< 1 Timothy 2 >
1 Nítorí náà mo gbà yín níyànjú ṣáájú ohun gbogbo, pé kí a máa bẹ̀bẹ̀, kí a máa gbàdúrà, kí a máa ṣìpẹ̀, àti kí a máa dúpẹ́ nítorí gbogbo ènìyàn.
Gorąco zachęcam was do modlitwy za wszystkich ludzi. Proście i błagajcie Boga, aby im pomagał i dziękujcie Mu za nich.
2 Fún àwọn ọba, àti gbogbo àwọn tí ó wà ni ipò àṣẹ, kí a lè máa lo ayé wa ní àlàáfíà àti ìdákẹ́ jẹ́ẹ́ pẹ̀lú nínú gbogbo ìwà-bí-Ọlọ́run àti ìwà mímọ́.
Módlcie się również za rządzących i wszystkich sprawujących władzę, abyśmy mogli żyć w pokoju, zachowując godność i oddając chwałę Panu.
3 Nítorí èyí dára, ó sì ṣe ìtẹ́wọ́gbà níwájú Ọlọ́run Olùgbàlà wa;
Takie postępowanie jest dobre i podoba się Bogu, naszemu Zbawicielowi,
4 ẹni tí ó fẹ́ kí gbogbo ènìyàn ní ìgbàlà kí wọ́n sì wá sínú ìmọ̀ òtítọ́.
który pragnie zbawić i doprowadzić do prawdy wszystkich ludzi.
5 Nítorí Ọlọ́run kan ní ń bẹ, onílàjà kan pẹ̀lú láàrín Ọlọ́run àti ènìyàn, àní Kristi Jesu ọkùnrin náà.
Istnieje bowiem tylko jeden Bóg i jeden pośrednik między Nim a ludźmi: Człowiek—Chrystus Jezus.
6 Ẹni ti ó fi ara rẹ̀ ṣe ìràpadà fún gbogbo ènìyàn—ẹ̀rí tí a fi fún ni ní àkókò tó yẹ.
To On złożył siebie jako okup za wszystkich ludzi. We właściwym czasie prawda ta została oznajmiona światu.
7 Nítorí èyí tí a yàn mi ṣe oníwàásù, aposteli òtítọ́ ni èmi ń sọ, èmi kò ṣèké olùkọ́ àwọn aláìkọlà nínú ìgbàgbọ́ àti òtítọ́.
Mnie zaś Bóg wybrał na apostoła i nakazał mi głosić tę nowinę poganom, nauczając ich wiary i prawdy. Jest to prawdziwe Boże powołanie. Mówiąc o tym, nie kłamię.
8 Mo fẹ́ kí àwọn ọkùnrin máa gbàdúrà níbi gbogbo, kí wọ́n máa gbé ọwọ́ mímọ́ sókè, ní àìbínú àti àìjiyàn.
Proszę więc, aby na spotkaniach mężczyźni modlili się wznosząc ku Bogu czyste ręce i mając serca wolne od gniewu oraz złości na innych ludzi.
9 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni kí àwọn obìnrin fi aṣọ ìwọ̀ntúnwọ̀nsì ṣe ara wọn ní ọ̀ṣọ́, ní ìwọ̀ntúnwọ̀nsì àti pẹ̀lú ìwà àìrékọjá; kì í ṣe pẹ̀lú irun dídì, tàbí wúrà, tàbí peali, tàbí aṣọ olówó iyebíye,
Kobiety zaś, przychodząc na spotkania, niech się odpowiednio ubierają—skromnie i niewyzywająco. Niech nie zwracają na siebie uwagi fryzurą, biżuterią czy modnymi ubraniami.
10 bí kò ṣe pẹ̀lú iṣẹ́ rere, èyí tí ó yẹ fún àwọn obìnrin tó jẹ́wọ́ pé wọ́n sin Ọlọ́run.
Prawdziwą ozdobą kobiet, które kochają Boga, powinno być bowiem dobre postępowanie.
11 Jẹ́ kí obìnrin máa fi ìdákẹ́ jẹ́ẹ́ àti ìtẹríba gbogbo kọ́ ẹ̀kọ́.
Na spotkaniach niech słuchają i uczą się w pokoju i uległości.
12 Ṣùgbọ́n èmi kò fi àṣẹ fún obìnrin láti máa kọ́ni, tàbí láti pàṣẹ lórí ọkùnrin, bí kò ṣe kí ó dákẹ́ jẹ́ẹ́.
Nie zgadzam się, aby nauczały i rządziły swoimi mężami, ale niech zachowują pokój.
13 Nítorí Adamu ni a kọ́ dá, lẹ́yìn náà, Efa.
To Adam został bowiem stworzony jako pierwszy, nie Ewa.
14 Adamu kọ́ ni a tànjẹ, ṣùgbọ́n obìnrin náà ni a tàn tí ó sì di ẹlẹ́ṣẹ̀.
I nie on został oszukany przez szatana, lecz Ewa—to ona bowiem zgrzeszyła jako pierwsza.
15 Ṣùgbọ́n a ó gbà àwọn obìnrin là nípa ìbímọ wọn, bí wọ́n bá dúró nínú ìgbàgbọ́, ìfẹ́, àti ìwà mímọ́ pẹ̀lú ìwà àìrékọjá.
Kobiety dostąpią jednak zbawienia poprzez macierzyństwo, jeśli będą wierzyć Chrystusowi, okazywać innym miłość oraz prowadzić czyste i skromne życie.