< 1 Samuel 6 >

1 Nígbà tí àpótí ẹ̀rí Olúwa sì ti wà ní agbègbè Filistini fún oṣù méje,
Rəbbina q'utye Filiştinaaşine cigabışee yighıble vazna avxu.
2 àwọn ará Filistini pe àwọn àlùfáà, àti àwọn alásọtẹ́lẹ̀, wọ́n sì sọ pé, “Kí ni kí a ṣe pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Olúwa? Sọ fún wa bí àwa yóò ti dá a padà sí ààyè rẹ̀.”
Filiştinaaşe kaahinariy falika ilyaakanbı qopt'ul eyhen: – İne Rəbbine q'utyeyk hucoona ha'as? Şak'le eyhe, şi nəxübiy mana çine cigeeqa savaak'al haa'as?
3 Wọ́n dáhùn wí pé, “Tí ẹ bá dá àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run ti àwọn ọmọ Israẹli padà, ẹ má ṣe dá a padà ní òfìfo, ṣùgbọ́n bí ó ti wù kí ó rí, ẹ fún un ní ẹbọ ẹ̀bi. Nígbà náà ni a ó mú un yín láradá, ẹ̀yin yóò sì mọ ìdí tí ọwọ́ rẹ̀ kò fi tí ì kúrò lára yín.”
Manbışe eyhen: – İzrailyne Allahna q'utye yı'q'əlqa savaak'al haa'as vukkanxhee, mana q'ərab savaak'al hımaa'a. Şu mançinemee, taxsir şolyva Rəbbis pay haa'as vukkan. Mane gahıl şunab yug qeepxhesınbı, Mang'vee şoke nya'asiy xıl ts'ıts'dyaa'avad, ats'axhxhesın.
4 Àwọn ará Filistini béèrè pé, “Irú ẹbọ ẹ̀bi wo ni kí a fi fún un?” Wọ́n dáhùn, “Wúrà oníkókó márùn-ún àti eku ẹ̀lírí wúrà márùn-ún, gẹ́gẹ́ bí iye àwọn aláṣẹ Filistini, nítorí àjàkálẹ̀-ààrùn kan náà ni ó kọlù yín àti olórí yín.
Filiştinaaşe qiyghanan: – Şal taxsirva nena payne Rəbbis haa'as vukkan? Kaahinaaşeyiy falika ilyaakanbışe eyhen: – Filiştinaaşika xhuleyre xərnayiy, hamanimen k'ınəəğəykena fıriy q'öv hav'u g'axuvle. Mana ver vuşdecab deş, vuşde ç'ak'ınbışdeb vuk'lelqa qabına.
5 Mọ àwòrán ààrùn oníkókó àti ti eku ẹ̀lírí yin tí ó ń ba orílẹ̀-èdè náà jẹ́ kí o sì bu ọlá fún Ọlọ́run Israẹli. Bóyá yóò gbé ọwọ́ rẹ̀ kúrò lára yín, lára ọlọ́run yín àti lára ilẹ̀ yín.
Mançil-alla fıraaşinıd, vuşda ölka q'əra qaa'ane q'övəəşinıd k'opyebı he'e, İzrailyne Allahısıb hı'rmat givxhe. Sayid manke, Mang'vee şokeb, vuşde allahaaşileb, vuşde cigabışileb xıl ts'ıts'aa'a.
6 Kí ni ó dé tí ẹ fi ń sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí àwọn ará Ejibiti àti Farao ti ṣe? Nígbà tí ó fi ọwọ́ líle mú wọn, ṣé wọn kò rán àwọn ọmọ Israẹli jáde kí wọn kí ó lè lọ ní ọ̀nà wọn?
Misirbışeyiy fironee q'ı't'y k'eççuyn xhinne, şunad hıma'a. Allah manbışilqa rəhı'm dena qıxhamee, manbışe İzrailybı g'avkkuynbı.
7 “Nísinsin yìí ẹ pèsè kẹ̀kẹ́ ẹrù tuntun sílẹ̀, pẹ̀lú màlúù méjì tí ó ti fi ọmú fún ọmọ, èyí tí a kò tí ì gba àjàgà sí ọrùn rí, kí ẹ sì so ó mọ́ kẹ̀kẹ́ náà, kí ẹ sì mú ọmọ wọn kúrò lọ́dọ̀ wọn wá sí ilé láti so.
