< 1 Samuel 6 >

1 Nígbà tí àpótí ẹ̀rí Olúwa sì ti wà ní agbègbè Filistini fún oṣù méje,
Perwerdigarning ehde sanduqi Filistiylerning yurtida yette ay turdi.
2 àwọn ará Filistini pe àwọn àlùfáà, àti àwọn alásọtẹ́lẹ̀, wọ́n sì sọ pé, “Kí ni kí a ṣe pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Olúwa? Sọ fún wa bí àwa yóò ti dá a padà sí ààyè rẹ̀.”
Filistiyler kahinlar bilen palchilarni chaqirip ulargha: — Perwerdigarning ehde sanduqini qandaq qilimiz? Uni qandaq qilip öz jayigha eweteleymiz? Yol körsitinglar, dédi.
3 Wọ́n dáhùn wí pé, “Tí ẹ bá dá àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run ti àwọn ọmọ Israẹli padà, ẹ má ṣe dá a padà ní òfìfo, ṣùgbọ́n bí ó ti wù kí ó rí, ẹ fún un ní ẹbọ ẹ̀bi. Nígbà náà ni a ó mú un yín láradá, ẹ̀yin yóò sì mọ ìdí tí ọwọ́ rẹ̀ kò fi tí ì kúrò lára yín.”
Ular: — Eger Israilning Xudasining ehde sanduqini qayturup ewetsenglar, quruq ewetmenglar, héch bolmighanda uning bilen bir «itaetsizlik qurbanliqi»ni birge ewetishinglar zörürdur, dédi. Shundaq qilghanda shipa tapisiler, shundaqla Uning qolining néme üchün silerdin ayrilmighanliqini bilisiler, dédi.
4 Àwọn ará Filistini béèrè pé, “Irú ẹbọ ẹ̀bi wo ni kí a fi fún un?” Wọ́n dáhùn, “Wúrà oníkókó márùn-ún àti eku ẹ̀lírí wúrà márùn-ún, gẹ́gẹ́ bí iye àwọn aláṣẹ Filistini, nítorí àjàkálẹ̀-ààrùn kan náà ni ó kọlù yín àti olórí yín.
Ular: — Biz némini itaetsizlik qurbanliqi qilip ewetimiz? — dep soridi. Ular: — Filistiylerning ghojilirining sani besh; shunga besh altun hürrek we besh altun chashqan yasap ewetinglar; chünki silerge we ghojanglargha oxshashla bala-qaza chüshti.
5 Mọ àwòrán ààrùn oníkókó àti ti eku ẹ̀lírí yin tí ó ń ba orílẹ̀-èdè náà jẹ́ kí o sì bu ọlá fún Ọlọ́run Israẹli. Bóyá yóò gbé ọwọ́ rẹ̀ kúrò lára yín, lára ọlọ́run yín àti lára ilẹ̀ yín.
Hürrekliringlarning sheklini we zémininglarni weyran qilidighan chashqanlarning sheklini neqish qilip yasap, Israilning Xudasigha shan-sherep keltürünglar. Shuning bilen u belkim silerning, ilahlirimizning we zémininglarning üstini basqan qolini yéniklitermikin: —
6 Kí ni ó dé tí ẹ fi ń sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí àwọn ará Ejibiti àti Farao ti ṣe? Nígbà tí ó fi ọwọ́ líle mú wọn, ṣé wọn kò rán àwọn ọmọ Israẹli jáde kí wọn kí ó lè lọ ní ọ̀nà wọn?
Misirliqlar bilen Pirewn öz köngüllirini qattiq qilghandek silermu némishqa öz könglünglarni qattiq qilisiler? U misirliqlargha zor qattiq qolluq körsetkendin kéyin, ular Israillarni qoyup bermidimu, ular shuning bilen qaytip kelmidimu?
7 “Nísinsin yìí ẹ pèsè kẹ̀kẹ́ ẹrù tuntun sílẹ̀, pẹ̀lú màlúù méjì tí ó ti fi ọmú fún ọmọ, èyí tí a kò tí ì gba àjàgà sí ọrùn rí, kí ẹ sì so ó mọ́ kẹ̀kẹ́ náà, kí ẹ sì mú ọmọ wọn kúrò lọ́dọ̀ wọn wá sí ilé láti so.
