< 1 Samuel 22 >

1 Dafidi sì kúrò níbẹ̀, ó sì sá sí ihò Adullamu; nígbà tí àwọn arákùnrin rẹ̀ àti ìdílé baba rẹ̀ sì gbọ́, wọ́n sì sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ọ́ wá níbẹ̀.
Gath lamkah loh David cet tih Adullam lungko la a poeng a hal. Te vaengah a manuca rhoek neh a napa imkhui loh boeih a yaak uh tih anih taeng la suntla uh.
2 Olúkúlùkù ẹni tí ó tí wà nínú ìpọ́njú, àti olúkúlùkù ẹni tí ó ti jẹ gbèsè, àti olúkúlùkù ẹni tí ó wà nínú ìbànújẹ́, sì kó ara wọn jọ sọ́dọ̀ rẹ̀, òun sì jẹ́ olórí wọn; àwọn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ sì tó ìwọ̀n irinwó ọmọkùnrin.
Te vaengah a caeknah kah hlang boeih, David taengah lai aka ba hlang boeih, hinglu khahing hlang boeih loh anih taengla coi uh thae. Te dongah amih taengah mangpa la om tih hlang ya li tluk loh anih taengah om uh.
3 Dafidi sì ti ibẹ̀ náà lọ sí Mispa tí Moabu: ó sì wí fún ọba Moabu pé, “Jẹ́ kí baba àti ìyá mi, èmi bẹ̀ ọ́ wá bá ọ gbé, títí èmi yóò fi mọ ohun ti Ọlọ́run yóò ṣe fún mi.”
David tah te lamloh Moab Mizpeh la cet tih, Moab manghai taengah, “Pathen loh kai ham a saii te ka ming duela a nu neh a pa he nang taengah cu mai saeh,” a ti nah.
4 Ó sì mú wọn wá síwájú ọba Moabu; wọ́n sì bá á gbé ní gbogbo ọjọ́ tí Dafidi fi wà nínú ihò náà.
Te tlam te Moab manghai kah mikhmuh ah amih te a khuen tih rhalvong khuiah David a om tue khuiah Moab manghai neh kho a sak uh.
5 Gadi wòlíì sí wí fún Dafidi pé, “Ma ṣe gbé inú ihò náà, yẹra, kí o sí lọ sí ilẹ̀ Juda.” Nígbà náà ni Dafidi sì yẹra, ó sì lọ sínú igbó Hereti.
Tonghma Gad loh David taengah, “Rhalvong khuiah om voel boeh, cet lamtah Judah kho te namah hamla kun thil,” a ti nah. Te dongah David te cet tih Hereth duup te a paan.
6 Saulu si gbọ́ pé a rí Dafidi àti àwọn ọkùnrin tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀; Saulu sì ń bẹ ní Gibeah lábẹ́ igi tamariski ní Rama; ọ̀kọ̀ rẹ̀ sì ń bẹ lọ́wọ́ rẹ̀, àti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ sì dúró tì í.
David neh anih taengkah hlang rhoek a phoe te Saul loh a yaak. Te vaengah Saul te Gibeah thaehhing kah kolanhlaeng hmuiah ngol tih a kut dongah caai a pom. A sal rhoek long khaw anih te boeih a pai thil uh.
7 Nígbà náà ni Saulu wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ tí ó dúró tì í, pé, “Ǹjẹ́ ẹ gbọ́ ẹ̀yin ará Benjamini, ọmọ Jese yóò ha fún olúkúlùkù yín ni oko ọgbà àjàrà bí? Kí ó sì sọ gbogbo yin dì olórí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti olórí ọ̀rọ̀ọ̀rún bí?
Saul loh amah aka pai thil a sal rhoek te, “Benjamin ca rhoek loh ya uh lah, Jesse capa loh nangmih boeih te khohmuen neh misur te m'paek aya? Nangmih te thawngkhat mangpa neh yakhat mangpa la boeih ng'khueh aya?
8 Tí gbogbo yín di ìmọ̀lù sí mi, tí kò sì sí ẹnìkan tí ó sọ létí mi pé, ọmọ mi ti bá ọmọ Jese mulẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kó sì sí ẹnìkan nínú yín tí ó ṣàánú mi, tí ó sì sọ ọ́ létí mi pé, ọmọ mi mú kí ìránṣẹ́ mi dìde sí mi láti ba dè mí, bí ó ti rí lónìí.”
