< 1 Samuel 16 >

1 Olúwa sọ fún Samuẹli pé, “Yóò ha ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò máa dárò Saulu, nígbà tí ó jẹ́ pé mo ti kọ̀ ọ́ ní ọba lórí Israẹli? Rọ òróró kún inú ìwo rẹ, kí o sì mú ọ̀nà rẹ pọ̀n, Èmi rán ọ sí Jese ará Bẹtilẹhẹmu. Èmi ti yan ọ̀kan lára àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ láti jẹ ọba.”
Rəbbee Şamuelik'le eyhen: – Ğu geebne Şaulna haa'as, geedne uts'ur ts'ıts'a'as? Zı mang'usse İzrailyna paççahiyvalla g'avşuna. Gaç q'ışika gyavts'av'u, yəqqı'lqa gixhe. Zı ğu Bet-Lexemğançene Yesseyne k'anyaqa g'ıxele. Zı mang'une dixbışike Yizdemee paççah g'əyxı'.
2 Ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Báwo ni èmi yóò ṣe lọ? Bí Saulu bá gbọ́ nípa rẹ̀, yóò pa mi.” Olúwa wí pé, “Mú abo ẹgbọrọ màlúù kan pẹ̀lú rẹ, kí o sì wí pé, ‘Èmi wá láti wá rú ẹbọ sí Olúwa.’
Şamuelee eyhen: – Zı nəxürna ı'qqəs? Şauluk'le g'ayxhee, zı gik'asda. Rəbbee eyhen: – Vaka sa vuç'e vukkee, «Rəbbis q'urban ablyaa'as arıva» eyhe.
3 Pe Jese wá sí ibi ìrúbọ náà, Èmi yóò sì fi ohun tí ìwọ yóò ṣe hàn ọ́. Ìwọ yóò fi òróró yàn fún mi, ẹni tí èmi bá fihàn ọ́.”
Yesseyir q'urban ablyaa'asde cigeeqa qot'le, qiyğa hucooyiy ha'as ıkkanva Zı vak'le eyhesın. Zı eyhene insanne vuk'lelqa ğu q'ış qadğvas, mang'uke Yizdemee paççah ha'as.
4 Samuẹli ṣe ohun tí Olúwa sọ. Nígbà tí ó dé Bẹtilẹhẹmu, àyà gbogbo àgbàgbà ìlú já, nígbà tí wọ́n pàdé rẹ̀. Wọ́n béèrè pé, “Ṣé àlàáfíà ní ìwọ bá wá?”
Şamuelee Rəbbee eyhəxüd ha'a. Mana Bet-Lexemqa qarımee, şaharın ağsaqqalar mang'une ögilqa qəvəyq'ən-qəvəyq'ən qığeepç'ı, eyhen: – Ğu yugvalisne arı?
5 Samuẹli sì dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni àlàáfíà ni; mo wá láti wá rú ẹbọ sí Olúwa. Ẹ ya ara yín sí mímọ́, kí ẹ sì wá rú ẹbọ pẹ̀lú mi.” Nígbà náà ni ó sì ya Jese sí mímọ́ pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀, ó sì pè wọ́n wá sí ibi ìrúbọ náà.
Mang'vee eyhen: – Ho'o, yugvalis arı. Zı Rəbbis q'urban ablyaa'as arı. Mətteepxha, zakasana q'urban ablyaa'ane cigeeqa able. Şamuelee Yesseyik'leyiy mang'une dixbışik'led mətteepxha q'urban ablyaa'asde cigeeqa ableva eyhe.
6 Nígbà tí wọ́n dé, Samuẹli rí Eliabu, ó rò nínú ara rẹ̀ pé lóòótọ́ ẹni òróró Olúwa dúró níbí níwájú Olúwa.
Manbı vüqqəmee, Şamuel Eliavıqa ilyakkı culed-alqa eyhen: «İna Rəbbee paççah ixhes g'əyxı'na vor!»
7 Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Samuẹli pé, “Má ṣe wo ti ìrísí rẹ̀ tàbí ti gíga rẹ̀, nítorí èmi ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀. Olúwa kì í wo ohun tí ènìyàn máa ń wò. Ènìyàn máa ń wo òde ara ṣùgbọ́n Olúwa máa ń wo ọkàn.”
