< 1 Samuel 6 >

1 Nígbà tí àpótí ẹ̀rí Olúwa sì ti wà ní agbègbè Filistini fún oṣù méje,
Angraeng ih thingkhong loe Philistin prae thungah khrah sarihto oh.
2 àwọn ará Filistini pe àwọn àlùfáà, àti àwọn alásọtẹ́lẹ̀, wọ́n sì sọ pé, “Kí ni kí a ṣe pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Olúwa? Sọ fún wa bí àwa yóò ti dá a padà sí ààyè rẹ̀.”
To naah Philistinnawk loe qaimanawk hoi hmabang angzo han koi hmuen khen kop kaminawk to kawk o moe, Angraeng ih thingkhong to kawbangmaw ka sak o han? Angmah ohhaih ahmuen ah maw ka thak o let han, na thui oh, tiah a naa o.
3 Wọ́n dáhùn wí pé, “Tí ẹ bá dá àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run ti àwọn ọmọ Israẹli padà, ẹ má ṣe dá a padà ní òfìfo, ṣùgbọ́n bí ó ti wù kí ó rí, ẹ fún un ní ẹbọ ẹ̀bi. Nígbà náà ni a ó mú un yín láradá, ẹ̀yin yóò sì mọ ìdí tí ọwọ́ rẹ̀ kò fi tí ì kúrò lára yín.”
Nihcae mah, Israael kaminawk ih Sithaw thingkhong na thak o let nahaeloe, bangkrai ah thak o hmah; zae angbawnhaih sak hanah hmuen paekhaih hoiah thak oh; to tiah ni ngan na tui o thai ueloe, tipongah maw anih ih ban nangcae khae hoi azuk ai, tiah na panoek o tih, tiah a naa o.
4 Àwọn ará Filistini béèrè pé, “Irú ẹbọ ẹ̀bi wo ni kí a fi fún un?” Wọ́n dáhùn, “Wúrà oníkókó márùn-ún àti eku ẹ̀lírí wúrà márùn-ún, gẹ́gẹ́ bí iye àwọn aláṣẹ Filistini, nítorí àjàkálẹ̀-ààrùn kan náà ni ó kọlù yín àti olórí yín.
Philistinnawk mah, Kawbaktih zae angbawnhaih hmuen paekhaih maw ka pat pae o han? tiah a naa o. Nihcae mah, Philistin ukkung angraeng zetto, sui hoi sak ih krang pangato, sui hoi sak ih pazu krang pangato paek oh; nangcae hoi nangcae ukkungnawk mah na tongh o ih nathaih loe maeto ah ni oh.
5 Mọ àwòrán ààrùn oníkókó àti ti eku ẹ̀lírí yin tí ó ń ba orílẹ̀-èdè náà jẹ́ kí o sì bu ọlá fún Ọlọ́run Israẹli. Bóyá yóò gbé ọwọ́ rẹ̀ kúrò lára yín, lára ọlọ́run yín àti lára ilẹ̀ yín.
Ahlut krang hoi na prae paro pazu krangnawk to sah oh loe, Israel Sithaw lensawkhaih to pakoeh oh; to tiah nahaeloe nangcae, na sithawnawk hoi na prae thung hoiah anih ih ban to azuk let khoe doeh om tih.
6 Kí ni ó dé tí ẹ fi ń sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí àwọn ará Ejibiti àti Farao ti ṣe? Nígbà tí ó fi ọwọ́ líle mú wọn, ṣé wọn kò rán àwọn ọmọ Israẹli jáde kí wọn kí ó lè lọ ní ọ̀nà wọn?
Tipongah Izip kaminawk hoi Faro baktiah palung na thah o loe? Israel Angraeng mah nihcae to kana parai ah thuitaek naah, Egypt kaminawk mah Israel kaminawk a prae thung hoiah tacawt o sak moe, a caeh o sak talai na ai maw?
7 “Nísinsin yìí ẹ pèsè kẹ̀kẹ́ ẹrù tuntun sílẹ̀, pẹ̀lú màlúù méjì tí ó ti fi ọmú fún ọmọ, èyí tí a kò tí ì gba àjàgà sí ọrùn rí, kí ẹ sì so ó mọ́ kẹ̀kẹ́ náà, kí ẹ sì mú ọmọ wọn kúrò lọ́dọ̀ wọn wá sí ilé láti so.
