< 1 Samuel 27 >

1 Dafidi sì wí ní ọkàn ara rẹ̀ pé, “Ǹjẹ́ ni ìjọ kan ni èmi yóò ti ọwọ́ Saulu ṣègbé, kò sì sí ohun tí ó yẹ mí jù kí èmi yára sá àsálà lọ sórí ilẹ̀ àwọn Filistini, yóò sú Saulu láti máa tún wa mi kiri ní gbogbo agbègbè Israẹli, èmi a sì bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀.”
A I iho la o Davida iloko o kona naau, e make auanei au i ka lima o Saula i kekahi la: e aho e holo koke au ma ka aina o ko Pilisetia; alaila aole manao o Saula e imi hou mai ia'u ma na wahi a pau o ka Iseraela: pela e pakele ai au i kona lima.
2 Dafidi sì dìde, ó sì rékọjá, òun pẹ̀lú ẹgbẹ̀ta ọmọkùnrin tí o ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ sí Akiṣi, ọmọ Maoki, ọba Gati.
Ku ae la o Davida, a hele aku la me na kanaka eono haneri me ia io Akisa la, ke keiki a Maoka, ke alii o Gata.
3 Dafidi sì bá Akiṣi jókòó ní Gati, òun, àti àwọn ọmọkùnrin rẹ, olúkúlùkù wọn pẹ̀lú ará ilé rẹ̀; Dafidi pẹ̀lú àwọn aya rẹ̀ méjèèjì, Ahinoamu ará Jesreeli, àti Abigaili ará Karmeli aya Nabali.
A noho iho la o Davida me Akisa ma Gata, oia a me kona poe kanaka, o kela kanaka keia kanaka me kona ohua, o Davida me kana mau wahine, o Ahinoama no Iezereela, a o Abigaila no Karemela, ka wahine a Nabala.
4 A sì sọ fún Saulu pé, Dafidi sálọ si Gati, òun kò sì tún wá á kiri mọ́.
A haiia mai la ia Saula, ua holo o Davida ma Gata: aole ia i imi hou aku ia ia.
5 Dafidi sì wí fún Akiṣi pé, “Bí ó bá jẹ́ pé èmi rí oore-ọ̀fẹ́ lójú rẹ̀, jẹ́ kí wọn ó fún mi ní ibìkan nínú àwọn ìletò wọ̀nyí; èmi yóò máa gbé ibẹ̀, èéṣe tí ìránṣẹ́ rẹ yóò sì máa bá ọ gbé ní ìlú ọba.”
Olelo aku la o Davida ia Akisa, Ina paha i alohaia mai au i kou maka, e haawi mai oe ia'u i wahi ma kekahi kulanakauhale ma ke kula i noho ai au malaila: no ke aha la o noho ai au me oe ma ke kulanakauhale alii?
6 Akiṣi sí fi Siklagi fún un ní ọjọ́ náà nítorí náà ni Siklagi fi dí ọba Juda títí ó fi dì òní yìí.
A haawi aku la o Akisa ia Zikelaga nona ia la: no ia mea, lilo aku la o Zikelaga no na'lii o ka Iuda a hiki i keia la.
7 Iye ọjọ́ tí Dafidi fi jókòó ní ìlú àwọn Filistini sì jẹ́ ọdún kan àti oṣù mẹ́rin.
A o na la o ko Davida noho ana ma ka aina o ko Pilisetia, hookahi ia makahiki a me na malama keu eha.
8 Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì gòkè lọ, wọ́n sì gbé ogun ti àwọn ará Geṣuri, àti àwọn ará Gesri, àti àwọn ará Amaleki àwọn wọ̀nyí ni ó sì tí ń gbé ní ilẹ̀ náà, láti ìgbà àtijọ́, bí ó ti fẹ̀ lọ sí Ṣuri títí ó fi dé ilẹ̀ Ejibiti.
Hele aku la o Davida me kona poe kanaka, a kaua aku la i ko Gesura, a me ko Gerezi, a me ka Amaleka: no ka mea, he poe kamaaina kahiko lakou o ka aina, kahi e hele aku ai i Sura, a hiki loa i ka aina o Aigupita.
9 Dafidi sì kọlu ilẹ̀ náà kò sì fi ọkùnrin tàbí obìnrin sílẹ̀ láààyè, ó sì kó àgùntàn, àti màlúù, àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àti ìbákasẹ, àti aṣọ, ó sì yípadà ó tọ Akiṣi wá.
A luku aku la o Davida i ka aina, aole i koe kekahi kanaka, aole hoi kekahi wahine e ola ana, a lawe ae la ia i na hipa, a me na bipi, a me na hoki, a me na kamelo, me ka lole, a hoi aku la a hiki io Akisa la.
10 Akiṣi sì bi í pé, “Níbo ni ẹ̀yin gbé rìn sí lónìí?” Dafidi sì dáhùn pé, “Sí ìhà gúúsù ti Juda ni, tàbí sí ìhà gúúsù ti Jerahmeeli,” tàbí “Sí ìhà gúúsù ti àwọn ará Keni.”
I mai la o Akisa, Mahea kahi a oukou i hao ai i keia la? I aku la o Davida, ma ka aoao hema o ka Iuda, a ma ka aoao hema o ka Ierahemeeli, a ma ka aoao hema o ko Keni.
11 Dafidi kò sì dá ọkùnrin tàbí obìnrin sí láààyè, láti mú ìròyìn wá sí Gati, wí pé, “Ki wọn máa bá à sọ ọ̀rọ̀ wa níbẹ̀, pé, ‘Báyìí ni Dafidi ṣe,’” àti bẹ́ẹ̀ ni ìṣe rẹ̀, yóò sì rí ni gbogbo ọjọ́ ti yóò fi jókòó ni ìlú àwọn Filistini.
Aole i hoopakele o Davida i kekahi kanaka, aole hoi i kekahi wahine e ola ana e hele ma Gata e olelo, o hai aku lakou no makou, i ka i ana'e, Pela o Davida i hana'i, a pela hoi kana e hana aku ai i na manawa a pau o kona noho ana ma ka aina o na Pilisetia.
12 Akiṣi sì gba ti Dafidi gbọ́, wí pé, “Òun ti mú kí Israẹli àti àwọn ènìyàn rẹ̀ kórìíra rẹ̀ pátápátá, yóò si jẹ́ ìránṣẹ́ mi títí láé.”
Manao aku la o Akisa i ka Davida, ua oiaio, i iho la, Ua hoolilo oia ia ia iho i mea hoowahawaha loa ia e kona poe kanaka, e ka Iseraela, a e lilo ia i kauwa na'u i ka manawa mau loa.

< 1 Samuel 27 >