Rəbbeemee Şamuelik'le inəxüd eyhe: – Mang'une micagiyvaliqayiy axtıvaliqa ilymakka, Zı mana əq'əna qı'ı. Rəbb, insan ilyakkan xhinne deş ilyakka. İnsan insanne aq'vayqa, tanaqa ilyakka, Rəbbmee insanne yik'eeqa ilyakka.
8 Nígbà náà ni Jese pe Abinadabu, ó sì jẹ́ kí ó rìn kọjá ní iwájú Samuẹli. Ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Olúwa kò yan ẹni yìí.”
Mane gahıl Yesseyee Avinadav qort'ul, mana Şamuelyne ögiyle alğayhe. Şamuelee eyhen: – Rəbbee inar g'əyxı' deş.
9 Jese sì jẹ́ kí Ṣamma rìn kọjá ní iwájú Samuẹli, ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Olúwa kò yan ẹni yìí náà.”
Manke Yesseyee Şamma qort'ul, mana alğayhe Şamuelyne ögeençe. Şamuelee eyhen: – Rəbbee inar g'əyxı' deş.
10 Jese jẹ́ kí àwọn ọmọ rẹ̀ méje rìn kọjá ní iwájú Samuẹli ṣùgbọ́n Samuẹli sọ fún un pé, “Olúwa kò yan àwọn wọ̀nyí.”
Yesseyee dixbışda yighırsana qort'ul, manbı Şamuelyne ögiyle alğaa'a. Şamuelee Yesseyk'le eyhen: – Rəbbee inbı g'əvxü deş.
11 Nígbà náà ni ó béèrè lọ́wọ́ Jese pé, “Ṣé èyí ni gbogbo àwọn ọmọ rẹ?” Jese dáhùn pé, “Ó ku àbíkẹ́yìn wọn, ó ń tọ́jú agbo àgùntàn.” Samuẹli sì wí pé, “Rán ìránṣẹ́ lọ pè é wá; àwa kò ní jókòó títí òun yóò fi dé.”
Şamuelee Yesseyke qiyghanan: – İnbı yiğne dixbışin gırgınbıne? Yesseyee eyhen: – Nekke k'ınnar vorna, mang'vee vəq'əbı uxhiyxhan. Şamuelee Yesseyk'le eyhen: – Mang'uqar qihna insan g'axıle, hasre manar inyaqa qoracen. Mana inyaqa qalesmee, şi sufranılqa savaales deş.
12 Ó sì ránṣẹ́ sí i, wọ́n sì mú un wọlé wá, ó jẹ́ ẹni tó mọ́ra, àwọ̀ ara rẹ̀ dùn ún wò, ó jẹ́ arẹwà gidigidi. Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Dìde kí o sì fi òróró yàn án, òun ni ẹni náà.”
Yesseyee mang'uqar qihna insan g'axuvu mana qalya'ana. Mang'uqa ç'ərəxən xhinnen danbı, micagın uleppı, uftanınıd aq'va eyxhe. Rəbbee Şamuelik'le eyhen: – Oza qixhe, mang'ulqa q'ış qadğve, Zı eyhena mana vor.
13 Nígbà náà ni Samuẹli mú ìwo òróró, ó sì ta á sí i ní orí ní iwájú àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀, láti ọjọ́ náà lọ, Ẹ̀mí Mímọ́ Olúwa wá sí orí Dafidi nínú agbára. Samuẹli sì lọ sí Rama.
Şamuelee q'ışnana gaç alyapt'ı, çocaaşine k'ane Davudulqa q'ış qadağva. Manke Rəbbin Rı'h Davudulqa g'eç'e, mane yiğıled mang'ul oğa axva. Şamuel mançe Ramayeeqa siyk'al.
14 Nísinsin yìí, ẹ̀mí Olúwa ti kúrò lára Saulu, ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Olúwa sì ń yọ ọ́ lẹ́nu.
Rəbbin Rı'h Şaulule atk'ınmee, Rəbbee mang'ulqa sa medın pisın rı'h g'ıxele ıxha. Mançinıb Şaulus əq'üba hoole vuxha.