Emdi yéngi bir harwa yasap, téxi boyunturuqqa köndürülmigen mozayliq ikki inekni harwigha qoshunglar; ulardin mozaylirini ayrip, öyde élip qélinglar;
8 Kí ẹ sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa sí orí kẹ̀kẹ́ ẹrù àti kí ẹ̀yin sì kó àwọn ohun èlò wúrà tí ẹ̀yin fi fún un gẹ́gẹ́ bí ti ẹbọ ẹ̀bi sí inú àpótí ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, kí ẹ̀yin kí ó sì rán an lọ,
andin Perwerdigarning ehde sanduqini kötürüp harwigha sélinglar; we uninggha ewetidighan itaetsizlik qurbanliqi qilidighan altun buyumlarni bir qapqa sélip sanduqqa yandap qoyunglar we sanduqni shu péti mangdurunglar;
9 ṣùgbọ́n kí ẹ sì máa ṣọ́ ọ. Tí ó bá ń lọ sí ilẹ̀ rẹ̀, ìlú rẹ̀, níhà Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà ni Olúwa mú àjálù ńlá yìí bá wa. Ṣùgbọ́n bí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀ nígbà náà ni a mọ̀ pé kì í ṣe ọwọ́ rẹ̀ ni ó kọlù wá, ṣùgbọ́n ó wá bẹ́ẹ̀ ni.”
andin qarap turunglar. Eger harwa Israil chégrisidiki yol bilen Beyt-Shemeshke mangsa, bizge kelgen shu chong bala-qazani chüshürgüchining özi Perwerdigar bolidu. Undaq bolmisa, bizni urghan Uning qoli emes, belki bizge chüshken tasadipiliq bolidu, xalas, déyishti.
10 Nígbà náà ni wọ́n ṣe èyí. Wọ́n mú abo màlúù méjì, tí ń fi ọmú fún ọmọ, wọn mọ́ ara, wọ́n sì dè é ni ilé kẹ̀kẹ́ ẹrù, wọn sì so àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀ ni ilé.
Shuning bilen Filistiyler shundaq qildi. Ular Mozayliq ikki inekni harwigha qoshup, mozaylirini öyde solap qoyup,
11 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa lé orí kẹ̀kẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ ni àpótí tí eku ẹ̀lírí wúrà àti àwòrán ààrùn oníkókó wà níbẹ̀.
Perwerdigarning ehde sanduqini harwigha sélip, altun chashqan we quyma hürrekler qachilan’ghan qapni uninggha yandap qoydi.
12 Nígbà náà; àwọn màlúù lọ tààrà sí ìhà Beti-Ṣemeṣi, wọ́n ń lọ tààrà, wọ́n sì ń dún bí wọ́n ti ń lọ. Wọn kò yà sí ọ̀tún tàbí yà sí òsì. Àwọn aláṣẹ Filistini tẹ̀lé wọn títí dé ibodè Beti-Ṣemeṣi.
Inekler Beyt-Shemeshke baridighan yol bilen udul yürüp ketti. Ular kötürülgen yol bilen mangghach möreytti, ya ong terepke ya sol terepke qéyip ketmidi. Filistiylerning ghojiliri ularning arqisidin Beyt-Shemeshning chégrisighiche bardi.
13 Nísinsin yìí, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi ń kórè jéró wọn ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, nígbà tí wọ́n wo òkè tí wọ́n sì rí àpótí ẹ̀rí Olúwa, wọ́n yọ̀ níwájú rẹ̀.
Beyt-Shemeshtikiler jilghida bughday oruwatatti, ular bashlirini kötürüp ehde sanduqini körüp xush bolushti.
14 Kẹ̀kẹ́ ẹrù wá sí pápá Joṣua ti Beti-Ṣemeṣi, níbẹ̀ ni ó ti dúró ní ẹ̀bá àpáta ńlá kan. Àwọn ènìyàn gé igi ara kẹ̀kẹ́ ẹrù sí wẹ́wẹ́ wọ́n sì fi àwọn màlúù náà rú ẹbọ sísun sí Olúwa.
Harwa Beyt-Shemeshlik Yeshuaning étizliqigha kélip, u yerdiki bir chong tashning yénida toxtap qaldi. Ular harwini chéqip, ikki inekni Perwerdigargha atap köydürme qurbanliq qildi.
