< 1 Samuel 21 >

1 Dafidi sì wá sí Nobu sọ́dọ̀ Ahimeleki àlùfáà, Ahimeleki sì bẹ̀rù láti pàdé Dafidi, ó sì wí fún un pé, “Èéha ti rí tí o fi ṣe ìwọ nìkan, àti tí kò sì sí ọkùnrin kan tí ó pẹ̀lú rẹ?”
David chu Ahimelech thempupa kimupi din Nob khopi’ah achen ahi. Ahimelech in David chu amu phat in ati anahot’in, “Itia nachangseh nahim? Ipijeh’a mikhatbeh in nahin kilhonpi louham?” tin ana dongin ahi.
2 Dafidi sì wí fún Ahimeleki àlùfáà pé, “Ọba pàṣẹ iṣẹ́ kan fún mi, ó sì wí fún mi pé, ‘Má ṣe jẹ́ kí ẹnìkan mọ ìdí iṣẹ́ náà ti mo rán ọ, àti èyí tí èmi ti pàṣẹ fún ọ.’ Èmi sì yan àwọn ìránṣẹ́ mi sí ibí báyìí.
David in adonbut’in, “Lengpan kin chomkhat’a eihinsol ahibouve, ipibol dia kahung hi koimacha hetsahlou dia eihil chah ahin, chule kasepaite chun katepna mun chom khat’a eikimupi diuva kaseipeh ahi,” ati
3 Ǹjẹ́ kín ni ó wà ní ọwọ́ rẹ̀? Fún mi ni ìṣù àkàrà márùn-ún tàbí ohunkóhun tí o bá rí.”
“Nehle chah ipipi nanei em? Changlhah pheng nga ahiloule, nehthei adang ipi um'em neipen,” ati.
4 Àlùfáà náà sí dá Dafidi lóhùn ó sì wí pé, “Kò sí àkàrà mìíràn lọ́wọ́ mi bí kò ṣe àkàrà mímọ́. Kìkì pé bi àwọn ọmọkùnrin bá ti pa ara wọn mọ́ kúrò lọ́dọ̀ obìnrin!”
Hichun thempupan jong, adonbut in “Keihon changlhah mai mai kaneipouve, ahinlah koitobang nailamcha-a numeiya kisuboh louho dingin changlhah theng kanei uve,” ati.
5 Dafidi sì dá àlùfáà náà lóhùn, ó sì wí fún un pé, “Nítòótọ́ ni a tí ń pa ara wá mọ́ kúrò lọ́dọ̀ obìnrin láti ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́ta wá, tí èmí ti jáde. Gbogbo nǹkan àwọn ọmọkùnrin náà ni ó mọ́, àti àkàrà náà sì wá dàbí àkàrà mìíràn, pàápàá nígbà tí ó jẹ́ pé òmíràn wà tí a yà sí mímọ́ lónìí nínú ohun èlò náà!”
Hichun David in, “Lungkham hihin, keiman, kamite ho adeh’a galsat dinga akiche tengule, numeija kona kikangse louho kaphal jipoi, gamkhol mai mai kache tengu jong hiche thudol’a kisuboh ngailou ahiuve, achutile hiche khohsah tum neiya kholjinna’a iti thenda diu ham!” ati.
6 Bẹ́ẹ̀ ni àlùfáà náà sì fi àkàrà mímọ́ fún un; nítorí tí kò sí àkàrà mìíràn níbẹ̀ bí kò ṣe àkàrà ìfihàn tí a ti kó kúrò níwájú Olúwa, láti fi àkàrà gbígbóná síbẹ̀ ní ọjọ́ tí a kó o kúrò.
Nehding dang aumtah lou jeh'in, thempupan changlhah kithensosa chu David apetai, ajeh chu changlhah Pathena tosa bou chu anei ahin, hichu athah akito nitengle changlhah chu kikhel dohji ahi. Chule hiche nikho nitah a chu thah ana kikoi khel ahi.
7 Ọkùnrin kan nínú àwọn ìránṣẹ́ Saulu sì ń bẹ níbẹ̀ lọ́jọ́ náà, tí a tí dádúró síwájú Olúwa; orúkọ rẹ̀ sì ń jẹ́ Doegi, ará Edomu olórí nínú àwọn darandaran Saulu.
Edomakon Doeg kiti mipa khat, Saul gancha ching lamkaipu khat anaum khan, houin mun’abol lhing ding kin aneijeh in anaumden khan ahi.
