< 2 Chronicles 11 >

1 Nígbà tí Rehoboamu dé Jerusalẹmu, ó kó ilé Juda àti Benjamini jọ, ọ̀kẹ́ mẹ́sàn-án ènìyàn tí a yàn, tí wọ́n jẹ́ ológun, láti bá Israẹli jà kí ó lè mú ìjọba náà padà bọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Lihouboua: me da Yelusaleme moilai bai bagadega doaga: lalu, e da baligili noga: i dadi gagui dunu 180,000 agoane, amo Yuda amola Bediamini fi ilima gilisi. E da gegene, bu ga (north) Isala: ili fi ili bu ouligimusa: dawa: i.
2 Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Ṣemaiah ènìyàn Ọlọ́run wá wí pé,
Be Gode da Ea Sia: Alofesu dunu (balofede) Siema: ia ema amane sia: i,
3 “Wí fún Rehoboamu ọmọ Solomoni ọba Juda, sí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ní Juda àti Benjamini,
“Lihouboua: me amola Yuda amola Bediamini fi dunu huluane ilima amane sia: sima,
4 ‘Èyí ní ohun tí Olúwa wí. Ẹ má ṣe gòkè lọ láti lọ jà pẹ̀lú arákùnrin yín, ẹ lọ sílé, gbogbo yín, nítorí ti ìṣe mi nìyí.’” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n tẹ̀lé ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, wọ́n sì padà sẹ́yìn láti yan lọ dojúkọ Jeroboamu.
‘Dilia fidafa Isala: ili dunu ili mae doagala: ma! Dilia huluane diasuga masa! Hou da wali doaga: i amo da Na hanaiga doaga: i.” Ilia huluane da Hina Gode Ea hamoma: ne sia: i nabi dagoi, amola ilia diasuga buhagi.
5 Rehoboamu ń gbe ní Jerusalẹmu ó sì kọ́ àwọn ìlú fún olódi ní Juda.
Lihouboua: me da Yelusaleme ganodini esalu. Ea sia: beba: le, Yuda dunu da moilai bai bagade hagudu dedei, amo gagili sali: - Bedeleheme, Ida: me, Degoua, Bedese, Siougou, Adala: me, Ga: de, Malisia, Sife, A:doula: me, La: igisi, Asoga, Soula, A:idialone amola Hibalone.
6 Bẹtilẹhẹmu, Etamu, Tekoa,
7 Beti-Suri, Soko, Adullamu,
8 Gati, Meraṣa Sifi,
9 Adoraimu, Lakiṣi, Aseka
10 Sora, Aijaloni, àti Hebroni. Wọ̀nyí ni àwọn ìlú ìdáàbòbò ní Juda àti Benjamini.
11 Ó sì mú àwọn ìlú olódi lágbára, ó sì fi àwọn balógun sínú wọn àti àkójọ oúnjẹ, àti òróró àti ọtí wáìnì.
E da amo huluane gasawane gagili sali, amola afae afae ouligima: ne, ouligisu dunu ilegei. Afae afae amo ganodini, e da ha: i manu, olife susuligi amola waini hano lidili legei.
12 Àti ní olúkúlùkù ìlú ni ó fi asà àti ọ̀kọ̀ sí, ó sì mú wọn lágbára gidigidi, ó sì ní Juda àti Benjamini lábẹ́ rẹ̀.
Amola ea da da: igene ga: su amola goge agei, amo gagili sali moilai bai bagade ganodini lidili legei. E da Yuda fi amola Bediamini fi gasawane ouligima: ne agoane hamosu.
13 Àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi, láti gbogbo ẹ̀yà wọn jákèjádò Israẹli wà ní ẹ̀bá rẹ̀.
Gobele salasu dunu amola Lifai fi dunu, ilia da Isala: ili soge fisili, ga (south) Yuda sogega misi.
14 Àwọn ará Lefi fi ìgbèríko sílẹ̀, wọ́n sì wá sí Juda àti Jerusalẹmu nítorí Jeroboamu àti àwọn ọmọ rẹ̀, ti kọ̀ wọ́n sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àwọn àlùfáà Olúwa.
Lifai fi dunu da ilia ohe fi ilia ha: i nasu soge amola eno soge fisili, Yuda sogega amola Yelusaleme moilai bai bagadega misi. Bai hina bagade Yelouboua: me amola e bagia dunu da ilia Hina Godema gobele salasu hawa: hamomu logo ga: i dagoi.
15 Ó sì yan àwọn àlùfáà tirẹ̀ fún àwọn ibi gíga wọ̀n-ọn-nì, àti fún àwọn ère òbúkọ, àti fún ẹgbọrọ màlúù tí ó ṣe.
