< 2 Chronicles 10 >

1 Rehoboamu sì lọ sí Ṣekemu nítorí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ti lọ síbẹ̀ láti fi jẹ ọba.
Na ka haere a Rehopoama ki Hekeme: kua tae mai hoki a Iharaira katoa ki Hekeme ki te whakakingi i a ia.
2 Nígbà tí Jeroboamu ọmọ Nebati gbọ́ ẹni ti ó wà ní Ejibiti, níbi tí ó ti sá kúrò lọ́dọ̀ ọba Solomoni ó sì padà láti Ejibiti.
A, no te rongonga o Ieropoama tama a Nepata; i Ihipa hoki ia, i rere hoki ki reira i te aroaro o Kingi Horomona; na hoki mai ana a Ieropoama i Ihipa.
3 Bẹ́ẹ̀ ni nígbà náà ó sì ránṣẹ́ sí Jeroboamu àti òun àti gbogbo àwọn Israẹli lọ sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu wọ́n sì wí fún pé,
Na ka tono tangata ratou ki te tiki i a ia. A ka haere a Ieropoama ratou ko Iharaira katoa, ka korero ki a Rehopoama, ka mea,
4 “Baba rẹ gbé àjàgà tí ó wúwo lórí wa, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ mú un fúyẹ́, iṣẹ́ líle àti àjàgà wúwo tí ó gbé ka orí wa, àwa yóò sì sìn ọ́.”
He pakeke te ioka i meatia e tou papa ki a matou: na mau e whakamama ake te mahi pakeke a tou papa me tana ioka taimaha i meatia e ia ki a matou, a ka mahi matou ki a koe.
5 Rehoboamu sì dáhùn pé, “Ẹ padà wá sọ́dọ̀ mi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta.” Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn náà sì lọ.
Na ka mea ia ki a ratou, Kia toru ra, ka hoki mai ki ahau. Na haere ana te iwi.
6 Nígbà náà ni ọba Rehoboamu fi ọ̀ràn lọ̀ àwọn àgbàgbà tí ó ti ń sin baba rẹ̀ Solomoni nígbà ayé rẹ̀, ó sì bi wọ́n léèrè pe, “Báwo ni ẹ̀yin yóò ṣe gbà mí ní ìmọ̀ràn láti dá àwọn ènìyàn wọ̀nyí lóhùn?”
Na ka runanga a Kingi Rehopoama ki nga kaumatua i tu i te aroaro o tona papa, o Horomona, i a ia i te ora, ka mea, Ki to koutou whakaaro me pehea te kupu e whakahokia e ahau ki tenei iwi?
7 Wọ́n sì dáhùn, “Tí ìwọ yóò bá ṣe rere sí àwọn ènìyàn wọ̀nyí kí o sì ṣe ìre fún wọn, kí o sì fún wọn ní ìdáhùn rere, wọn yóò sì máa jẹ́ ìránṣẹ́ rẹ nígbà gbogbo.”
Na ka korero ratou ki a ia, ka mea, Ki te mea ka pai tau ki tenei iwi, a ka whakamanawareka koe i a ratou, a ka pai nga korero e korerotia e koe ki a ratou, na ko ratou hei pononga mau i nga ra katoa.
8 Ṣùgbọ́n Rehoboamu kọ ìmọ̀ràn náà tí àwọn àgbàgbà fi fún un, ó sì fi ọ̀rọ̀ lọ àwọn ọmọ ọkùnrin tí ó ti dàgbàsókè pẹ̀lú rẹ̀ tí wọ́n sì ń dúró níwájú rẹ̀.
Otiia whakarerea ake e ia te whakaaro i whakatakotoria mana e nga kaumatua, a runanga ana ki nga taitama i kaumatua ngatahi nei me ia, i tu nei ki tona aroaro.
9 Ó sì béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Kí ni ìmọ̀ràn yín? Báwo ni kí a ṣe dá àwọn ènìyàn wọ̀nyí tí wọ́n wí fún mi pé, ‘Mú kí àjàgà tí baba rẹ gbé lé wa kí ó fúyẹ́ díẹ̀.’”
I mea ia ki a ratou, Ki to koutou whakaaro me pehea te kupu e whakahokia e tatou ki tenei hunga i korero mai nei ki ahau, i mea mai nei, Whakamamakia ake te ioka i meatia e tou papa ki a matou?
10 Àwọn ọ̀dọ́mọdé tí ó ti dàgbà pẹ̀lú rẹ dá a lóhùn pé, “Sọ fún àwọn ènìyàn tí ó wí fún ọ wí pé, ‘Baba rẹ gbé àjàgà wúwo lórí wa, ṣùgbọ́n mú àjàgà wa fúyẹ́,’ wí fún wọn pé, ‘Ìka ọwọ́ mi kékeré, ó nípọn ju ìbàdí baba mi lọ.