15 Àwọn ìránṣẹ́ Saulu sì wí fún un pé, “Wò ó, ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ń yọ ọ́ lẹ́nu.
Şaulne insanaaşe mang'uk'le eyhen: – Allahee g'axuvuyne pisde rı'hı'n həşde vas əq'üba hoole.
16 Jẹ́ kí olúwa wa pàṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ tí ó wà níhìn-ín láti wa ẹnìkan tí ó lè fi dùùrù kọrin. Yóò sì ṣe é nígbà tí ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run bá bà lé ọ, ìwọ yóò sì sàn.”
Yişda xərna, yiğne insanaaşilqa əmr hee'e, vas yugba lira əlivxəs vəəxəna insan t'abal he'ecen. Allahee g'axuvuyn pisın rı'h valqa qadımee, mang'vee lira əlivxee, vasıd yugda ixhes.
17 Nígbà náà ni Saulu wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Ẹ wá ẹnìkan tí ó lè kọrin dáradára kí ẹ sì mú u wá fún mi.”
Şaulee cune insanaaşik'le eyhen: – Manke yizdemee sa yugba lira ilyviyxəna insan t'abal hı'ı zasqa ayre.
18 Ọ̀kan nínú ìránṣẹ́ náà dáhùn pé, “Èmi ti ri ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Jese ti Bẹtilẹhẹmu tí ó mọ orin kọ, ó jẹ́ alágbára àti ológun. Ó ní ọgbọ́n ọ̀rọ̀ òun sì dára ní wíwò. Olúwa sì wà pẹ̀lú u rẹ̀.”
Mang'une insanaaşine sang'vee alidghıniy qele: – Zak'le Bet-Lexemğançene Yesseyne dixbışde sang'vee yugba lira ilyviyxə g'avcuna. Mana cehil, yik'ekana, yugra siç'ekkvana, k'orara yuşan ha'ana, micagna gadeyiy. Rəbbir mang'ukayiy.
19 Saulu sì rán oníṣẹ́ sí Jese wí pé, “Rán Dafidi ọmọ rẹ sí mi, ẹni tí ó ń ṣọ́ àgùntàn.”
Şaulee, Yesseysqa xabar ana insanar g'axuvu, eyhen: – Vəq'əbı uxhiyxhan ha'ana yiğna dix, Davud, zasqa g'axıle.
20 Jese sì mú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ti a di ẹrù lé àti ìgò ọtí wáìnì àti ọmọ ewúrẹ́; ó sì rán wọn nípa ọwọ́ Dafidi ọmọ rẹ̀ sí Saulu.
Yesseyee əməlelqa gıney, çaxıren tuluğ, mısva alivxhu, cune duxayka Davuduka Şaulus g'uxoole.
21 Dafidi sì tọ Saulu lọ, ó sì dúró níwájú rẹ̀, òun sì fẹ́ ẹ gidigidi, Dafidi sì wá di ọ̀kan nínú àwọn tí ń ru ìhámọ́ra rẹ̀.
Davud Şaulusqa qarı, mang'une ögil ulyoyzar. Şaulus Davud geer ikkiykan, mang'uke cuna silahdar ha'a.
22 Nígbà náà ni Saulu ránṣẹ́ sí Jese pé, “Jẹ́ kí Dafidi dúró níwájú mi, nítorí tí ó wù mí.”
Qiyğa Şaulee, Yesseysqa cuna insan g'axuvu, eyhen: – Hucoona ixhes, hasre Davud yizde k'ane axvecen, mana zasqa yugra qarı.
23 Ó sì ṣe, nígbà tí ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá bá dé sí Saulu, Dafidi a sì fi ọwọ́ rẹ̀ kọrin lára dùùrù: a sì san fún Saulu, ara rẹ̀ a sì dá; ẹ̀mí búburú náà a sì fi sílẹ̀.
Allahee g'axuvuyn pisın rı'h Şaululqa qadıyne gahbışil, Davudee cuna lira alyapt'ı əlivxümee, mana yug qexhe ıxha. Pisın rı'hı'd mang'uke əq'əna qexhe ıxha.

< 1 Samuel 16 >