< 1 Samuel 24 >

1 Nígbà tí Saulu padà kúrò lẹ́yìn àwọn Filistini a sì sọ fún un pé, “Wò ó, Dafidi ń bẹ́ ni aginjù En-Gedi.”
A I ka hoi ana mai o Saula i ka hahai ana i ko Pilisetia, ua haiia mai ia ia, i mai la, Aia hoi o Davida ma ka waonahele o Enegedi.
2 Saulu sì mú ẹgbẹ̀rún mẹ́ta akọni ọkùnrin tí a yàn nínú gbogbo Israẹli ó sì lọ láti wá Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ lórí òkúta àwọn ewúrẹ́ igbó.
Alaila lawe ae la o Saula i ekolu tausani kanaka i waeia noloko mai o ka Iseraela a pau, a hele aku la e imi ia Davida a me kona poe kanaka maluna o na pohaku o na kao hihiu.
3 Ó sì dé ibi àwọn agbo àgùntàn tí ó wà ní ọ̀nà, ihò kan sì wà níbẹ̀, Saulu sì wọ inú rẹ̀ lọ láti bo ẹsẹ̀ rẹ̀, Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì ń bẹ lẹ́bàá ihò náà.
A hiki aka ia i na pa hipa ma ke ala, a malaila he ana; a komo aku la o Saula e uhi i kona wawae: a o Davida a me kona poe kanaka aia ma na aoao o ke ana.
4 Àwọn ọmọkùnrin Dafidi sì wí fún un pé, “Wò ó, èyí ni ọjọ́ náà tí Olúwa wí fún ọ pé, ‘Wò ó, èmi fi ọ̀tá rẹ lé ọ lọ́wọ́, ìwọ ó sì ṣe sí i gẹ́gẹ́ bí ó ti tọ́ lójú rẹ.’” Dafidi sì dìde, ó sì yọ́ lọ gé etí aṣọ Saulu.
I aku la na kanaka o Davida ia ia, Aia hoi, ua hiki mai ka la a Iehova i i mai ai, Aia hoi, e hoolilo ana au i kou enemi iloko o kou lima, i hana aku ai oe ia ia e like me kou makemake. Alaila ku ae la o Davida, a oki malu iho i ka lepa o ka lole aahu o Saula.
5 Ó sì ṣe lẹ́yìn èyí, àyà já Dafidi nítorí tí ó gé etí aṣọ Saulu.
A mahope iho, kui iho la ka naau o Davida ia ia iho, i kona oki ana i ka lepa o ka lole aahu o Saula.
6 Òun sì wí fún àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ pé, “Èèwọ̀ ni fún mi láti ọ̀dọ́ Olúwa wá bí èmi bá ṣe nǹkan yìí sí ẹni tí a ti fi àmì òróró Olúwa yàn, láti nawọ́ mi sí i, nítorí pé ẹni àmì òróró Olúwa ni.”
I aku la ia i kona poe kanaka, Ua hoole mai o Iehova ke hana aku au i keia mea i kuu haku, i ka mea a Iehova i poni ai, a e kau aku i kuu lima maluna ona, no ka mea, oia ka mea i poniia e Iehova.
7 Dafidi sì fi ọ̀rọ̀ wọ̀nyí dá àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ dúró, kò sì jẹ́ kí wọn dìde sí Saulu, Saulu sì dìde kúrò ní ihò náà, ó sì bá ọ̀nà rẹ̀ lọ.
Hooikaika aku la o Davida i kona poe kanaka ma keia olelo, aole ia i ae aku ia lakou e ku e ia Saula. Ku ae la o Saula mawaho o ke ana, a hele aku la ma ke ala.
8 Dafidi sì dìde lẹ́yìn náà, ó sì jáde kúrò nínú ihò náà ó sì kọ sí Saulu pé, “Olúwa mi, ọba!” Saulu sì wo ẹ̀yìn rẹ̀. Dafidi sì dojú rẹ́ bo ilẹ̀ ó sì tẹríba fún un.
Mahope iho, ku ae la o Davida a hele iwaho o ke ana, a kahea aku la mahope o Saula, i aku la, E kuu haku, e ke alii. A nana ae la o Saula mahope ona, kulou iho la o Davida me kona maka ma ka honua, a haule iho ilalo.
9 Dafidi sì wí fún Saulu pé, “Èéha ti ṣe tí ìwọ fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ àwọn ènìyàn pé, ‘Wò ó, Dafidi ń wa ẹ̀mí rẹ́’?
I aku la o Davida ia Saula, No ke aha la oe i hoolohe ai i ka olelo a kanaka, i ka i ana mai, Aia hoi, ke imi nei o Davida e hana eha ia oe?
10 Wò ó, ojú rẹ́ rí i lónìí, bí Olúwa ti fi ìwọ lé mi lọ́wọ́ lónìí nínú ihò, àwọn kan ní kí èmi ó pa ọ, ṣùgbọ́n èmi dá ọ sí, ‘Èmi sì wí pé, èmi kì yóò nawọ́ mi sí olúwa mi, nítorí pé ẹni àmì òróró Olúwa ni òun jẹ́.’
Aia hoi, i keia la ua ike kou maka i ka hoolilo ana o Iehova ia oe iloko o kuu lima ma ke ana: a i mai la kekahi e pepehi ia oe; aka, ua aloha au ia oe; i aku la, Aole au e kau aku i kuu lima maluna o kuu haku; no ka mea, oia ka Iehova i poni ai.
