< 1 Samuel 2 >

1 Hana sì gbàdúrà pé, “Ọkàn mi yọ̀ sí Olúwa; ìwo agbára mi ni a sì gbé sókè sí Olúwa. Ẹnu mi sì gbòòrò lórí àwọn ọ̀tá mi, nítorí ti èmi yọ̀ ni ìgbàlà rẹ̀.
Ha: na da Godema amane sia: ne gadoi, “Hina Gode da na dogo ganodini hahawane hou nabalesi dagoi. Na da Ea nama hamoi amoga hahawane bagadedafa gala. Na da na ha lai dunu amoba: le ousa. Gode da nama bagade fidibiba: le, na da hahawane bagade.
2 “Kò sí ẹni tí ó mọ́ bi Olúwa; kò sí ẹlòmíràn bí kò ṣe ìwọ; kò sì sí àpáta bi Ọlọ́run wa.
Dunu afae da Hina Gode Ea hadigi agoai da hamedafa gala, E agoai hamedafa gala. Ea ouligibi agoane enoga da hamedafa ouligisa.
3 “Má ṣe halẹ̀; má ṣe jẹ́ kí ìgbéraga ti ẹnu yín jáde nítorí pé Ọlọ́run olùmọ̀ ni Olúwa, láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ wá ni a ti ń wọn ìwà.
Dilia ha: gi hidabe go yolema! Amola dilia hidale nodosu sia: yolesili ouiya: ma! Bai Hina Gode da liligi huluanedafa dawa: Amola E da dunu ilia hamoi huluane defele fofada: nana.
4 “Ọ̀run àwọn alágbára ti ṣẹ́, àwọn tí ó ṣe aláìlera ni a fi agbára dì ní àmùrè.
Nimi bagade gegesu dunu ilia oulali da fili fasisa. Be asaboi dunu da bu gasa fisa.
5 Àwọn tí ó yọ̀ fún oúnjẹ ti fi ara wọn ṣe alágbàṣe, àwọn tí ebi ń pa kò sì ṣe aláìní. Tó bẹ́ẹ̀ tí àgàn fi bí méje. Ẹni tí ó bímọ púpọ̀ sì di aláìlágbára.
Ha: su hame dawa: dunu da bu ha: beba: le, ha: i manu lama: ne hawa: hamosa. Be ha: su dunu da bu hame ha: sa. Dunuga lai aligime uda da wali mano fesuale lalelegesa. Be mano galusulu uda ea mano huluane da hagia: sa.
6 “Olúwa pa ó sì sọ di ààyè; ó mú sọ̀kalẹ̀ lọ sí isà òkú, ó sì gbé dìde. (Sheol h7585)
Hina Gode da fane legesa amola bu wa: lesisu dawa: E da dunu bogoi sogega asunasisa, amola amo bu sinidigima: ne oule maha. (Sheol h7585)
7 Olúwa sọ di tálákà; ó sì sọ di ọlọ́rọ̀; ó rẹ̀ sílẹ̀, ó sì gbé sókè.
E da dunu oda liligi bagade gaguma: ne hamosa, amola oda mae gaguiwane esaloma: ne hamosa. E da oda fonobonesisa amola oda bagalesisa.
8 Ó gbé tálákà sókè láti inú erùpẹ̀ wá, ó gbé alágbe sókè láti orí òkìtì eérú wá, láti mú wọn jókòó pẹ̀lú àwọn ọmọ-aládé, láti mu wọn jogún ìtẹ́ ògo, “Nítorí pé ọ̀wọ́n ayé ti Olúwa ni, ó sì ti gbé ayé ka orí wọn.
Hina Gode da hame gagui dunu gulu dabolei dialu, amo gaguia gadolesisa, amola sugui dunu ilia da: i dioi fisima: ne wa: legadolesisa. Ea hamobeba: le, sugui dunu da hina bagade ea mano amoma na: iyado agoane esala amola dunu eno da ilima nodone dawa: digisa. Osobo bagade ea baidafa da Hina Gode Ea: Amo da: iya E da osobo bagade hahamoi.