Həşdemee sa ts'edın daşk'a hı'ı, mançik mısacab xamut qidyav'una q'ıkar gyooqa'ana q'öble zer avt'le. Q'ıkarmee mançike curu'u xaaqa qıkkee.
8 Kí ẹ sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa sí orí kẹ̀kẹ́ ẹrù àti kí ẹ̀yin sì kó àwọn ohun èlò wúrà tí ẹ̀yin fi fún un gẹ́gẹ́ bí ti ẹbọ ẹ̀bi sí inú àpótí ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, kí ẹ̀yin kí ó sì rán an lọ,
Rəbbina q'utyeb alyapt'ı daşk'eeqa gyuvxhe, taxsir şolyva Mang'us allesın k'ınəəğəyken karbıd mançine k'anene yeşuk'eeqa gixhxhe. Qiyğaled daşk'a yəqqı'l hee'e hooracen.
9 ṣùgbọ́n kí ẹ sì máa ṣọ́ ọ. Tí ó bá ń lọ sí ilẹ̀ rẹ̀, ìlú rẹ̀, níhà Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà ni Olúwa mú àjálù ńlá yìí bá wa. Ṣùgbọ́n bí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀ nígbà náà ni a mọ̀ pé kì í ṣe ọwọ́ rẹ̀ ni ó kọlù wá, ṣùgbọ́n ó wá bẹ́ẹ̀ ni.”
Yı'q'əle saccu ilyaake. Man çine cigeeqa, Bet-Şemeşne suralqa atk'ınee, mana ver şalqa ooxuna Rəbb vornava eyhen vodun. Maqa idyapk'ıneeme, şak'le ats'axhxhesın, şas ı'xı'yn xıl Mang'un deşud. Man çiled-alqa ıxhayn kar vodun.
10 Nígbà náà ni wọ́n ṣe èyí. Wọ́n mú abo màlúù méjì, tí ń fi ọmú fún ọmọ, wọn mọ́ ara, wọ́n sì dè é ni ilé kẹ̀kẹ́ ẹrù, wọn sì so àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀ ni ilé.
Nəxüdiy uvhu, insanaaşe məxüdud ha'an. Q'öble zer qabı daşk'ayk iviyt'al, mançin q'ıkarıd xaa g'alya'a.
11 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa lé orí kẹ̀kẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ ni àpótí tí eku ẹ̀lírí wúrà àti àwòrán ààrùn oníkókó wà níbẹ̀.
Daşk'eeqa Rəbbine q'utyeyka sacigee, manbışe k'ınəəğəyke hı'iyn q'övərnanayiy fırarnana yeşuk giviyxhe.
12 Nígbà náà; àwọn màlúù lọ tààrà sí ìhà Beti-Ṣemeṣi, wọ́n ń lọ tààrà, wọ́n sì ń dún bí wọ́n ti ń lọ. Wọn kò yà sí ọ̀tún tàbí yà sí òsì. Àwọn aláṣẹ Filistini tẹ̀lé wọn títí dé ibodè Beti-Ṣemeṣi.
Mançile qiyğa zerbı qotkuda ayk'ananbı Bet-Şemeşne suralqa. Manbı sağılqa, solulqa siditk'ıl, sa yəq avqu, heğa-heğa ayk'ananbı. Filiştinaaşin ç'ak'ınbı mançiqab qihna Bet-Şemeş giviyğalne cigeeqamee avayk'ananbı.
13 Nísinsin yìí, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi ń kórè jéró wọn ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, nígbà tí wọ́n wo òkè tí wọ́n sì rí àpótí ẹ̀rí Olúwa, wọ́n yọ̀ níwájú rẹ̀.
Mane gahıl Bet-Şemeşğançenbı suk qiviyşal çolee vooxhe. Manbı q'utye g'avcu şadeebaxhenbı.
14 Kẹ̀kẹ́ ẹrù wá sí pápá Joṣua ti Beti-Ṣemeṣi, níbẹ̀ ni ó ti dúró ní ẹ̀bá àpáta ńlá kan. Àwọn ènìyàn gé igi ara kẹ̀kẹ́ ẹrù sí wẹ́wẹ́ wọ́n sì fi àwọn màlúù náà rú ẹbọ sísun sí Olúwa.
Daşk'a Bet-Şemeşğançene Yeşuayne çoleeqa qadı, sa xənne g'ayeyne k'ane ulyoyzaran. İnsanaaşe daşk'a haq'var hı'ı mançike osbı ha'a. Zerbışiked, Rəbbis gyooxhan haa'ana q'urban ablyaa'a.
