< 1 Samuel 29 >
1 Àwọn Filistini sì kó gbogbo ogun wọn jọ sí Afeki: Israẹli sì dó ni ibi ìsun omi tí ó wà ní Jesreeli.
Na rĩrĩ, Afilisti magĩcokanĩrĩria mbũtũ ciao cia ita kũu Afeku, nao Isiraeli makĩamba hema hakuhĩ na gĩthima kĩrĩa kĩarĩ kũu Jezireeli.
2 Àwọn ìjòyè Filistini sì kọjá ní ọ̀rọ̀ọ̀rún àti lẹgbẹẹgbẹ̀rún; Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ pẹ̀lú Akiṣi sì kẹ́yìn.
Na rĩrĩa aathani a Afilisti maahĩtũkaga na ikundi ciao cia magana na cia ngiri, Daudi na andũ ake maathiiaga marĩ thuutha hamwe na Akishi.
3 Àwọn ìjòyè Filistini sì béèrè wí pé, “Kín ni àwọn Heberu ń ṣe níhìn-ín yìí?” Akiṣi sì wí fún àwọn ìjòyè Filistini pé “Dafidi kọ yìí, ìránṣẹ́ Saulu ọba Israẹli, tí ó wà lọ́dọ̀ mi láti ọjọ́ wọ̀nyí tàbí láti ọdún wọ̀nyí, èmi kò ì tì í rí àṣìṣe kan ni ọwọ́ rẹ̀ láti ọjọ́ tí ó ti dé ọ̀dọ̀ mi títí di òní yìí.”
Anene acio a ita rĩa Afilisti makĩũria atĩrĩ, “Nĩ atĩa ũhoro wa Ahibirania aya?” Akishi agĩcookia atĩrĩ, “Githĩ ũyũ ti Daudi, ũrĩa warĩ mũnene wa Saũlũ mũthamaki wa Isiraeli? Akoretwo arĩ hamwe na niĩ makĩria ma mwaka ũmwe na kuuma mũthenya ũrĩa oimire gwa Saũlũ, nginyagia ũmũthĩ, ndirĩ ndamuona na ihĩtia.”
4 Àwọn ìjòyè Filistini sì bínú sí i; àwọn ìjòyè Filistini sì wí fún un pé, “Jẹ́ kí ọkùnrin yìí padà kí ó sì lọ sí ipò rẹ̀ tí ó fi fún un, kí ó má sì jẹ́ kí ó bá wa sọ̀kalẹ̀ lọ sí ogun, kí ó má ba à jásí ọ̀tá fún wa ni ogun, kín ni òun ó fi ba olúwa rẹ̀ làjà, orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí kọ́?
No anene a mbũtũ cia ita cia Afilisti makĩmũrakarĩra, makĩmwĩra atĩrĩ, “Ĩra mũndũ ũyũ ahũndũke nĩguo acooke handũ harĩa wamũheire. Ndegũthiĩ hamwe na ithuĩ mbaara-inĩ ndakae gũtũgarũrũka rĩrĩa tũrarũa. Nĩ ũndũ ũngĩ ũrĩkũ mũndũ ũyũ angĩĩka maiguithanie na mwathi wake, tiga kũũraga andũ aitũ?
5 Ṣé èyí ni Dafidi tiwọn torí rẹ̀ gberin ara wọn nínú ijó wí pé, “‘Saulu pa ẹgbẹ̀rún rẹ̀, Dafidi si pa ẹgbẹgbàarùn-ún tirẹ̀.’”
Githĩ ũyũ ti Daudi ũrĩa mainĩire nyĩmbo-inĩ ciao ũũ: “‘Saũlũ nĩeyũragĩire andũ ngiri nyingĩ, nake Daudi akooraga ngiri makũmi maingĩ’?”
