< 1 Samuel 1 >

1 Ọkùnrin kan wà, láti Ramataimu-Sofimu, láti ìlú olókè Efraimu, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Elkana, ọmọ Jerohamu, ọmọ Elihu, ọmọ Tohu, ọmọ Sufu, ará Efrata.
Goumi soge amoga Ifala: ime fifi lai dunu ilia da La: ima moilaiga fi dialu. Amogai dunu afae Elega: ina esalu. E da Yilouha: me ea mano, amola ea aowa da Ilaihu galu. Ea sosogo fi da Douhu fi amoga galu, be fidafa da Safe.
2 Ó sì ní ìyàwó méjì, orúkọ wọn ni Hana àti Penina: Penina ní ọmọ, ṣùgbọ́n Hana kò ní.
Elega: ina da uda aduna lai galu. Elea dio da Ha: na amola Binina. Binina da mano gilisi galu, be Ha: na da aligime esalu.
3 Ní ọdọọdún, ọkùnrin yìí máa ń gòkè láti ìlú rẹ̀ láti lọ sìn àti láti ṣe ìrúbọ sí Olúwa àwọn ọmọ-ogun jùlọ ní Ṣilo, níbi tí àwọn ọmọkùnrin Eli méjèèjì, Hofini àti Finehasi ti jẹ́ àlùfáà Olúwa.
Elega: ina da ode huluane Siailou moilaiga Hina Gode Bagadedafa Ema nodone sia: ne gadomusa: , amola gobele sala ahoasu. Amogawi, Ilai ea mano aduna amo Hofenai amola Finia: se da Hina Gode Ea gobele salasu ouligisu dunu esalu.
4 Nígbàkígbà tí ó bá kan Elkana láti ṣe ìrúbọ, òun yóò bù lára ẹran fún aya rẹ̀ Penina àti fún gbogbo àwọn ọmọ ọkùnrin àti obìnrin.
Elega: ina da ea gobele salasu liligi ianoba, e da heda: sini na: iyadodi afae Bininama iasu, amola eno afae Binina ea manogili sagosu.
5 Ṣùgbọ́n ó máa ń pín ìlọ́po fun Hana nítorí pé ó fẹ́ràn rẹ̀ àti pé Olúwa ti sé e nínú.
Elega: ina da Ha: na ema bagade asigisu, be amomane ema heda: sini afae afae fawane ianusu. Bai Hina Gode da Ha: na ema mano hame i.
6 Nítorí pé Olúwa ti sé e nínú, orogún rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí ní fín níràn láti lè mú kí ó bínú.
Binina da Ha: na ema hame asigisu. E da Ha: na ema da: da: losu. Bai Hina Gode da Ha: na aligime hamonesi, e da Ha: nama da: da: losu.
7 Eléyìí sì máa ń ṣẹlẹ̀ ní ọdọọdún. Nígbàkígbà tí Hana bá gòkè lọ sí ilé Olúwa, orogún rẹ̀ a máa fín níràn títí tí yóò fi máa sọkún tí kò sì ní lè jẹun.
Amanemusu hamonana ode bagohame gidigisa asi. Ilia da Hina Gode Ea diasuga ahoanoba, Binina da Ha: na da: i dioma: ne gadesu amola da: da: losu hamobeba: le, Ha: na bagadewane da: i dione amola disu amola ha: i manu gobei amoga hamedafa nasu.
8 Elkana ọkọ rẹ̀ yóò sọ fún un pé, “Hana èéṣe tí ìwọ fi ń sọkún? Èéṣe tí ìwọ kò fi jẹun? Èéṣe tí ìwọ fi ń ba ọkàn jẹ́? Èmi kò ha ju ọmọ mẹ́wàá lọ fún ọ bí?”
Be egoa Elega: ina da Ha: nama agoane adole ba: su, “Ha: na! Abuliba: le di da dinana amola ha: i manu gobei hame nahala: ? Abuliba: le di da eso huluane da: i dioiwane ba: sala: ? Di da nama asigi hou da dunu mano nabuane gala ilima asigi hou da hame baligiyale dawa: bela: ?”
9 Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n ti jẹ, tí wọ́n tún mu tán ní Ṣilo, Hana dìde wá síwájú Olúwa. Nígbà náà, Eli àlùfáà wà lórí àga ní ẹ̀gbẹ́ ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa ní ibi tí ó máa ń jókòó.
Eso afaega, Hina Gode Ea diasu Siailou moilaiga amo ganodini ha: i nanu fisiagale, Ha: na da wa: legadole, e da bagade da: i dione amola Hina Godema sia: ne gadosa ha: gidafa dinanu. Amogalu, gobele salasu ouligisu dunu Ilai da logo holei gadenenewane hi fisu fafai da: iya esalu.
