< 1 Samuel 21 >

1 Dafidi sì wá sí Nobu sọ́dọ̀ Ahimeleki àlùfáà, Ahimeleki sì bẹ̀rù láti pàdé Dafidi, ó sì wí fún un pé, “Èéha ti rí tí o fi ṣe ìwọ nìkan, àti tí kò sì sí ọkùnrin kan tí ó pẹ̀lú rẹ?”
Na rĩrĩ, Daudi agĩthiĩ Nobu, kũrĩ Ahimeleku ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai. Ahimeleku aamũtũnga akĩinaina, akĩmũũria atĩrĩ, “Kaĩ ũrĩ wiki nĩkĩ? Nĩ kĩĩ mũtarĩ na mũndũ ũngĩ?”
2 Dafidi sì wí fún Ahimeleki àlùfáà pé, “Ọba pàṣẹ iṣẹ́ kan fún mi, ó sì wí fún mi pé, ‘Má ṣe jẹ́ kí ẹnìkan mọ ìdí iṣẹ́ náà ti mo rán ọ, àti èyí tí èmi ti pàṣẹ fún ọ.’ Èmi sì yan àwọn ìránṣẹ́ mi sí ibí báyìí.
Daudi agĩcookeria Ahimeleku ũcio mũthĩnjĩri-Ngai atĩrĩ, “Nĩ mũthamaki ũnjathĩte ngeke ũndũ mũna na akanjĩĩra atĩrĩ, ‘Mũndũ o na ũ ndakamenye ũndũ ũrĩa ngũtũmĩte na ũrĩa ngwathĩte.’ No andũ akwa-rĩ, nĩ ndĩmerĩte tũcemanie handũ hana.
3 Ǹjẹ́ kín ni ó wà ní ọwọ́ rẹ̀? Fún mi ni ìṣù àkàrà márùn-ún tàbí ohunkóhun tí o bá rí.”
Na rĩrĩ, nĩ kĩĩ ũrĩ nakĩo gĩa kũrĩa? He mĩgate ĩtano, kana o kĩrĩa gĩothe ũngĩhota kuona.”
4 Àlùfáà náà sí dá Dafidi lóhùn ó sì wí pé, “Kò sí àkàrà mìíràn lọ́wọ́ mi bí kò ṣe àkàrà mímọ́. Kìkì pé bi àwọn ọmọkùnrin bá ti pa ara wọn mọ́ kúrò lọ́dọ̀ obìnrin!”
No mũthĩnjĩri-Ngai ũcio agĩcookeria Daudi atĩrĩ, “Ndirĩ na mĩgate ĩrĩa ĩhũthĩirwo kũrĩĩo, no rĩrĩ, haha nĩ harĩ mĩgate ĩrĩa mĩamũre, angĩkorwo andũ acio matihutanĩtie na andũ-a-nja.”
5 Dafidi sì dá àlùfáà náà lóhùn, ó sì wí fún un pé, “Nítòótọ́ ni a tí ń pa ara wá mọ́ kúrò lọ́dọ̀ obìnrin láti ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́ta wá, tí èmí ti jáde. Gbogbo nǹkan àwọn ọmọkùnrin náà ni ó mọ́, àti àkàrà náà sì wá dàbí àkàrà mìíràn, pàápàá nígbà tí ó jẹ́ pé òmíràn wà tí a yà sí mímọ́ lónìí nínú ohun èlò náà!”
Daudi agĩcookia atĩrĩ, “Ti-itherũ tũtikoretwo hamwe na andũ-a-nja, o ta ũrĩa arĩ mũtugo witũ rĩrĩa rĩothe ngumagara. Indo cia andũ aya nĩ theru o na gũtuĩka marĩ mawĩra-inĩ matarĩ maamũre. Ũmũthĩ indo ciao itikĩrĩ nyamũre makĩria!”
6 Bẹ́ẹ̀ ni àlùfáà náà sì fi àkàrà mímọ́ fún un; nítorí tí kò sí àkàrà mìíràn níbẹ̀ bí kò ṣe àkàrà ìfihàn tí a ti kó kúrò níwájú Olúwa, láti fi àkàrà gbígbóná síbẹ̀ ní ọjọ́ tí a kó o kúrò.
Nĩ ũndũ ũcio mũthĩnjĩri-Ngai ũcio akĩmũnengera mĩgate ĩyo mĩamũre, nĩgũkorwo hau hatiarĩ na mĩgate ĩngĩ tiga mĩgate ĩrĩa yaigagwo mbere ya Jehova, na nĩyeheretio mbere ya Jehova mũthenya ũcio, na hakaigwo mĩgate ĩngĩ mĩhiũ.
7 Ọkùnrin kan nínú àwọn ìránṣẹ́ Saulu sì ń bẹ níbẹ̀ lọ́jọ́ náà, tí a tí dádúró síwájú Olúwa; orúkọ rẹ̀ sì ń jẹ́ Doegi, ará Edomu olórí nínú àwọn darandaran Saulu.