6 Akiṣi sì pe Dafidi, ó sì wí fún un pé, “Bí Olúwa ti ń bẹ láààyè, ìwọ jẹ́ olóòótọ́ àti ẹni ìwà rere lójú mi, ní àlọ rẹ àti ààbọ̀ rẹ pẹ̀lú mi ní ogun: nítorí pé èmi ko tí ì ri búburú kan lọ́wọ́ rẹ́ láti ọjọ́ ti ìwọ ti tọ̀ mí wá, títí o fi dì òní yìí ṣùgbọ́n lójú àwọn ìjòyè, ìwọ kò ṣe ẹni tí ó tọ́.
Nĩ ũndũ ũcio Akishi agĩĩta Daudi, akĩmwĩra atĩrĩ, “Ti-itherũ o ta ũrĩa Jehova atũũraga muoyo, nĩũkoretwo ũrĩ mwĩhokeku, na no njigue wega tũgĩtungata hamwe nawe ita-inĩ. Kuuma mũthenya ũrĩa wokire kũrĩ niĩ nginya rĩu, ndirĩ ndoona ihĩtia rĩaku, no anene aya a mbũtũ cia ita matingĩgwĩtĩkĩra.
7 Ǹjẹ́ yípadà kí o sì máa lọ ní àlàáfíà, kí ìwọ má ṣe bà àwọn Filistini nínú jẹ́.”
Hũndũka ũthiĩ na thayũ; ndũgeeke ũndũ ũngĩrakaria anene a Afilisti.”
8 Dafidi sì wí fún Akiṣi pé, “Kín ni èmi ṣe? Kín ni ìwọ sì rí lọ́wọ́ ìránṣẹ́ rẹ láti ọjọ́ ti èmi ti ń gbé níwájú rẹ títí di òní yìí, tí èmi kì yóò fi lọ bá àwọn ọ̀tá ọba jà.”
Daudi akĩũria atĩrĩ, “Nĩ atĩa njĩkĩte? Nĩ atĩa wonete mũũru na ndungata yaku kuuma mũthenya ũrĩa ndookire kũrĩ we nginya rĩu? Nĩ kĩĩ gĩkũgiria thiĩ ngarũe na thũ cia mũthamaki, mwathi wakwa?”
9 Akiṣi sì dáhùn, ó sì wí fún Dafidi pé, “Èmi mọ̀ pé ìwọ ṣe ẹni rere lójú mi, bi angẹli Ọlọ́run; ṣùgbọ́n àwọn ìjòyè Filistini wí pé, ‘Òun kì yóò bá wa lọ sí ogun.’
Akishi akĩmũcookeria atĩrĩ, “Nĩnjũũĩ atĩ ũkoretwo ũrĩ mwega maitho-inĩ makwa ta mũraika wa Ngai; no rĩrĩ, anene a mbũtũ cia ita rĩa Afilisti moigĩte atĩrĩ, ‘Ũcio ndangĩĩtĩkĩrio atwarane na ithuĩ kũu mbaara-inĩ.’
10 Ǹjẹ́, nísinsin yìí dìde ní òwúrọ̀ pẹ̀lú àwọn ìránṣẹ́ olúwa rẹ tí ó bá ọ wá, ki ẹ si dìde ní òwúrọ̀ nígbà tí ilẹ̀ bá mọ́ kí ẹ sì máa lọ.”
Rĩu rooka gũũkĩra rũciinĩ tene, hamwe na ndungata cia mwathi waku iria mũũkĩte nacio, na muume gũkũ rũciinĩ gũgĩthererũka.”
11 Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì dìde ní òwúrọ̀ láti padà lọ sí ilẹ̀ àwọn Filistini. Àwọn Filistini sì gòkè lọ sí Jesreeli.
Nĩ ũndũ ũcio Daudi na andũ ake makĩrooka gũũkĩra rũciinĩ tene nĩguo macooke bũrũri-inĩ wa Afilisti, nao Afilisti makĩambata magĩthiĩ Jezireeli.