Vaihi maitaw leeng kangtha to sah oh loe, a caa tahnu paek li mawitaw amno hnetto to hoi o ah; a nuiah hmuen phawhhaih thing koeng o hmah; maitaw amno to maitaw leeng pongah pathlet oh loe, maitaw caa to loe im ah hoi o ving ah.
8 Kí ẹ sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa sí orí kẹ̀kẹ́ ẹrù àti kí ẹ̀yin sì kó àwọn ohun èlò wúrà tí ẹ̀yin fi fún un gẹ́gẹ́ bí ti ẹbọ ẹ̀bi sí inú àpótí ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, kí ẹ̀yin kí ó sì rán an lọ,
Angraeng ih thingkhong to la oh loe, maitaw leeng nuiah suem oh; zae angbawnhaih sak han paek ih hmuen baktih toengah, sui hoi sak ih ahlut krang hoi pazu krangnawk to Sithaw thingkhong taengah suem oh loe, thak oh.
9 ṣùgbọ́n kí ẹ sì máa ṣọ́ ọ. Tí ó bá ń lọ sí ilẹ̀ rẹ̀, ìlú rẹ̀, níhà Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà ni Olúwa mú àjálù ńlá yìí bá wa. Ṣùgbọ́n bí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀ nígbà náà ni a mọ̀ pé kì í ṣe ọwọ́ rẹ̀ ni ó kọlù wá, ṣùgbọ́n ó wá bẹ́ẹ̀ ni.”
Angmah prae caehhaih Beth-Shemesh bangah Sithaw ih thingkhong to caeh nahaeloe, a tongh o ih hae baktih kasae loe Angraeng mah ni ohsak; toe to bangah ni caeh ai nahaeloe, anih ih ban hoiah aicae hae hum ai, hae raihaih loe a tongh o han ih aimacae taham raihaih ah ni om tih, tiah a naa o.
10 Nígbà náà ni wọ́n ṣe èyí. Wọ́n mú abo màlúù méjì, tí ń fi ọmú fún ọmọ, wọn mọ́ ara, wọ́n sì dè é ni ilé kẹ̀kẹ́ ẹrù, wọn sì so àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀ ni ilé.
To pongah kaminawk mah to tiah sak o; a thuih o ih baktih toengah a caa tahnu panae li maitaw amno hnetto a lak o moe, maitaw leeng pongah pathlet o; a caa hnik loe im ah paung o caeng.
11 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa lé orí kẹ̀kẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ ni àpótí tí eku ẹ̀lírí wúrà àti àwòrán ààrùn oníkókó wà níbẹ̀.
Angraeng ih thingkhong to maitaw leeng nuiah suek o; a taeng ih thingkhong thungah loe sui hoiah sak ih pazu krang hoi ahlut krangnawk to suek o.
12 Nígbà náà; àwọn màlúù lọ tààrà sí ìhà Beti-Ṣemeṣi, wọ́n ń lọ tààrà, wọ́n sì ń dún bí wọ́n ti ń lọ. Wọn kò yà sí ọ̀tún tàbí yà sí òsì. Àwọn aláṣẹ Filistini tẹ̀lé wọn títí dé ibodè Beti-Ṣemeṣi.
To naah maitaw hnik loe Beth-Shemesh vangpui bangah katoeng ah caeh hoi poe; banqoi bantang amkhraeng ai ah, lampui ah caeh o poe; Philistin ukkungnawk loe Beth-Shemesh vangpui khoek to bang o.
13 Nísinsin yìí, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi ń kórè jéró wọn ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, nígbà tí wọ́n wo òkè tí wọ́n sì rí àpótí ẹ̀rí Olúwa, wọ́n yọ̀ níwájú rẹ̀.
To naah Beth-Shemeseh vangpui ih kaminawk loe, azawn ah cang aah o li vop; a khet o tahang naah, Sithaw thingkhong to hnuk o; a hnuk o ih hmuen pongah anghoe o.
14 Kẹ̀kẹ́ ẹrù wá sí pápá Joṣua ti Beti-Ṣemeṣi, níbẹ̀ ni ó ti dúró ní ẹ̀bá àpáta ńlá kan. Àwọn ènìyàn gé igi ara kẹ̀kẹ́ ẹrù sí wẹ́wẹ́ wọ́n sì fi àwọn màlúù náà rú ẹbọ sísun sí Olúwa.
Maitaw leeng loe Beth-Shemesh vangpui kami, Joshua ih lawk ah angzoh moe, kalen parai lungsong taengah anghak; kaminawk mah maitaw leeng thingnawk to boeng o moe, maitaw to Angraeng khaeah angbawnhaih ah sak o.