Nangmih loh kai he boeih nan hlaengtang thil uh ngawn dae kai capa loh Jesse capa neh paipi a saii vaengah kai hna ah a kun moenih. Tihnin kah bangla kai he rhongngol thil ham ka capa loh ka sal a pai puei te kai ham ko aka thae tih kai hna ah aka thui khaw na om uh moenih,” a ti nah.
9 Doegi ará Edomu tí a fi jẹ olórí àwọn ìránṣẹ́ Saulu, sì dáhùn wí pé, “Èmi rí ọmọ Jese, ó wá sí Nobu, sọ́dọ̀ Ahimeleki ọmọ Ahitubu.
Tedae Saul kah sal rhoek taengah aka pai Edom hoel Doeg loh a doo tih, “Jesse capa te ka hmuh, Nob kah Ahitub capa Ahimelek taengla pawk coeng.
10 Òun sì béèrè lọ́dọ̀ Olúwa fún un, ó sì fún un ní oúnjẹ, ó sí fún un ni idà Goliati ará Filistini.”
Anih ham BOEIPA a dawt pah tih anih te lampu a paek. Te phoeiah Philisti Goliath kah cunghang te anih taengla a paek,” a ti nah.
11 Ọba sì ránṣẹ́ pe Ahimeleki àlùfáà, ọmọ Ahitubu àti gbogbo ìdílé baba rẹ̀, àwọn àlùfáà tí ó wà ni Nobu: gbogbo wọn ni ó sì wá sọ́dọ̀ ọba.
Te dongah manghai loh Ahitub capa khosoih Ahimelek neh Nob ah khosoih aka bi a napa imkhui boeih te a tah tih a khue. Te dongah amih te manghai taengla boeih ha pawk uh.
12 Saulu sì wí pé, “Ǹjẹ́ gbọ́, ìwọ ọmọ Ahitubu.” Òun sì wí pé, “Èmi nìyìí olúwa mi.”
Saul loh, “Ahitub capa, hnatun lah,” a ti nah vanbangla, “Ka om he ka boeipa,” a ti nah.
13 Saulu sì wí fún un pé, “Kí ni ó dé tí ẹ̀yin fi ṣọ̀tẹ̀ sí mi, ìwọ àti ọmọ Jese, tí ìwọ fi fún un ní àkàrà, àti idà, àti ti ìwọ fi béèrè fún un lọ́dọ̀ Ọlọ́run kí òun lè dìde sí mi, láti ba dè mí, bí ó ti rí lónìí.”
Te phoeiah anih te Saul loh, “Balae tih kai he nang neh Jesse capa loh nan hlaengtang thil tih, anih te buh neh cunghang na paek. Tihnin kah bangla kai aka pai thil tih rhongngol thil ham a anih yueng la Pathen na dawt?” a ti nah.
14 Ahimeleki sì dá ọba lóhùn, ó sì wí pé, “Ta ni ó jẹ́ olóòtítọ́ nínú gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ bí Dafidi, ẹni tí ó jẹ́ àna ọba, ẹni tí ó ń gbọ́ tìrẹ, tí ó sì ni ọlá ní ilé rẹ.
Ahimelek loh manghai te a doo tih, “David bangla aka cak tih manghai cava te na sal rhoek boeih khuiah ulae aka om. Na taengom lamkah nong mai cakhaw na imkhui ah a oep uh.
15 Òní lèmi ó ṣẹ̀ṣẹ̀ máa béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run fún un bí? Kí èyí jìnnà sí mi: kí ọba má ṣe ka nǹkan kan sí ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́rùn, tàbí sí gbogbo ìdílé baba mi: nítorí pé ìránṣẹ́ rẹ̀ kò mọ̀kan nínú gbogbo nǹkan yìí, díẹ̀ tàbí púpọ̀.”
Tihnin ah anih ham Pathen ka dawt he ka uem a, kai lamkah tah savisava, manghai loh a sal neh a pa cako boeih taengah olcen kama khueh boel saeh. Na sal loh hekah olka a yit a len khaw boeih a ming moenih,” a ti nah.
