< 2 Chronicles 12 >

1 Lẹ́yìn ìgbà tí a fi ìjọba Rehoboamu múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba, tí ó sì ti di alágbára, òun àti gbogbo Israẹli, pẹ̀lú rẹ̀ ni wọ́n pa òfin Olúwa tì.
Rehoboam kah ram neh a thadueng he cikngae bangla om, amah neh Israel boeih long khaw BOEIPA kah olkhueng te a hnawt.
2 Nítorí tí wọn kò ṣọ òtítọ́ sí Olúwa. Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu ní ọdún karùn-ún ti ọba Rehoboamu.
Rehoboam manghai kah a kum nga dongah tah BOEIPA taengah boe a koek uh dongah Egypt manghai Shishak loh Jerusalem te a muk.
3 Pẹ̀lú ẹgbàá mẹ́fà kẹ̀kẹ́ àti ọ̀kẹ́ mẹ́ta àwọn ọkùnrin ẹlẹ́ṣin àti àìníye ọ̀wọ́ ogun ti Libia, Sukki àti Kuṣi, tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ láti Ejibiti.
Te vaengah leng thawngkhat yahnih, marhang caem thawng sawmrhuk lo. Egypt, Lubim, Sukkiim neh Kushi lamloh anih taengla aka pawk he pilnam hlangmi naa moenih.
4 Ó fi agbára mú àwọn ìlú ààbò ti Juda, pẹ̀lú wá sí Jerusalẹmu bí ó ti jìnnà tó.
Judah kah kasam khopuei rhoek te a loh tih Jerusalem la pawk.
5 Nígbà náà, wòlíì Ṣemaiah wá sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu àti sí ọ̀dọ̀ àwọn olórí Juda tí wọ́n ti péjọ ní Jerusalẹmu nítorí ìbẹ̀rù Ṣiṣaki, ó sì wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ìwọ ti pa mí tì; nítorí náà èmi náà ti pa yín tì sí ọ̀dọ̀ Ṣiṣaki.”
Te vaengah tonghma Shemaiah te Jerusalem kah Shishak maelhmai kongah aka tingtun Rehoboam neh Judah mangpa rhoek taengla pawk tih amih te, “Nangmih kah BOEIPA loh he ni a thui. Kai nan hnawt uh coeng dongah ni kai loh nangmih te Shishak kut ah kam voeih,” a ti nah.
6 Àwọn olórí Israẹli àti ọba rẹ̀ ará wọn sílẹ̀, wọ́n sì wí pé, “Olódodo ni Olúwa.”
Te daengah Israel mangpa rhoek neh manghai khaw kunyun tih, “BOEIPA tah dueng pai,” a ti uh.
7 Nígbà tí Olúwa rí i pé, wọ́n ti rẹ̀ ara wọn sílẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa yí tọ Ṣemaiah lọ pé, “Níwọ́n ìgbà tí wọ́n ti rẹ ara wọn sílẹ̀, Èmi kì yóò pa wọ́n ṣùgbọ́n, yóò fún wọn ní ìtúsílẹ̀ tó bá yá. Ìbínú mi kì yóò dà sórí Jerusalẹmu ní ipasẹ̀ Ṣiṣaki.
Te dongah a kunyun uh te BOEIPA loh a hmuh vaengah BOEIPA ol Shemaiah taengla pawk tih, “A kunyun coeng dongah amih te ka phae mahpawh. Tedae amih te loeihnah ka paek pawn ni. Ka kosi Shishak kut lamloh Jerusalem ah bo mahpawh.
8 Bí ó ti wù kí ó rí, wọn yóò sìn ní abẹ́ rẹ̀, kí wọn kí ó lè mọ̀ ìyàtọ̀ láàrín sí sìn mí àti sí sin àwọn ọba ilẹ̀ mìíràn.”
Tedae anih taengah sal la a om uh daengah nikai kah thothuengnah neh diklai ram kah thothuengnah te a ming uh eh,” a ti nah.