9 Yóò pa ẹsẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ mọ́, àwọn ènìyàn búburú ni yóò dákẹ́ ní òkùnkùn. “Nípa agbára kò sí ọkùnrin tí yóò borí.
Hina Gode da Ema molole fa: no bobogesu dunu ilia esalusu noga: le ouligisa. Be wadela: i hamosu dunu da gasi ganodini alalolesisa. Amaiba: le, dunu da hi gasaga hasalimusa: hame dawa:
10 A ó fọ́ àwọn ọ̀tá Olúwa túútúú; láti ọ̀run wá ni yóò sán àrá sí wọn; Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ òpin ayé. “Yóò fi agbára fún ọba rẹ̀, yóò si gbé ìwo ẹni àmì òróró rẹ̀ sókè.”
Hina Gode da Ema ha lai dunu huluane wadela: lesimu. Ilia da Ea ougi sia: gugelebe bagade agoane Hebene gadodili dabe nabimu. Hina Gode da osobo bagade fi dunu huluane ilima fofada: mu. E da Ea hina bagade dunu ilima gasa imunu. E da Ea ilegei hina bagade amo hasalima: ne hamomu.”
11 Elkana sì lọ sí Rama, sí ilé rẹ̀, ọmọ náà sì ń ṣe ìránṣẹ́ fún Olúwa níwájú Eli àlùfáà.
Amalalu, Elega: ina da La: ima moilaiga buhagi. Be goi Sa: miuele da Siailou moilaiga esalu. E da Hina Gode Ea hawa: hamosu, amola gobele salasu dunu Ilai da e ouligisu.
12 Àwọn ọmọ Eli sì jẹ́ ọmọ Beliali; wọn kò mọ Olúwa.
Ilai egefela da wadela: i hamosu dunu. Elea da Hina Gode Ea sia: hamedafa nabasu.
13 Iṣẹ́ àwọn àlùfáà pẹ̀lú àwọn ènìyàn ni pé nígbà tí ẹnìkan bá ṣe ìrúbọ, ìránṣẹ́ àlùfáà á dé, nígbà tí ẹran náà bá ń hó lórí iná, pẹ̀lú ọ̀pá-ẹran náà oníga mẹ́ta ní ọwọ́ rẹ̀.
14 Òun a sì fi gún inú apẹ, tàbí àgé tàbí ọpọ́n, tàbí ìkòkò, gbogbo èyí tí ọ̀pá-ẹran oníga náà bá mú wá sí òkè, àlùfáà á mú un fún ara rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń ṣe sí gbogbo Israẹli tí ó wá sí ibẹ̀ ní Ṣilo.
Amola sema gobele salasu dunu ilia enoma edegemusa: hamoi, elea da amoma hame fa: no bobogesu. Be amomane dunu da ilia Godema iasu gobele salaloba, amo gebo hu da ladalea, gobele salasu dunu ea hawa: hamosu ilia da misini ofodo gelaba gobei amo da gelaboga guili nasuga gadufili lale, gobele salasu dunu ilia fawane da amo nasu. Isala: ili dunu huluane da Siailou moilaiga gobele salasu ima: ne masu, da amo udigili wamolale nasu hou ba: i.
15 Pẹ̀lú, kí wọn tó sun ọ̀rá náà, ìránṣẹ́ àlùfáà á dé, á sì wí fún ọkùnrin tí ó ń ṣe ìrúbọ pé, “Fi ẹran fún mi láti sun fún àlùfáà; nítorí tí kì yóò gba ẹran sísè lọ́wọ́ rẹ, bí kò ṣe tútù.”
Amola, hamoma: ne sia: i eno gala da gobele salasu ohe ea sefe ofene fasili, laluma gobesisu. Be amo hamoma: ne sia: i mae dawa: le, gobele salasu hawa: hamosu dunu ela da Isala: ili dunuma amane sia: su, “Gobele salasu dunu da hu gahe hi houma: ne, nama ima. E da sosobenega gobei higamu.”
