< 2 Chronicles 11 >

1 Nígbà tí Rehoboamu dé Jerusalẹmu, ó kó ilé Juda àti Benjamini jọ, ọ̀kẹ́ mẹ́sàn-án ènìyàn tí a yàn, tí wọ́n jẹ́ ológun, láti bá Israẹli jà kí ó lè mú ìjọba náà padà bọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀.
A HIKI o Rehoboama i Ierusalema, hoakoakoa ae la ia i ka ohana a Iuda a me Beniamina, hookahi haneri a me kanawalu tausani kanaka ui, he poe koa, e kaua aku i ka Iseraela, e hoihoi mai i ke aupuni ia Rehoboama.
2 Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Ṣemaiah ènìyàn Ọlọ́run wá wí pé,
A hiki mai ka olelo a Iehova ia Semaia, i ke kanaka o ke Akua, i mai la,
3 “Wí fún Rehoboamu ọmọ Solomoni ọba Juda, sí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ní Juda àti Benjamini,
E olelo aku oe ia Rehoboama i ke keiki a Solomona i ke alii o ka Iuda, a i ka poe mamo a Iseraela a pau ma Iuda a me Beniamina, e i aku,
4 ‘Èyí ní ohun tí Olúwa wí. Ẹ má ṣe gòkè lọ láti lọ jà pẹ̀lú arákùnrin yín, ẹ lọ sílé, gbogbo yín, nítorí ti ìṣe mi nìyí.’” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n tẹ̀lé ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, wọ́n sì padà sẹ́yìn láti yan lọ dojúkọ Jeroboamu.
Penei ka olelo a Iehova, Mai pii aku oukou, aole hoi oukou e kaua aku i ko oukou poe hoahanau; e hoi kela kanaka keia kanaka i kona hale iho; no ka mea, na'u aku neia mea: a lohe lakou a pau i ka olelo a Iehova, a hoi lakou mai ko lakou hele ana aku e kaua ia Ieroboama.
5 Rehoboamu ń gbe ní Jerusalẹmu ó sì kọ́ àwọn ìlú fún olódi ní Juda.
A noho iho la o Rehoboama ma Ierusalema, a kukulu iho la ia ma Iuda i na kulanakauhale paa i ka pa.
6 Bẹtilẹhẹmu, Etamu, Tekoa,
Kukulu iho la oia ia Betelehema, a me Etena, a me Tekoa.
7 Beti-Suri, Soko, Adullamu,
A me Betazura, a me Soko, a me Adulama,
8 Gati, Meraṣa Sifi,
A me Gata, a me Anaresa, a me Zipa,
9 Adoraimu, Lakiṣi, Aseka
A me Adoraima, a me Lakisa, a me Azeka,
10 Sora, Aijaloni, àti Hebroni. Wọ̀nyí ni àwọn ìlú ìdáàbòbò ní Juda àti Benjamini.
A me Zora, a me Aialona, a me Heberona, aia no ma Iuda, a ma Beniamina, he mau kulanakauhale paa i ka pa.
11 Ó sì mú àwọn ìlú olódi lágbára, ó sì fi àwọn balógun sínú wọn àti àkójọ oúnjẹ, àti òróró àti ọtí wáìnì.
A hoopaa iho la oia i na paakaua, a hoonoho aku la iloko olaila i na luna a me na ahu ai, a me ka aila, a me ka waina.
12 Àti ní olúkúlùkù ìlú ni ó fi asà àti ọ̀kọ̀ sí, ó sì mú wọn lágbára gidigidi, ó sì ní Juda àti Benjamini lábẹ́ rẹ̀.
A iloko o kela kulanakauhale keia kulanakauhale, waiho iho la ia i na palekaua, a me na ihe, hana iho la oia malaila a paa loa, a ia ia o Iuda a me Beniamina ma kona aoao.
13 Àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi, láti gbogbo ẹ̀yà wọn jákèjádò Israẹli wà ní ẹ̀bá rẹ̀.
A o na kahuna, a me na Levi iwaena o ka Iseraela a pau, hele mai lakou io na la, mai kauwahi o lakou a pau mai.
14 Àwọn ará Lefi fi ìgbèríko sílẹ̀, wọ́n sì wá sí Juda àti Jerusalẹmu nítorí Jeroboamu àti àwọn ọmọ rẹ̀, ti kọ̀ wọ́n sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àwọn àlùfáà Olúwa.