9 Nígbà tí Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu, ó gbé àwọn ìṣúra ilé Olúwa, àti àwọn ìṣúra ààfin ọba. Ó gbé gbogbo rẹ̀, pẹ̀lú àwọn àpáta wúrà tí Solomoni dá.
Egypt manghai Shishak loh Jerusalem te a paan vaengah BOEIPA im thakvoh neh manghai im kah thakvoh te a loh. A cungkuem te a loh tih Solomon loh a saii sui photling khaw a khuen.
10 Bẹ́ẹ̀ ni, ọba Rehoboamu dá àwọn àpáta idẹ láti fi dípò wọn, ó sì fi èyí lé àwọn alákòóso àti olùṣọ́ tí ó wà ní ẹnu iṣẹ́ ní àbáwọlé ẹnu-ọ̀nà ààfin ọba lọ́wọ́.
Te dongah te rhoek yueng la manghai Rehoboam loh rhohum photling a saii tih manghai im kah thohka aka tawt, imtawt mangpa kut ah a khueh.
11 Ìgbàkígbà tí ọba bá lọ sí ilé Olúwa, àwọn olùṣọ́ n lọ pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n ń gbé àwọn àpáta náà àti lẹ́yìn, wọ́n dá wọn padà sí yàrá ìṣọ́.
Manghai te BOEIPA im la a caeh dingdoeng vaengah imtawt rhoek khaw cet uh tih photling te a bai uh. Te phoeiah imtawt kah tanhnaem la a thak uh.
12 Nítorí ti Rehoboamu rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, ìbínú Olúwa yí padà kúrò lórí rẹ̀, a kò sì pa á run pátápátá. Nítòótọ́, ìre díẹ̀ wà ní Juda.
Amah a kunyun van dongah BOEIPA kah thintoek khaw anih lamloh mael tih a bawtnah hil phae pawh. Tedae Judah ah khaw ol then om pueng.
13 Ọba Rehoboamu fi ara rẹ̀ lélẹ̀ gidigidi ní Jerusalẹmu, ó sì tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí ọba. Ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógójì nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba fún ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ní Jerusalẹmu, ìlú ńlá tí Olúwa ti yàn jáde kúrò nínú gbogbo àwọn ẹ̀yà Israẹli ní èyí tí ó fẹ́ fi orúkọ rẹ̀ síbẹ̀. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Naama, ará Ammoni.
Manghai Rehoboam tah Jerusalem ah cak tih sawmli kum khat a lo ca hil manghai. Rehoboam a manghai van neh Jerusalem khopuei ah kum hlai rhih manghai. Te tah Israel koca boeih lamloh amah ming pahoi khueh ham ni BOEIPA loh a coelh. Rehoboam manu ming tah Ammoni Naamah ni.
14 O sì ṣe búburú, nítorí tí kò múra nínú ọkàn rẹ̀ láti wá Olúwa.
Tedae BOEIPA te toem hamla a lungbuei a cikngae pawt dongah boethae a saii.
15 Fún tí iṣẹ́ ìjọba Rehoboamu láti ìbẹ̀rẹ̀ dé ìparí, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé ìrántí ti Ṣemaiah wòlíì àti ti Iddo, aríran tí ó ní ṣe pẹ̀lú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá? Ìtẹ̀síwájú ogun jíjà sì wà láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu.
Rehoboam kah olka a kung neh a doong te tonghma Shemaiah olka, khohmu Iddo kah a khuui dongah Rehoboam kah caemtloek neh Jeroboam kah a tue boeih neh a daek uh moenih a?
16 Rehoboamu sun pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sin ín sínú ìlú ńlá ti Dafidi. Abijah ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Rehoboam khaw a napa rhoek taengla a khoem uh vaengah tah David khopuei ah a up uh. Te phoeiah a capa Abijah te anih yueng la manghai.

< 2 Chronicles 12 >