16 Bí ọkùnrin náà bá sì wí fún un pé, “Jẹ́ kí wọn ó sun ọ̀rá náà nísinsin yìí, kí o sì mú iyekíye tí ọkàn rẹ̀ bá fẹ́,” nígbà náà ni yóò dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, ṣùgbọ́n kí ìwọ ó fi í fún mi nísinsin yìí, bí kó ṣe bẹ́ẹ̀, èmi ó fi agbára gbà á.”
Be dunu da dabe bu adole iasea, “Ninia da sema defele, sefe hidadea suli sa: ima: ma, amasea fa: no dia hanai lama!” Be gobele salasu ea hawa: hamosu dunu elea amane sia: su, “Abola! Wahadafa nama ima! Dia amane hame hamosea, na da ni gasa fili logele samogemu.”
17 Ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì tóbi gidigidi níwájú Olúwa: nítorí tí àwọn ènìyàn kórìíra ẹbọ Olúwa.
Goe Ilai egefela wadela: i hou hamosu amo Hina Gode da bagadewane higale ba: i. Bai elea da Hina Godema iasu liligi amo da bai hameyale dawa: beba: le, gugunufinisisu.
18 Ṣùgbọ́n Samuẹli ń ṣe ìránṣẹ́ níwájú Olúwa, ọmọdé, ti a wọ̀ ní efodu ọ̀gbọ̀.
Wahamusu goihadi Sa: miuele da sema mida: gisa: gisu abula salawane, Hina Gode Ea hawa: hamonanu.
19 Pẹ̀lúpẹ̀lú, ìyá rẹ̀ máa ń dá aṣọ ìlekè péńpé fún un, a sì máa mú wá fún un lọ́dọọdún, nígbà tí ó bá bá ọkọ rẹ̀ gòkè wá láti ṣe ìrúbọ ọdún.
Ode huluane ea: me Ha: na da abula fonobahadi amunanu, amola egoala Godema odegamusu gobele sala ahoabe, amoga abula eagofe Sa: miuelegili gaguli ahoasu.
20 Eli súre fún Elkana àti aya rẹ̀ pé, “Kí Olúwa fún ọ ní irú-ọmọ láti ara obìnrin yìí wá, nítorí ẹ̀bùn tí ó béèrè tí ó sì tún fún Olúwa.” Wọ́n sì lọ sí ilé wọn.
Amalalu, Ilai da Elega: ina amola iduama Gode Ea Dioba: le nodoma: ne sia: su, amola Elega: inama amane sia: i, “Hina Gode da di amola dia uda alima mano alia Godema i, amo ea sogebi lama: ne, mano eno imunu da defea.” Amalalu Elega: ina amola Ha: nala da ela diasuga bu ahoasu.
21 Olúwa si bojú wo Hana, ó sì lóyún, ó bí ọmọkùnrin mẹ́ta àti ọmọbìnrin méjì. Samuẹli ọmọ náà sì ń dàgbà níwájú Olúwa.
Hina Gode da Ha: na hahawane dogolegele fidibiba: le, e da dunu mano udiana amola uda mano aduna eno lalelegei. Goihadi Sa: miuele da Hina Gode Ea hawa: hamonana asigilai.
22 Eli sì di arúgbó gidigidi, ó sì gbọ́ gbogbo èyí ti àwọn ọmọ rẹ̀ ṣe sí gbogbo Israẹli; àti bi wọ́n ti máa ń bá àwọn obìnrin sùn, tí wọ́n máa ń péjọ ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ.
Ilai da da: i hamone esalu. E da eso huluane ea mano elea Isala: ili dunuma wadela: le hamobe nabalusu. Elea da uda da Hina Gode Ea abula diasu logo holeiga hawa: hamonanu, amo amola gilisili golale, adole lasu.
23 Ó sì wí fún wọn pé, kí ni ó ti ri “Èétirí tí èmi fi ń gbọ́ irú nǹkan bẹ́ẹ̀ sí yín? Nítorí tí èmi ń gbọ́ iṣẹ́ búburú yín láti ọ̀dọ̀ gbogbo ènìyàn.