15 Àwọn ará Lefi gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa wá sí ìsàlẹ̀ pẹ̀lú àpótí tí ohun èlò wúrà wà níbẹ̀, wọ́n sì gbé wọn ka orí àpáta ńlá náà. Ní ọjọ́ náà, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi rú ẹbọ sísun, wọ́n sì ṣe ìrúbọ sí Olúwa.
Lawiylar Perwerdigarning ehde sanduqi bilen altun buyumlar bar qapni chüshürüp chong tashning üstige qoydi. Shu küni Beyt-Shemeshtikiler Perwerdigargha köydürme qurbanliqlar we bashqa qurbanliqlarni qildi.
16 Àwọn aláṣẹ Filistini márààrún rí gbogbo èyí, wọ́n sì padà ní ọjọ́ náà sí Ekroni.
Filistiylerning besh ghojisi bularni körüp shu küni Ekron’gha qaytip ketti.
17 Èyí ni kókó wúrà tí àwọn Filistini fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀bi ọ̀kọ̀ọ̀kan fún Aṣdodu, ọ̀kan ti Gasa, ọ̀kan ti Aṣkeloni, ọ̀kan ti Gati, ọ̀kan ti Ekroni.
Filistiylerning Perwerdigargha itaetsizlik qurbanliqi qilip bergen altun hürriki: — Ashdod üchün bir, Gaza üchün bir, Ashkélon üchün bir, Gat üchün bir we Ekron üchün bir idi.
18 Wúrà eku ẹ̀lírí jẹ́ iye ìlú tí àwọn aláṣẹ Filistini márààrún ti wá, ìlú olódi pẹ̀lú ìletò wọn. Àpáta ńlá náà, lórí èyí tí a gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa lé jẹ́ ẹ̀rí títí di òní ní oko Joṣua ará Beti-Ṣemeṣi.
Altun chashqanlarning sani bolsa Filistiylerning besh ghojisigha tewe barliq sheherning sani bilen barawer idi. Bu sheherler sépilliq sheherler we ulargha qarashliq sehra-kentlerni, shundaqla ular Perwerdigarning ehde sanduqini qoyghan chong chimenzarghiche hemme jayni öz ichige alatti. Bu chimenzar hazirmu Beyt-Shemeshlik Yeshuaning étizliqida bar.
19 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kọlu díẹ̀ lára àwọn ọkùnrin Beti-Ṣemeṣi, ó pa àádọ́rin wọn, nítorí wọ́n ti wo inú àpótí ẹ̀rí Olúwa. Àwọn ènìyàn ṣọ̀fọ̀ nítorí àjálù ńlá tí Olúwa fi bá ọ̀pọ̀ wọn jà.
Emma Beyt-Shemeshtikiler öz meyliche ehde sanduqining ichige qarighini üchün Perwerdigar ulardin yetmish ademni, jümlidin chonglardin ellikni urdi. Perwerdigar xelqni mundaq qattiq urghanliqi üchün pütün xelq matem tutti.
20 Àwọn ọkùnrin ará Beti-Ṣemeṣi béèrè pé, “Ta ni ó le è dúró ní iwájú Olúwa Ọlọ́run mímọ́ yìí? Ọ̀dọ̀ ta ni àpótí ẹ̀rí Olúwa yóò gbà gòkè lọ láti ibí yìí?”
Beyt-Shemeshtikiler: — Bu muqeddes Xuda Perwerdigarning aldida kim öre turalaydu? Ehde sanduqi bizning bu yerdin kimning qéshigha apirilishi kérek? — dédi.
21 Nígbà náà, wọ́n rán àwọn ìránṣẹ́ sí àwọn ènìyàn tí Kiriati-Jearimu wí pé, “Àwọn Filistini ti dá àpótí ẹ̀rí Olúwa padà. Ẹ sọ̀kalẹ̀ wá, kí ẹ gbé e gòkè lọ sí ọ̀dọ̀ yín.”
Andin ular Kiriat-Yéarimdikilerge elchilerni ewitip: — Filistiyler Perwerdigarning ehde sanduqini qayturup berdi. Bu yerge kélip uni özünglargha élip kétinglar, dédi.

< 1 Samuel 6 >