Na ka korero ki a ia nga taitama i kaumatua ngatahi nei me ia, ka mea, Kia penei tau ki atu ki tenei hunga i korero mai nei ki a koe, i mea mai nei, I whakataimahatia e tou papa to matou ioka, na kia mama tau ki a matou; kia penei tau ki atu ki a ratou, ko toku maihao iti, ka nui atu i te hope o toku papa.
11 Baba mi gbé àjàgà wúwo ka orí yín; èmi yóò sì tún mú kí ó wúwo sì í. Baba mi fi pàṣán nà yín; èmi yóò sì nà yín pẹ̀lú àkéekèe.’”
Na, i whakawaha e toku papa he ioka taimaha ki a koutou, ka tapiritia e ahau tetahi atu mea ki to koutou ioka; he wepu ta toku papa i whiu ai i a koutou, otiia ka whiua koutou e ahau ki te kopiona.
12 Ní ọjọ́ kẹta Jeroboamu àti gbogbo ènìyàn sì padà sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu, gẹ́gẹ́ bí ọba ti sọ, “Ẹ padà wá sọ́dọ̀ mi ní ọjọ́ kẹta.”
Heoi kua tae a Ieropoama ratou ko te iwi katoa ki a Rehopoama i te toru o nga ra; ko ta te kingi hoki tena i korero ai, i a ia i mea ra, Hoki mai ki ahau i te toru o nga ra.
13 Nígbà náà ni ọba dá wọn lóhùn ní ọ̀nà líle. Rehoboamu ọba sì kọ̀ ìmọ̀ràn àwọn àgbàgbà sílẹ̀,
A pakeke tonu ta te kingi i whakahoki ai ki a ratou; whakarerea ake e Rehopoama te whakaaro o nga kaumatua,
14 Ó sì tẹ̀lé ìmọ̀ràn àwọn ọ̀dọ́mọdé, ó sì wí pé, “Baba mi mú kí àjàgà yín wúwo; èmi yóò sì mú kí ó wúwo jù bẹ́ẹ̀ lọ. Baba mi nà yín pẹ̀lú pàṣán; èmi yóò sì nà yín pẹ̀lú àkéekèe.”
Ka korero ki a ratou i runga i to nga taitama whakaaro, a ka mea, I whakataimahatia to koutou ioka e toku papa, heoi ka tapiritia atu ano e ahau: i whiua koutou e toku papa ki te wepu, ka whiua ia koutou e ahau ki te kopiona.
15 Bẹ́ẹ̀ ni ọba kò sì fetísí àwọn ènìyàn, nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ni. Láti mú ọ̀rọ̀ Olúwa ṣẹ tí a ti sọ fún Jeroboamu ọmọ Nebati nípasẹ̀ Ahijah ará Ṣilo.
Heoi kihai i rongo te kingi ki ta te iwi; na te Atua hoki te take, kia mana ai tana kupu i korero ai a Ihowa, na te mangai o Ahia Hironi ki a Ieropoama tama a Nepata.
16 Nígbà tí gbogbo Israẹli rí i wí pé ọba kọ̀ láti gbọ́ tiwọn, wọ́n sì dá ọba lóhùn wí pé, “Ìpín kí ní a ní nínú Dafidi, ìní wo ni a ní nínú ọmọ Jese? Ẹ lọ sí àgọ́ yín, ẹ̀yin Israẹli! Bojútó ilé rẹ, ìwọ Dafidi!” Bẹ́ẹ̀ ní gbogbo àwọn ọmọ Israẹli lọ sí ilé wọn.
A, no te kitenga o Iharaira katoa kihai te kingi i rongo ki ta ratou, ka utua e te iwi te kingi; ka mea ratou, Ko te aha ianei to matou wahi i a Rawiri? kahore nei hoki o tatou wahi tupu i te tama a Hehe: ki o koutou teneti, e Iharaira! na kia w hai kanohi koe ki tou whare, e Rawiri! Heoi haere ana a Iharaira katoa ki tona teneti, ki tona teneti.
17 Ṣùgbọ́n ní ti àwọn ọmọ Israẹli tí ń gbé ní ìlú Juda, Rehoboamu ń jẹ ọba lórí wọn.
Ko nga tama ia a Iharaira e noho ana i nga pa o Hura, ko Rehopoama i kingi mo ratou.
18 Ọba Rehoboamu rán Adoniramu jáde, ẹni tí ó wà ní ìkáwọ́ iṣẹ́ onírúurú, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli sọ ọ́ ní òkúta pa. Ọba Rehoboamu, gbìyànjú láti dé inú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ ó sì sálọ sí Jerusalẹmu.
Katahi ka tono a Kingi Rehopoama i te rangatira takoha, i a Harorama; a akina ana ia e nga tama a Iharaira ki te kohatu, a mate iho. Na hohoro tonu te eke o Kingi Rehopoama ki tona hariata, a rere ana ki Hiruharama.
19 Bẹ́ẹ̀ ni Israẹli sì wà ní ìṣọ̀tẹ̀ lórí ilé Dafidi títí fi di òní yìí.
Heoi whakakeke ana a Iharaira ki te whare o Rawiri, a taea noatia tenei ra.

< 2 Chronicles 10 >