10 Pẹ̀lú ẹ̀dùn ọkàn Hana sọkún gidigidi, ó sì gbàdúrà sí Olúwa.
11 Ó sì jẹ́ ẹ̀jẹ́ wí pé, “Olúwa àwọn ọmọ-ogun, jùlọ tí ìwọ bá le bojú wo ìránṣẹ́bìnrin rẹ kí ìwọ sì rántí rẹ̀, tí ìwọ kò sì gbàgbé ìránṣẹ́ rẹ ṣùgbọ́n tí ìwọ yóò fún un ní ọmọkùnrin, nígbà náà èmi yóò sì fi fún Olúwa ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ a kì yóò sì fi abẹ kàn án ní orí.”
Ha: na da Hina Godema amane ilegele sia: i, “Hina Gode Bagadedafa! Nama ba: ma! Na da Dia hawa: hamosu uda! Na da: i dioi ba: ma, amola na mae gogolema! Dia nagili mano ima! Amasea, amo mano na da Dima bu mogili gagale imunu, amalu ea dialuma hinabo hamedafa damunisimu.”
12 Bí ó sì ṣe ń gbàdúrà sí Olúwa, Eli sì kíyèsi ẹnu rẹ̀.
Ha: na da agoane Hina Godema sia: ne gadosa aligili bagadewane sia: ne gadolalusu. Amola Ilai da Ha: na ea lafi sosodolalu.
13 Hana ń gbàdúrà láti inú ọkàn rẹ̀, ṣùgbọ́n ètè rẹ̀ ni ó ń mì, a kò gbọ́ ohùn rẹ̀. Eli rò wí pé ó ti mu ọtí yó.
Ha: na da sadoga sia: ne gadosu. Ea lafi da fafudalu be sia: da hame nabi. Amaiba: le, Ilai da amo uda adini nanu, feloabeyale dawa: lu,
14 Eli sì wí fún un pé, “Yóò ti pẹ́ fún ọ tó tí ìwọ yóò máa yó? Mú ọtí wáìnì rẹ̀ kúrò.”
amola Ha: nama amane sia: i, “Yolema! Adini nanu di dunu eno ilia ba: ma: ne mae hidama. Adini nanu yolesili, bu gahegima.”
15 Hana dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, Olúwa mi, èmi ni obìnrin oníròbìnújẹ́. Èmi kò mu ọtí wáìnì tàbí ọtí líle; èmi ń tú ọkàn mi jáde sí Olúwa ni.
Ha: na da bu adole i, “Esega! Na da we adini maiga hame feloasa. Na da hiawini, na da: i dioi huluane Hina Godema olelelala.
16 Má ṣe mú ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí obìnrin búburú. Èmi ti ń gbàdúrà níhìn-ín nínú ìrora ọkàn àti ìbànújẹ́ mi.”
Na da hamedei udayale mae dawa: ma. Na agoane sia: ne gadoi. Bai na bagade da: i dioiba: le fawane, agoane sia: ne gadoi.”
17 Eli dáhùn pé, “Máa lọ ní àlàáfíà, kí Ọlọ́run Israẹli fi ohun tí ìwọ ti béèrè ní ọwọ́ rẹ̀ fún ọ.”
Ilai da amane sia: i, “Hahawane masa! Amola Isala: ili Gode da dia hanai adole ba: i liligi dima imunu da defea.”
18 Ó wí pé, “Kí ìránṣẹ́bìnrin rẹ rí oore-ọ̀fẹ́ lójú rẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni obìnrin náà bá tirẹ̀ lọ, ó sì jẹun, kò sì fa ojú ro mọ́.
Ha: na da bu adole i, “Di da eso huluane nama asabole dawa: lumu da defea.” Amalalu, e da asili, ha: i nanu, ea da: i dioi fisi dagoi ba: i.
19 Wọ́n sì dìde ni kùtùkùtù òwúrọ̀, wọn wólẹ̀ sìn níwájú Olúwa, wọn padà wa sí ilé wọn ni Rama: Elkana si mọ Hana aya rẹ̀: Olúwa sì rántí rẹ̀.
Amalu, golale hahabedafa, Elega: ina amola ea sosogo huluane da wa: legadole, Hina Godema nodone sia: ne gadolalu, ili La: ima moilaiga buhagi. Elega: ina da idua Ha: nala gilisili golai, amola Hina Gode da Ha: na ea sia: ne gadoi adole ba: i defele ema i.
