiti gameng iti balay ti ari. Innalana amin; innalana pay dagiti kalasag a balitok nga inaramid ni Solomon.
10 Bẹ́ẹ̀ ni, ọba Rehoboamu dá àwọn àpáta idẹ láti fi dípò wọn, ó sì fi èyí lé àwọn alákòóso àti olùṣọ́ tí ó wà ní ẹnu iṣẹ́ ní àbáwọlé ẹnu-ọ̀nà ààfin ọba lọ́wọ́.
Nangaramid ni Ari Rehoboam kadagiti kalasag a bronse a kasukat dagitoy ket intalekna dagitoy kadagiti ima dagiti panguloen dagiti guardia, a mangbanbantay kadagiti ruangan ti balay ti ari.
11 Ìgbàkígbà tí ọba bá lọ sí ilé Olúwa, àwọn olùṣọ́ n lọ pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n ń gbé àwọn àpáta náà àti lẹ́yìn, wọ́n dá wọn padà sí yàrá ìṣọ́.
Ket napasamak a tunggal sumrek ti ari iti balay ni Yahweh, awiten dagiti guardia dagitoy a kalasag; ket isublidanto met laeng dagitoy iti siled dagiti guardia.
12 Nítorí ti Rehoboamu rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, ìbínú Olúwa yí padà kúrò lórí rẹ̀, a kò sì pa á run pátápátá. Nítòótọ́, ìre díẹ̀ wà ní Juda.
Idi nagpakumbaba ni Rehoboam, bimmaaw ti pungtot ni Yahweh kenkuana, isu a saanna isuna a namimpinsan a dinadael; maysa pay, adda pay laeng masarakan a kinaimbag idiay Juda.
13 Ọba Rehoboamu fi ara rẹ̀ lélẹ̀ gidigidi ní Jerusalẹmu, ó sì tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí ọba. Ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógójì nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba fún ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ní Jerusalẹmu, ìlú ńlá tí Olúwa ti yàn jáde kúrò nínú gbogbo àwọn ẹ̀yà Israẹli ní èyí tí ó fẹ́ fi orúkọ rẹ̀ síbẹ̀. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Naama, ará Ammoni.
Pinabileg ngarud ni Ari Rehoboam ti kinaarina idiay Jerusalem, ket nagturay isuna. Agtawen iti uppat a pulo ket maysa ni Rehoboam idi nangrugi isuna nga agturay, ket nagturay isuna iti sangapulo ket pito a tawen idiay Jerusalem, a siudad a pinili ni Yahweh manipud kadagiti amin a tribu ti Israel tapno kanayon a maidayaw isuna sadiay. Naama ti nagan ti inana, a taga-Ammon.
14 O sì ṣe búburú, nítorí tí kò múra nínú ọkàn rẹ̀ láti wá Olúwa.
Dakes ti inaramidna, gapu ta saanna nga impapuso a sapulen ni Yahweh.
15 Fún tí iṣẹ́ ìjọba Rehoboamu láti ìbẹ̀rẹ̀ dé ìparí, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé ìrántí ti Ṣemaiah wòlíì àti ti Iddo, aríran tí ó ní ṣe pẹ̀lú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá? Ìtẹ̀síwájú ogun jíjà sì wà láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu.
No maipanggep kadagiti dadduma a banbanag maipapan kenni Rehoboam, manipud iti rugi agingga iti maudi, saan kadi a naisurat dagitoy kadagiti surat ni profeta Semaias ken ni Iddo a Mammadto, nga addaan met iti listaan iti kaputotan ni Rehoboam ken iti kankanayon a panagginnubat da ken ni Jeroboam?
16 Rehoboamu sun pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sin ín sínú ìlú ńlá ti Dafidi. Abijah ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Pimmusay ni Rehoboam ket naitabon iti siudad ni David; ni Abias a putotna a lalaki ti simmukat kenkuana nga ari.

< 2 Chronicles 12 >