Yelouboua: me da hi hanaiga, gobele salasu dunu amo da ogogosu ‘gode’ amola wadela: i a: silibu amola ea loboga hamoi bulamagau mano gawali agoai, ilima nodone sia: ne gadosu hou ouligima: ne, ili ilegei.
16 Àwọn tó wá láti gbogbo ẹ̀yà Israẹli tí wọ́n fi ọkàn wọn fún wíwá Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tẹ̀lé àwọn ará Lefi lọ sí Jerusalẹmu láti lọ rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run baba a wọn.
Isala: ili fi huluane amoga, nowa da Isala: ili Hina Godema moloiwane fa: no bobogemusa: dawa: i, ilia da Isala: ili soge fisili, Lifai fi dunuma fa: no bobogele, Yelusalemega asi. Bai ilia da ilia aowalalia Hina Godema gobele salasu hou hamomusa: hanai galu.
17 Ó fún ìjọba Juda ní agbára, ó sì ti Rehoboamu ọmọ Solomoni lẹ́yìn fún ọdún mẹ́ta nítorí ọdún mẹ́ta ni wọ́n fi rìn ní ọ̀nà ti Dafidi àti Solomoni ní àkókò yí.
Amo dunu da Yuda fima gilisibiba: le, Yuda da gasa bagade ba: i. Ode udianaga, ilia da Soloumane egefe Lihouboua: me fuligala: i. Amola ilia da hina bagade Da: ibidi amola hina bagade Soloumane ela esalebe galu, amo defele, ilia da hahawane esalu.
18 Rehoboamu fẹ́ Mahalati tí ó jẹ́ ọmọbìnrin ti ọmọkùnrin Dafidi Jerimoti bi àti ti Abihaili, ọmọbìnrin ti ọmọkùnrin Jese Eliabu bí.
Lihouboua: me da Ma: ihala: de lai. Ma: ihala: de ea ada da Yelimode (Da: ibidi egefe). Ea ame da A: biha: ile (Ilaia: be idiwi amola Yesi ea aiya: ).
19 Ó bí àwọn ọmọ fún un: Jeuṣi, Ṣemariah àti Sahamu.
Lihouboua: me amola Ma: ihala: de elea dunu mano da Yeuse, Siemalaia amola Sa: iha: me.
20 Nígbà náà, ó fẹ́ Maaka ọmọbìnrin Absalomu, tí ó bí Abijah fún Attai, Sisa àti Ṣelomiti.
Fa: no, Lihouboua: me da Ma: iaga (A: basalome idiwi) amo lai. Eleagefelali da Abaidia, A:da: i, Sisa amola Siloumode.
21 Rehoboamu fẹ́ràn Maaka ọmọbìnrin Absalomu ju èyíkéyìí nínú àwọn ìyàwó rẹ̀ àti àwọn àlè rẹ̀ lọ. Ní gbogbo rẹ̀, ó ní ìyàwó méjìdínlógún àti ọgọ́ta àlè ọmọkùnrin méjìdínlọ́gbọ̀n àti ọgọ́ta ọmọbìnrin.
Lihouboua: me da udadafa 18 agoane lai amola gidisedagi uda 60 agoane lai. Egefelali idi da 28 agoane, amola idiwilali idi da 60 agoane. Hi dogolegeidafa uda da Ma: iaga.
22 Rehoboamu yan Abijah ọmọ Maaka láti jẹ́ olóyè ọmọ-aládé láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀, kí ó ba à lè ṣe é ní ọba.
Ma: iaga amola egefe Abaidia da Lihouboua: me ea dogolegeidafa. Amaiba: le, Lihouboua: me da Abaidia amo e bagia hina bagade hamoma: ne ilegei.
23 Ó hùwà ọlọ́gbọ́n, nípa fí fọ́n díẹ̀ nínú àwọn ọmọ rẹ̀ jákèjádò ká àwọn agbègbè Juda àti Benjamini àti sí gbogbo àwọn ìlú ńlá olódi. Ó fún wọn ní ọ̀pọ̀ ohun tí wọ́n fẹ́, ó sì fẹ́ ọ̀pọ̀ ìyàwó fún wọn.
Lihouboua: me da dawa: iwane hamonanusu. E da egefelali ilima hawa: hamosu ilegei. Ea sia: beba: le, ilia da Yuda amola Bediamini soge amola gagili sali moilai bai bagade, amo ganodini ouligisu hawa: hamosu. E da liligi bagade ilima i, amola ilia lama: ne, uda bagohame ilima i.

< 2 Chronicles 11 >