Amaiba: le, Ilai da ea mano elama amane sia: i, “Abuliba: le alia da wadela: i hou agoane hamosala: ? Dunu huluane ilia da wadela: i hou alia hamobego huluane nama alofele iaha.
24 Bẹ́ẹ̀ kọ́ ẹ̀yin ọmọ mi, nítorí kì ṣe ìròyìn rere èmi gbọ́; ẹ̀yin mú ènìyàn Olúwa dẹ́ṣẹ̀.
Ada alia: ! Go yolesima! Amo hou Hina Gode Ea fi dunu da sia: sia: dalebe da wadela: idafa.
25 Bí ẹnìkan bá ṣẹ̀ sí ẹnìkejì, onídàájọ́ yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀: ṣùgbọ́n bí ẹnìkan bá ṣẹ̀ sí Olúwa, ta ni yóò bẹ̀bẹ̀ fún un?” Wọn kò sì fi etí sí ohùn baba wọn, nítorí tí Olúwa ń fẹ́ pa wọ́n.
Dunu da dunu enoma wadela: le hamosea, Gode da amo dunu gaga: musa: dawa: Be dunu da Hina Godema wadela: le hamosea, nowa da gaga: ma: bela: ?” Be Ilai ea mano elea da eda sia: hame nabasu. Bai Hina Gode da ele fane legemusa: ilegei dagoi.
26 Ọmọ náà Samuẹli ń dàgbà, ó sì rí ojúrere lọ́dọ̀ Olúwa, àti ènìyàn pẹ̀lú.
Be goihadi Sa: miuele da Hina Godema amola dunu enoma hahawane asaboiwane asigilalu.
27 Ènìyàn Ọlọ́run kan tọ Eli wá, ó sì wí fún un pé, “Báyìí ni Olúwa wí, ‘Èmi fi ara mi hàn ní gbangba fún ilé baba rẹ, nígbà tí wọ́n ń bẹ ní Ejibiti nínú ilé Farao.
Balofede dunu (Gode Sia: Alofesu dunu) da Ilaima Hina Gode Ea adole iasu amane olelei, “Musa: dia aowa Elane amola ea sosogo fi ilia Idibidi hina bagade ea udigili hawa: hamonanoba, Na da Elanema Na hou olelei.
28 Èmi sì yàn án kúrò láàrín gbogbo ẹ̀yà Israẹli láti jẹ́ àlùfáà mi, láti rú ẹbọ lórí pẹpẹ mi, láti fi tùràrí jóná, láti wọ efodu níwájú mi, èmi sì fi gbogbo ẹbọ tí ọmọ Israẹli máa ń fi iná sun fún ìdílé baba rẹ̀.
Na da Isala: ili fi ili huluane ba: lalu, Elane ea fi fawane ilia oloda hawa: hamoma: ne, amola gabusiga: manoma ulagima: ne, amola Na hanai dawa: ma: ne Ifode (Bidegi Ga: su) salima: ne, ea fi ilegei. Amola ilia da oloda gobele salasu ha: i manu la: idi lale manusa: , Na da logo doasi dagoi.
29 Èéha ṣe tí ẹ̀yin fi tàpá sí ẹbọ àti ọrẹ mi, tí mo pàṣẹ ní ibùjókòó mi, ìwọ sì bu ọlá fún àwọn ọmọ rẹ jù mí lọ, tí ẹ sì fi gbogbo àṣàyàn ẹbọ Israẹli àwọn ènìyàn mi mú ara yín sanra.’
Na da Na fi ilima ilia Nama gobele salasu amola udigili iasu ima: ne sia: i. Abuliba: le di da dia manoma nodone dawa: lala, be Nama hame dawa: sala: ? Bai ela da ela musu alema: ne, gobele salasu amo Na fi da Nama iaha, amoga hedesi ida: iwane fawane lale naha, amo di da elea logo hame hedofasa.
30 “Nítorí náà Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí pé, ‘Èmi ti wí nítòótọ́ pé, ilé rẹ àti ilé baba rẹ, yóò máa rìn níwájú mi títí.’ Ṣùgbọ́n nísinsin yìí Olúwa wí pé, ‘Kí á má rí i! Àwọn tí ó bú ọlá fún mi ni èmi yóò bu ọlá fún, àti àwọn tí kò kà mí sí ni a ó sì ṣe aláìkàsí.