15 Àwọn ará Lefi gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa wá sí ìsàlẹ̀ pẹ̀lú àpótí tí ohun èlò wúrà wà níbẹ̀, wọ́n sì gbé wọn ka orí àpáta ńlá náà. Ní ọjọ́ náà, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi rú ẹbọ sísun, wọ́n sì ṣe ìrúbọ sí Olúwa.
Leviyne nasıleençene insanaaşe Rəbbina q'utye, k'ınəəğəyke hı'iyn q'övəriy fırar sı'ına yeşuk'ub daşk'eençe gyaqqı, sa xənne g'ayel ooqa giyxhe. Mane yiğıl Bet-Şemeşğançenbışe Rəbbis gyooxhan haa'ane q'urbanıle ğayrı, medın q'urbanbıd gyaat'anbı.
16 Àwọn aláṣẹ Filistini márààrún rí gbogbo èyí, wọ́n sì padà ní ọjọ́ náà sí Ekroni.
Filiştinaaşine maqa abıyne xhone xərıng'uk'le man g'acu, mane yiğılycab Ekronqa siviyk'al.
17 Èyí ni kókó wúrà tí àwọn Filistini fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀bi ọ̀kọ̀ọ̀kan fún Aṣdodu, ọ̀kan ti Gasa, ọ̀kan ti Aṣkeloni, ọ̀kan ti Gati, ọ̀kan ti Ekroni.
Filiştinaaşe taxsir colyva Aşdod eyhene şaharne doyule, Gəzzə eyhene şaharne doyule, Aşkelon eyhene şaharne doyule, Gat eyhene şaharne doyule, Ekron eyhene şaharne doyule Rəbbis k'ınəəğəyke hı'iyn fırar adayle.
18 Wúrà eku ẹ̀lírí jẹ́ iye ìlú tí àwọn aláṣẹ Filistini márààrún ti wá, ìlú olódi pẹ̀lú ìletò wọn. Àpáta ńlá náà, lórí èyí tí a gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa lé jẹ́ ẹ̀rí títí di òní ní oko Joṣua ará Beti-Ṣemeṣi.
K'ınəəğəyke hı'iyn q'övərmee, hiqiy-alla cabırbışikane şaharbışisiy çine hiqiy-allane xivaaşis sik'ı adayle. Mane şaharbışiqa xhoyre xərna ıxha. Bet-Şemeşğane Yeşuayne çoleena, Rəbbina q'utye gyuvxhuna xəbna g'aye giyniyne yiğılqamee avxu vob.
19 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kọlu díẹ̀ lára àwọn ọkùnrin Beti-Ṣemeṣi, ó pa àádọ́rin wọn, nítorí wọ́n ti wo inú àpótí ẹ̀rí Olúwa. Àwọn ènìyàn ṣọ̀fọ̀ nítorí àjálù ńlá tí Olúwa fi bá ọ̀pọ̀ wọn jà.
Rəbbine q'utyeyne aq'a ilyaakıva, Allahee Bet-Şemeşğançenbışde vuk'lelqa ver ooxa. Rəbbee manbışda yights'al insan gek'a. Milletıd, Rəbbee cone vuk'lelqa ooxune verır-alla geşşe ıxha.
20 Àwọn ọkùnrin ará Beti-Ṣemeṣi béèrè pé, “Ta ni ó le è dúró ní iwájú Olúwa Ọlọ́run mímọ́ yìí? Ọ̀dọ̀ ta ni àpótí ẹ̀rí Olúwa yóò gbà gòkè lọ láti ibí yìí?”
Bet-Şemeşğançenbışe eyhen: – İne muq'addasne Allahne, Rəbbine ögil şavusse ulyozaras əxəye? Nyaqane ina q'utye quvkees?
21 Nígbà náà, wọ́n rán àwọn ìránṣẹ́ sí àwọn ènìyàn tí Kiriati-Jearimu wí pé, “Àwọn Filistini ti dá àpótí ẹ̀rí Olúwa padà. Ẹ sọ̀kalẹ̀ wá, kí ẹ gbé e gòkè lọ sí ọ̀dọ̀ yín.”
Qiyğa manbışe Kiryat-Yearim eyhene şaharne milletısqa xabar ana insanar g'axuvu, eyhen: – Filiştinaaşe Rəbbina q'utye yı'q'əlqa savaak'al hav'u, able mana quvkee.

< 1 Samuel 6 >