20 Ó sì ṣe, nígbà tí ọjọ́ rẹ̀ pé, lẹ́yìn ìgbà tí Hana lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Samuẹli, pé, “Nítorí tí mo béèrè rẹ̀ lọ́wọ́ Olúwa.”
Amalu, Ha: na da abula agui esalu, dunu mano lalelegei. Ha: na da ea mano ea dio Sa: miuele asuli. Sa: miuele amo dawa: loma: ne da “Na da e lama: ne, Hina Godema adole ba: i.”
21 Ọkùnrin náà Elkana, àti gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, gòkè lọ láti rú ẹbọ ọdún sí Olúwa, àti láti sán ẹ̀jẹ́ rẹ̀.
Elega: ina amola ea sosogo fi ilia da odegamusu Siailou moilaiga Godema gobele sala ahoasu, be amo eso da doaga: iba: le, e da liligi eno ida: iwane galamusu Godema gobele salimusa: ilegei.
22 Ṣùgbọ́n Hana kò gòkè lọ; nítorí tí ó sọ fún ọkọ rẹ̀ pé, “Ó di ìgbà tí mo bá gba ọmú lẹ́nu ọmọ náà, nígbà náà ni èmi yóò mú un lọ, kí òun lè fi ara hàn níwájú Olúwa, kí ó sí máa gbé ibẹ̀ títí láé.”
Be amo asi amoga Ha: na da hame asi. E da egoama amane sia: i, “Na mano da dodo nanu yolesea, na da Hina Gode Ea diasuga asula masunu. Amogai e da eso huluane esaloma: ne.”
23 Elkana ọkọ rẹ̀ sì wí fún un pé, “Ṣe èyí tí ó tọ́ lójú rẹ. Dúró títí ìwọ yóò fi gba ọmú lẹ́nu rẹ̀; ṣùgbọ́n kí Olúwa sá à mú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni obìnrin náà sì jókòó, ó sì fi ọmú fún ọmọ rẹ̀ títí ó fi gbà á lẹ́nu rẹ̀.
Amalalu, Elega: ina da bu adole i, “Defea! Dia hanai habo da defea galea amo hamoma. Diasua esala, dodo nanusu yolesea fawane Gode Ea diasuga masa. Amola Hina Gode da dia ilegele mogili gagai sia: i amo dafawane hamomu da defea.” Amaiba: le, Ha: na da diasua esalu, mano ouligilalu.
24 Nígbà tí ó sì gba ọmú lẹ́nu rẹ̀, ó sì mú un gòkè lọ pẹ̀lú ara rẹ̀. Pẹ̀lú ẹgbọrọ màlúù mẹ́ta, àti ìyẹ̀fun efa kan, àti ìgò ọtí wáìnì kan, ó sì mú un wá sí ilé Olúwa ní Ṣilo: ọmọ náà sì wà ní ọmọdé.
Ha: na da manoma dodo ianu yolei galu, e da Sa: miuele Siailou moilaiga oule asi. Amogai e da bulamagau gawali ode udiana gidigi adole amola agi10 gilogala: me agoane amola ohe gadofoga hamoi esaga waini hano dili sali amo gaguli asi.
25 Wọ́n pa ẹgbọrọ màlúù, wọ́n sì mú ọmọ náà tọ Eli wá.
Ili da bulamagau fane ligisilalu, mano amo oule Ilaima asi.
26 Hana sì wí pé, “Olúwa mi, bí ọkàn rẹ ti wà láààyè, Olúwa mi, èmi ni obìnrin náà tí ó dúró lẹ́bàá ọ̀dọ̀ rẹ níhìn-ín tí ń tọrọ lọ́dọ̀ Olúwa.
Ha: na da Ilaima amane sia: i, “Ae esega! Dia da na dawa: bela: ? Na da uda musa: dia ba: i gui Hina Godema sia: ne gadosa lelebe ba: i.
27 Ọmọ yìí ni mo ń tọrọ; Olúwa sì fi ìdáhùn ìbéèrè tí mo béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀ fún mi.
Na da goe mano nama ima: ne Hina Godema adole ba: lalu, amaiba: le E da nagili mano i amo wea.
28 Nítorí náà pẹ̀lú, èmi fi í fún Olúwa; ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀: nítorí tí mo ti béèrè rẹ̀ fún Olúwa.” Wọn si wólẹ̀ sin Olúwa níbẹ̀.
Amaiba: le, na da amo mano Hina Godema ia misi. Amalu ea fifi ahoanusu huluane da Hina Gode Hifawane da ouligilalumu,” Ha: na da amane sia: i. Amalu, ilia da goega gilisili Hina Godema nodone sia: ne gadoi.

< 1 Samuel 1 >