No ka mea, haalele ka poe Levi i na wahi o lakou, a me ko lakou hooiliua, a hele lakou i Iuda, a i Ierusalema, no ka mea, kipaku o Ieroboama a me kana mau keiki ia lakou mailoko aku o ka oihana kahuna no Iehova:
15 Ó sì yan àwọn àlùfáà tirẹ̀ fún àwọn ibi gíga wọ̀n-ọn-nì, àti fún àwọn ère òbúkọ, àti fún ẹgbọrọ màlúù tí ó ṣe.
A hoonoho oia nona i na kahuna, no na wahi kiekie, a no na kao, a no na keiki bipi ana i hana'i.
16 Àwọn tó wá láti gbogbo ẹ̀yà Israẹli tí wọ́n fi ọkàn wọn fún wíwá Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tẹ̀lé àwọn ará Lefi lọ sí Jerusalẹmu láti lọ rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run baba a wọn.
A mahope o keia mau mea, o ka poe a pau noloko o na ohana a pau o ka Iseraela i haawi aku i ko lakou mau naau e imi ia Iehova ke Akua o ka Iseraela, hele mai lakou i Ierusalema e mohai aku ia Iehova, i ke Akua o ko lakou poe kupuna.
17 Ó fún ìjọba Juda ní agbára, ó sì ti Rehoboamu ọmọ Solomoni lẹ́yìn fún ọdún mẹ́ta nítorí ọdún mẹ́ta ni wọ́n fi rìn ní ọ̀nà ti Dafidi àti Solomoni ní àkókò yí.
A hookupaa iho la lakou i ke aupuni o Iuda, a hookupaa no hoi ia Rehoboama i ke keiki a Solomona i na makahiki ekolu; no ka mea, i na makahiki ekolu, hele lakou ma ka aoao o Davida a me Solomona.
18 Rehoboamu fẹ́ Mahalati tí ó jẹ́ ọmọbìnrin ti ọmọkùnrin Dafidi Jerimoti bi àti ti Abihaili, ọmọbìnrin ti ọmọkùnrin Jese Eliabu bí.
A lawe iho la o Rehoboama i wahine nana, ia Mehalata, i ke kaikamahine a Ieremota, ke keiki a Davida, a me Abehaila, ke kaikamahine a Eliaba ke keiki a Iese.
19 Ó bí àwọn ọmọ fún un: Jeuṣi, Ṣemariah àti Sahamu.
A hanau mai oia nana i na keiki, o Ieusa, me Samaria, a me Zahama.
20 Nígbà náà, ó fẹ́ Maaka ọmọbìnrin Absalomu, tí ó bí Abijah fún Attai, Sisa àti Ṣelomiti.
A mahope iho, lawe oia ia Maaka i ke kaikamahine a Abesaloma; a hanau mai oia nana o Abiia, a me Atai, a me Ziza. a me Silomita.
21 Rehoboamu fẹ́ràn Maaka ọmọbìnrin Absalomu ju èyíkéyìí nínú àwọn ìyàwó rẹ̀ àti àwọn àlè rẹ̀ lọ. Ní gbogbo rẹ̀, ó ní ìyàwó méjìdínlógún àti ọgọ́ta àlè ọmọkùnrin méjìdínlọ́gbọ̀n àti ọgọ́ta ọmọbìnrin.
Aloha iho la o Rehoboama ia Maaka i ke kaikamahine a Abesaloma, mamua o kana mau wahine a pau, a me kana poe haiawahine; (no ka mea, aia no ia ia he umikumamawalu wahine, a me na haiawahine he kanaono; a hanau mai he iwakalua a me kumamawalu na keikikane, a me na kaikamahine he kanaono.)
22 Rehoboamu yan Abijah ọmọ Maaka láti jẹ́ olóyè ọmọ-aládé láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀, kí ó ba à lè ṣe é ní ọba.
Hoonoho iho la o Rehoboama ia Abiia i ke keiki a Maaka i luna mawaena o kona poe hoahanau, no ka hoalii aku ia ia.
23 Ó hùwà ọlọ́gbọ́n, nípa fí fọ́n díẹ̀ nínú àwọn ọmọ rẹ̀ jákèjádò ká àwọn agbègbè Juda àti Benjamini àti sí gbogbo àwọn ìlú ńlá olódi. Ó fún wọn ní ọ̀pọ̀ ohun tí wọ́n fẹ́, ó sì fẹ́ ọ̀pọ̀ ìyàwó fún wọn.
A hana maalea iho la oia, a hoonoho liilii ia i kana poe keiki ma na aina a pau o Iuda a me Beniamina, a iloko o na kulanakauhale a pau i paa i ka pa, a haawi aku oia ia lakou i ka ai a nui. Makemake iho la ia i na wahine he nui loa.

< 2 Chronicles 11 >