11 Pẹ̀lúpẹ̀lú, baba mi, wò ó, àní wo etí aṣọ rẹ lọ́wọ́ mi; nítorí èmi gé etí aṣọ rẹ, èmi kò sì pa ọ́, sì wò ó, kí o sì mọ̀ pé kò sí ibi tàbí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ mi, èmi kò sì ṣẹ̀ ọ̀, ṣùgbọ́n ìwọ ń dọdẹ ẹ̀mí mi láti gbà á.
E nana oe, e kuu makuakane, e nana hoi i ka lepa o kou aahu ma kuu lima: no ka mea, i kuu oki ana i ka lepa o kou aahu, aole hoi i pepehi ia oe, e nana hoi, e ike oe, aole he hewa, aole hoi he lawehala iloko o kuu lima, aole no au i hana hewa aku ia oe: aka, ke imi mai nei oe i kuu ola e lawe aka ia.
12 Kí Olúwa ṣe ìdájọ́ láàrín èmi àti ìwọ, àti kí Olúwa ó gbẹ̀san mi lára rẹ; ṣùgbọ́n, ọwọ́ mi kì yóò sí lára rẹ.
Na Iehova e hooponopono iwaena o kaua, a na Iehova e hoopai ia oe no'u; aka, aole e kauia'ku kuu lima maluna ou.
13 Gẹ́gẹ́ bí òwe ìgbà àtijọ́ ti wí, ìwà búburú a máa ti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn búburú jáde wá; ṣùgbọ́n ọwọ́ mi kì yóò sí lára rẹ.
E like me ka olelo a ka poe kahiko, No ka poe hewa mai ka hewa; aka, aole e kauia'ku kuu lima maluna ou.
14 “Nítorí ta ni ọba Israẹli fi jáde? Ta ni ìwọ ń lépa? Òkú ajá, tàbí eṣinṣin?
Mamuli owai i puka mai nei ke alii o ka Iseraela? e alualu ana oe ia wai? mamuli o ka ilio make anei? mamuli o ka ukulele anei?
15 Kí Olúwa ó ṣe onídàájọ́, kí ó sì dájọ́ láàrín èmi àti ìwọ, kí ó sì gbèjà mi, kí ó sì gbà mí kúrò lọ́wọ́ rẹ.”
O Iehova ka lunakanawai, a nana e hooponopono iwaena o kaua, a nana hoi e hooponopono mai i kuu mea, a e hoopakele mai ia'u mai kou lima ae.
16 Ó sì ṣe, nígbà tí Dafidi sì dákẹ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún Saulu, Saulu sì wí pé, “Ohùn rẹ ni èyí bí, Dafidi ọmọ mi?” Saulu sì gbé ohùn rẹ̀ sókè, ó sọkún.
A pau ae la ka Davida olelo ana'ku i keia mau olelo ia Saula; i mai la o Saula, O kou leo anei keia, e Davida kuu keiki? a hookiekie ae la o Saula i kona leo iluna, a uwe iho la.
17 Ó sì wí fún Dafidi pé, “Ìwọ ṣe olódodo jù mí lọ; nítorí pé ìwọ ti fi ìre san án fún mi, èmi fi ibi san án fún ọ.
I aku la oia ia Davida, Ua oi aka kou pono mamua o ko'u: no ka mea, ua hana pono mai oe ia'u a ua hana ino aku au ia oe.
18 Ìwọ sì fi oore tí ìwọ ti ṣe fún mi hàn lónìí: nígbà tí ó jẹ́ pé, Olúwa ti fi ẹ̀mí mi lé ọ lọ́wọ́, ìwọ kò sì pa mí.
A ua hoike mai oe i keia la i kau hana pono mai ia'u: no ka mea, i ko Iehova hoolilo ana ia'u iloko o kou lima, aole oe i pepehi mai ia'u.
19 Nítorí pé bí ènìyàn bá rí ọ̀tá rẹ̀, ó lè jẹ́ kí ó lọ ní àlàáfíà bí? Olúwa yóò sì fi ìre san èyí ti ìwọ ṣe fún mi lónìí.
Ina i loaa i ke kanaka kona enemi, e kuu ola aku anei kela ia ia? no ia mea, e uku mai o Iehova ia oe i ka pono no ka mea au i hana mai ai ia'u i keia la.
20 Wò ó, èmi mọ̀ nísinsin yìí pé, nítòótọ́ ìwọ ó jẹ ọba, àti pé ìjọba Israẹli yóò sì fi ìdí múlẹ̀ ní ọwọ́ rẹ.
Ano hoi, ua ike maopopo no au, e lilo auanei oe i alii, a e hookupaaia ke aupuni o ka Iseraela iloko o kou lima.
21 Sì búra fún mi nísinsin yìí ní orúkọ Olúwa, pé, ìwọ kì yóò gé irú-ọmọ mi kúrò lẹ́yìn mi, àti pé, ìwọ kì yóò pa orúkọ mi run kúrò ní ìdílé baba mi.”
Ano hoi, e hoohiki mai oe ia'u ma Iehova, i ole oe e hooki iho i ka'u hua mahope o'u, i ole hoi oe e hooki i kuu inoa mai ka hale aku o ko'u makuakane.
22 Dafidi sì búra fún Saulu. Saulu sì lọ sí ilé rẹ̀; ṣùgbọ́n Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì gòkè lọ sí ihò náà.
A hoohiki aku la o Davida ia Saula, a hoi aku la o Saula i kona wahi; aka, pii aku la o Davida me kona poe kanaka ma kahi paa.

< 1 Samuel 24 >