15 Àwọn ará Lefi gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa wá sí ìsàlẹ̀ pẹ̀lú àpótí tí ohun èlò wúrà wà níbẹ̀, wọ́n sì gbé wọn ka orí àpáta ńlá náà. Ní ọjọ́ náà, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi rú ẹbọ sísun, wọ́n sì ṣe ìrúbọ sí Olúwa.
Levinawk mah Angraeng ih thingkhong to lak o, kalah thingkhong thungah kaom sui hoi sak ih hmuennawk doeh a lak o pacoengah, lungsong nuiah koeng o; to na niah Beth-Shemesh vangpui kaminawk mah, angbawnhaih to sak o moe, Angraeng khaeah angbawnhaih hmuen to tathlang o.
16 Àwọn aláṣẹ Filistini márààrún rí gbogbo èyí, wọ́n sì padà ní ọjọ́ náà sí Ekroni.
Philistin ukkung pangatonawk mah to tiah angbawnhaih to hnuk o pacoeng, to na niah Ekron vangpui ah amlaem o let.
17 Èyí ni kókó wúrà tí àwọn Filistini fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀bi ọ̀kọ̀ọ̀kan fún Aṣdodu, ọ̀kan ti Gasa, ọ̀kan ti Aṣkeloni, ọ̀kan ti Gati, ọ̀kan ti Ekroni.
Philistin kaminawk mah Angraeng khaeah pat pae o let ih, zae angbawnhaih hmuen ah kaom, sui hoiah sak ih ahlut baktiah kacong kuk krangnawk to Ashdod vangpui ah maeto, Gaza vangpui ah maeto, Ashkelon vangpui ah maeto, Gath vangpui ah maeto, Ekron vangpui ah maeto, a pat pae o boih.
18 Wúrà eku ẹ̀lírí jẹ́ iye ìlú tí àwọn aláṣẹ Filistini márààrún ti wá, ìlú olódi pẹ̀lú ìletò wọn. Àpáta ńlá náà, lórí èyí tí a gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa lé jẹ́ ẹ̀rí títí di òní ní oko Joṣua ará Beti-Ṣemeṣi.
Philistin kaminawk ih avang, ukkung angraeng pangatonawk ohhaih ahmuen, sipae hoi thungh ih vangpuinawk zetto ah sui hoi sak ih pazu krangnawk to pat pae o. Angraeng ih thingkhong suekhaih kalen parai Abel ih thlung loe, Beth-Shemesh vangpui kami, Joshua lawk ah vaihni ni khoek to hnukung ah oh.
19 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kọlu díẹ̀ lára àwọn ọkùnrin Beti-Ṣemeṣi, ó pa àádọ́rin wọn, nítorí wọ́n ti wo inú àpótí ẹ̀rí Olúwa. Àwọn ènìyàn ṣọ̀fọ̀ nítorí àjálù ńlá tí Olúwa fi bá ọ̀pọ̀ wọn jà.
Toe nihcae mah Angraeng ih thingkhong athung bang to khet o pongah, Sithaw mah Beth-Shemesh vangpui ih kami sing panga, quisarihto dueksak; Angraeng mah nihcae nuiah kana parai ah danpaek moe, kami paroeai hum pongah, kaminawk loe palungset o.
20 Àwọn ọkùnrin ará Beti-Ṣemeṣi béèrè pé, “Ta ni ó le è dúró ní iwájú Olúwa Ọlọ́run mímọ́ yìí? Ọ̀dọ̀ ta ni àpótí ẹ̀rí Olúwa yóò gbà gòkè lọ láti ibí yìí?”
To pongah Beth-Shemesh ih kaminawk mah, Hae ih ciimcai Angraeng Sithaw hmaa ah mi maw angdoe thai tih? Hae thingkhong loe aicae khae hoi mi khaeah maw caeh tih? tiah a thuih o.
21 Nígbà náà, wọ́n rán àwọn ìránṣẹ́ sí àwọn ènìyàn tí Kiriati-Jearimu wí pé, “Àwọn Filistini ti dá àpótí ẹ̀rí Olúwa padà. Ẹ sọ̀kalẹ̀ wá, kí ẹ gbé e gòkè lọ sí ọ̀dọ̀ yín.”
To naah Kiriath Jearim vangpui ih kaminawk khaeah laicaeh to patoeh o moe, Philistinnawk mah Angraeng ih thingkhong to thak o let; angzo o tathuk loe, na ohhaih ahmuen ah sin oh, tiah thuih pae o.

< 1 Samuel 6 >