16 Ọba sì wí pé, “Ahimeleki, kíkú ni ìwọ yóò kú, ìwọ àti gbogbo ìdílé baba rẹ̀.”
Tedae manghai loh, “Ahimelek, namah khaw na pa imkhui boeih khaw na duek rhoe na duek ni,” a ti nah.
17 Ọba sì wí fún àwọn aṣáájú ti máa ń sáré níwájú ọba, tí ó dúró tì í pé, “Yípadà kí ẹ sì pa àwọn àlùfáà Olúwa; nítorí pé ọwọ́ wọn wà pẹ̀lú Dafidi, àti nítorí pé wọ́n mọ ìgbà tí òun sá, wọn kò sì sọ ọ́ létí mi.” Ṣùgbọ́n àwọn ìránṣẹ́ ọba kò sì jẹ́ fi ọwọ́ wọn lé àwọn àlùfáà Olúwa láti pa wọ́n.
Te phoeiah manghai loh a taengkah aka pai aka cungpoeh rhoek taengah, “BOEIPA kah khosoih te vael uh lamtah ngawn. Amih kut khaw David taengah nuen van tih David a yong te a ming uh lalah kai hna ah phoe puei uh pawh,” a ti nah. Tedae BOEIPA khosoih rhoek cuuk thil ham neh a kut hlah thil ham tah manghai kah sal rhoek loh huem uh pawh.
18 Ọba sì wí fún Doegi pé, “Ìwọ yípadà, kí o sì pa àwọn àlùfáà!” Doegi ará Edomu sì yípadà, ó sì kọlu àwọn àlùfáà, ó sì pa wọ́n ní ọjọ́ náà, àrùnlélọ́gọ́rin ènìyàn ti ń wọ aṣọ ọ̀gbọ̀ efodu.
Te vaengah manghai loh Doeg te, “Doeg nang loh vael lamtah khosoih rhoek te cuuk thil,” a ti nah. Te dongah Edom hoel Doeg loh khosoih rhoek te a vael tih a cuuk thil. Te dongah takhlawk hnisui aka vah hlang sawmrhet panga te hnin at dongah a duek sak.
19 Ó sì fi ojú idà pa ara Nobu, ìlú àwọn àlùfáà náà àti ọkùnrin àti obìnrin, ọmọ wẹ́wẹ́, àti àwọn tí ó wà lẹ́nu ọmú, àti màlúù, àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àti àgùntàn.
Khosoih rhoek kah khopuei Nob te khaw cunghang ha neh a ngawn tih, tongpa khaw huta, camoe, cahni khaw, vaito, laak neh tu khaw cunghang ha neh a thup.
20 Ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Ahimeleki ọmọ Ahitubu tí a ń pè ní Abiatari sì bọ́; ó sì sá àsálà tọ Dafidi lọ.
Tedae Ahitub capa Ahimelek kah a capa pakhat tah loeih. Anih ming tah Abiathar tih David hnukah yong.
21 Abiatari sì fihan Dafidi pé Saulu pa àwọn àlùfáà Olúwa tán.
Saul loh BOEIPA kah khosoih rhoek a ngawn te Abiathar loh David taengla a puen pah.
22 Dafidi sì wí fún Abiatari pé, “Èmi ti mọ̀ ní ọjọ́ náà, nígbà tí Doegi ará Edomu ti wà níbẹ̀ pé, nítòótọ́ yóò sọ fún Saulu: nítorí mi ni a ṣe pa gbogbo ìdílé baba rẹ.
David loh Abiathar taengah, “Edom hoel Doeg loh Saul taengah puen rhoe puen pahoi ni tila amah tekah khohnin ah ka ming, na pa imkhui kah a hinglu boeih te kai ni laikung coeng.
23 Ìwọ jókòó níhìn-ín lọ́dọ̀ mi, má ṣe bẹ̀rù, nítorí pé ẹni ti ń wá ẹ̀mí mi, ó ń wá ẹ̀mí rẹ, ṣùgbọ́n lọ́dọ̀ mi ni ìwọ ó wà ní àìléwu.”
Kai taengah khosa lamtah kai kah hinglu han toem khaw, nang kah hinglu han toem akhaw anih te rhih boeh. Kai taengah tah na sueng coeng,” a ti nah.

< 1 Samuel 22 >