8 Dafidi sì tún wí fún Ahimeleki pé, “Kò sí ọ̀kọ̀ tàbí idà lọ́wọ́ rẹ níhìn-ín? Nítorí tí èmi kò mú idà mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò mú nǹkan ìjà mi lọ́wọ́, nítorí pé iṣẹ́ ọba náà jẹ́ iṣẹ́ ìkánjú.”
David in Ahimeleh jah’a, “Nakoma tengcha ahiloule chemjam um'em? Lengpa kin’a kigoman louva kahung ahin, manchah ima kahin choilou ahi!” ati.
9 Àlùfáà náà sì wí pé, “Idà Goliati ará Filistini tí ó pa ní àfonífojì Ela ní ń bẹ, wò ó, a fi aṣọ kan wé e lẹ́yìn efodu; bí ìwọ yóò bá mú èyí, mú un; kò sì sí òmíràn níhìn-ín mọ́ bí kò ṣe ọ̀kan náà.” Dafidi sì wí pé, “Kò sí èyí tí ó dàbí rẹ̀ fún mi.”
Hichun Ahimelech in, “Elah phaicham’a nathana pa, Philistine mipa Goliath chemjam bou chu kanei’e; hikoma thempu von kikoina nunglam’a khun pon’in akichun in aume, nadeilekilah in, adangvang aumpoi” ati. Chuin David in ajah’a, “Hichu neipen! Chusang’a phajo le hoijo chemjam adang umponte,” ati.
10 Dafidi sì dìde, o sì sá ni ọjọ́ náà níwájú Saulu, ó sì lọ sọ́dọ̀ Akiṣi, ọba Gati.
Hichun David Saul koma konin ajamdoh’in, Gath khopi Achish lengpa heng ajontan ahi.
11 Àwọn ìránṣẹ́ Akiṣi sì wí fún un pé, “Èyí ha kọ́ ní Dafidi ọba ilẹ̀ náà? Ǹjẹ́ wọn kò ha ti dárin ti wọ́n sì gbe orin nítorí rẹ̀, tí wọ́n sì jó pé, “‘Saulu pa ẹgbẹ̀rún tirẹ̀. Dafidi sì pa ẹgbàárùn-ún tirẹ̀’?”
Ahinlah Achish lenggam sung’a lamkaiho chu akomuva aumding chu akipah pouvin ahi. Amahon, “Hiche mipa hi agamsung’a leng changsa David chu hilou haimo? Miho lamuva, ama chung changa hi la asah uva Saul in mi asang asangin athat’in, David in vang sangsom somin athat’e, tia alachoipao chu hilou ham?” tin adonguve.
12 Dafidi sì pa ọ̀rọ̀ wọ̀nyí í mọ́ ni ọkàn rẹ̀, ó sì bẹ̀rù Akiṣi ọba Gati gidigidi.
Hiche athuseiho chu David in ajah phat’in Gath lengpa Achish chu akicha lheh jeng tan ahi.
13 Òun sì pa ìṣe rẹ̀ dà níwájú wọn, ó sì sọ ara rẹ̀ di aṣiwèrè ní ọwọ́ wọn, ó sì ń fi ọwọ́ rẹ̀ ha ìlẹ̀kùn ojú ọ̀nà, ó sì ń wá itọ́ sí irùngbọ̀n rẹ̀.
Hijeh chun David jong aki ngolsah’in, kotpi phungdung ho chu ajihpolin, chule akhalhang dunga achilphon akaisah deh duhin jeng in ahi.
14 Nígbà náà ni Akiṣi wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Wó o, nítorí kín ni ẹ̀yin ṣe mú un tọ̀ mí wá.
Achaina in Achish lengpan amiteho komah, “Hitobang mingol chu kahenga nahung sah’u ham?
15 Mo ha ni un fi aṣiwèrè ṣe? Tí ẹ̀yin fi mú èyí tọ̀ mí wá láti hu ìwà aṣiwèrè níwájú mi? Eléyìí yóò ha wọ inú ilé mi?”
Kakimvella hitobang mingol kaneilouva nabollu ham? Ipi dinga motchon chon a eisuboi ding bep’a ka-insunglai tah’a, kamasang’a hichepa hinpuilut nahiuvam?” tin ahung eojah jeng in ahi.

< 1 Samuel 21 >