Na da Isala: ili fi ilia Hina Gode! Na da musa: dia sosogo amola dia fidafa da eso huluane Na gobele salasu hawa: hamonanumu ilegei dagoi. Be Na da waha agoane sia: sa, dia Nama gobele salabe bu hame hamomu. Be wali nowa da Nama nodone dawa: digisia, Na da amo dunuma nodone dawa: digimu. Amola nowa da Na higasea, Na da higamu.
31 Kíyèsi i, àwọn ọjọ́ ń bọ̀ tí èmi ó gé agbára rẹ kúrò, àti agbára baba rẹ, tí kì yóò sí arúgbó kan nínú ilé rẹ.
Nabima! Na da dia sosogo fi amola dia fidafa amo ganodini goimusu fane lelegemu eso da gadenesa. Amasea, dia fi ganodini dunu afae da esala hame da: i hamomu.
32 Ìwọ yóò rí wàhálà ti Àgọ́, nínú gbogbo ọlá tí Ọlọ́run yóò fi fún Israẹli; kì yóò sí arúgbó kan nínú ilé rẹ láéláé.
Amola di da da: i diomu, amola Na da Isala: ili fi dunu eno amo Na fidibi ba: sea, di da mudabe ba: mu. Be dia fi amo ganodini dunu afaega da esala hame da: i hamomu.
33 Ọkùnrin tí ó jẹ́ tìrẹ, tí èmi kì yóò gé kúrò ní ibi pẹpẹ mi ni a ó dá sí láti sọkún yọ lójú àti láti banújẹ́. Ṣùgbọ́n gbogbo irú-ọmọ ilé rẹ̀ ni a ó fi idà pa ní ààbọ̀ ọjọ́ wọn.
Be amomane Na da digaga afadafa esaloma: mu, amalu e da Nama gobele salasu dunu esaloma: mu. Be amomane e da si wadela: le amola baligiliwane da: i diomu. Amola dia sosogo fi huluane da se bagade nabawane bogogia: mu.
34 “‘Kí ni ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọmọ ọkùnrin rẹ̀ méjèèjì, Hofini àti Finehasi, yóò jẹ́ àmì fún ọ—àwọn méjèèjì yóò kú ní ọjọ́ kan náà.
Dia mano aduna amo Hofenai amola Finia: se ela da ele galu eso afaega bogomu. Amasea, dia da Na sia: i amo da dafawane galebeya dawa: mu.
35 Èmi yóò dìde fún ara mi láti gbé àlùfáà olódodo dìde fún ara mi, ẹni tí yóò ṣe gẹ́gẹ́ bí ohun tí ó wà ní ọkàn mi àti inú mi. Èmi yóò fi ẹsẹ̀ ilé rẹ̀ múlẹ̀ gbọningbọnin òun yóò sì ṣe òjíṣẹ́ níwájú ẹni òróró mi ní ọjọ́ gbogbo.
Na da gobele salasu dunu afae ilegemu. E da eso huluane Nama molole fa: no bobogemu amola Na hanai huluane hamomu. Na da ema egaga fi imunu. Ilia da Na ilegei hina bagade ema noga: le hawa: hamomu.
36 Nígbà náà olúkúlùkù ẹnikẹ́ni tí ó bá kù ní ìdílé yín, yóò jáde wá yóò sì foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀ nítorí ẹyọ fàdákà àti nítorí èépá àkàrà àti ẹ̀bẹ̀ pé, “Jọ̀wọ́ yàn mí sí ọ̀kan nínú iṣẹ́ àwọn àlùfáà, kí èmi kí ó le máa rí oúnjẹ jẹ.”’”
Amola digaga fi dunu hame bogoi esala, da amo gobele salasu dunuma muni amola ha: i manu edegemusa: masunu. Amola ilia da ha: i manu lama: ne, gobele salasu dunuma fidima: ne, ha: giwane adole ba: mu.

< 1 Samuel 2 >