Na rĩrĩ, mũthenya ũcio, haarĩ na mũndũ ũmwe warĩ ndungata ya Saũlũ, aahingĩrĩirio hau mbere ya Jehova; nake eetagwo Doegu ũrĩa Mũedomu, ũrĩa warĩ mũnene wa arĩithi a Saũlũ.
8 Dafidi sì tún wí fún Ahimeleki pé, “Kò sí ọ̀kọ̀ tàbí idà lọ́wọ́ rẹ níhìn-ín? Nítorí tí èmi kò mú idà mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò mú nǹkan ìjà mi lọ́wọ́, nítorí pé iṣẹ́ ọba náà jẹ́ iṣẹ́ ìkánjú.”
Daudi akĩũria Ahimeleku atĩrĩ, “Kaĩ ũtarĩ na itimũ kana rũhiũ rwa njora haha? Ndinooka na rũhiũ rwakwa rwa njora kana kĩndũ kĩngĩ kĩa mbaara, nĩ ũndũ wĩra wa mũthamaki uuma wa ihenya.”
9 Àlùfáà náà sì wí pé, “Idà Goliati ará Filistini tí ó pa ní àfonífojì Ela ní ń bẹ, wò ó, a fi aṣọ kan wé e lẹ́yìn efodu; bí ìwọ yóò bá mú èyí, mú un; kò sì sí òmíràn níhìn-ín mọ́ bí kò ṣe ọ̀kan náà.” Dafidi sì wí pé, “Kò sí èyí tí ó dàbí rẹ̀ fún mi.”
Mũthĩnjĩri-Ngai ũcio agĩcookia atĩrĩ, “Rũhiũ rwa njora rwa Goliathũ, Mũfilisti ũrĩa woragĩire Gĩtuamba-inĩ kĩa Ela, rũrĩ haha; naruo ruohetwo na taama rũkaigwo thuutha wa ebodi. Angĩkorwo nĩũkũrwenda-rĩ, ruoe; gũtirĩ na rũhiũ rũngĩ rwa njora tiga o rũu.” Daudi akiuga atĩrĩ, “Gũtirĩ rũhiũ rũngĩ taruo; kĩrũũnengere.”
10 Dafidi sì dìde, o sì sá ni ọjọ́ náà níwájú Saulu, ó sì lọ sọ́dọ̀ Akiṣi, ọba Gati.
Mũthenya ũcio Daudi akĩũrĩra Saũlũ, agĩthiĩ kũrĩ Akishi mũthamaki wa Gathu.
11 Àwọn ìránṣẹ́ Akiṣi sì wí fún un pé, “Èyí ha kọ́ ní Dafidi ọba ilẹ̀ náà? Ǹjẹ́ wọn kò ha ti dárin ti wọ́n sì gbe orin nítorí rẹ̀, tí wọ́n sì jó pé, “‘Saulu pa ẹgbẹ̀rún tirẹ̀. Dafidi sì pa ẹgbàárùn-ún tirẹ̀’?”
No ndungata cia Akishi ikĩmwĩra atĩrĩ, “Githĩ ũyũ ti Daudi, ũrĩa mũthamaki wa bũrũri? Githĩ tiwe mainagĩra nyĩmbo-inĩ ciao atĩrĩ: “‘Saũlũ nĩeyũragĩire andũ ngiri nyingĩ, na Daudi akeyũragĩra andũ ngiri makũmi maingĩ’?”
12 Dafidi sì pa ọ̀rọ̀ wọ̀nyí í mọ́ ni ọkàn rẹ̀, ó sì bẹ̀rù Akiṣi ọba Gati gidigidi.
Nake Daudi akĩiga ũhoro ũcio ngoro-inĩ na agĩĩtigĩra Akishi mũthamaki wa Gathu mũno.
13 Òun sì pa ìṣe rẹ̀ dà níwájú wọn, ó sì sọ ara rẹ̀ di aṣiwèrè ní ọwọ́ wọn, ó sì ń fi ọwọ́ rẹ̀ ha ìlẹ̀kùn ojú ọ̀nà, ó sì ń wá itọ́ sí irùngbọ̀n rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio akĩĩgũrũkithia mbere yao; na rĩrĩa aarĩ moko-inĩ mao, agĩĩtua ta mũndũ mũgũrũki, akĩharaga mĩrango ya kĩhingo, agĩitaga rũta rũikũrũkanĩtie na nderu ciake.
14 Nígbà náà ni Akiṣi wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Wó o, nítorí kín ni ẹ̀yin ṣe mú un tọ̀ mí wá.
Akishi akĩĩra ndungata ciake atĩrĩ, “Ta rorai mũndũ ũyũ! Nĩ mũgũrũku! Mwakĩmũrehe kũrĩ niĩ nĩkĩ?
15 Mo ha ni un fi aṣiwèrè ṣe? Tí ẹ̀yin fi mú èyí tọ̀ mí wá láti hu ìwà aṣiwèrè níwájú mi? Eléyìí yóò ha wọ inú ilé mi?”
Kaĩ nyiihĩtie agũrũki atĩ nĩguo mũndehere mũndũ ũyũ haha eke maũndũ ta maya mbere yakwa? Mũndũ ũyũ no nginya oke nyũmba yakwa?”

< 1 Samuel 21 >