< 1 Samuel 16 >

1 Olúwa sọ fún Samuẹli pé, “Yóò ha ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò máa dárò Saulu, nígbà tí ó jẹ́ pé mo ti kọ̀ ọ́ ní ọba lórí Israẹli? Rọ òróró kún inú ìwo rẹ, kí o sì mú ọ̀nà rẹ pọ̀n, Èmi rán ọ sí Jese ará Bẹtilẹhẹmu. Èmi ti yan ọ̀kan lára àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ láti jẹ ọba.”
OLELO mai la o Iehova ia Samuela, Pehea la ka loihi o kou uwe ana ia Saula, no ka mea, ua haalele au ia ia, aole oia ke alii maluna o ka Iseraela? E hoopiha oe i kou pepeiaohao i ka aila, a e hele, e hoouna aku au ia oe io Iese la no Betelehema: no ka mea, ua wae iho au i alii no'u iwaena o kana mau keiki.
2 Ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Báwo ni èmi yóò ṣe lọ? Bí Saulu bá gbọ́ nípa rẹ̀, yóò pa mi.” Olúwa wí pé, “Mú abo ẹgbọrọ màlúù kan pẹ̀lú rẹ, kí o sì wí pé, ‘Èmi wá láti wá rú ẹbọ sí Olúwa.’
I aku la o Samuela, Pehea la wau e hele ai? ina lohe o Saula, e pepehi mai ia ia'u. Olelo mai la o Iehova, E lawe pu me oe i bipiwahine, a e i aku, Ua hele mai nei au e kaumaha aku ia Iehova.
3 Pe Jese wá sí ibi ìrúbọ náà, Èmi yóò sì fi ohun tí ìwọ yóò ṣe hàn ọ́. Ìwọ yóò fi òróró yàn fún mi, ẹni tí èmi bá fihàn ọ́.”
A e kahea aku oe ia Iese e hele i ka mohai, a e hoike aku au ia oe i kau mea e hana aku ai: a e poni iho oe no'u i ka mea a'u e olelo aku ai ia oe.
4 Samuẹli ṣe ohun tí Olúwa sọ. Nígbà tí ó dé Bẹtilẹhẹmu, àyà gbogbo àgbàgbà ìlú já, nígbà tí wọ́n pàdé rẹ̀. Wọ́n béèrè pé, “Ṣé àlàáfíà ní ìwọ bá wá?”
A hana aku la o Samuela i ka Iehova i olelo mai ai, a hele aku la i Betelehema: a haalulu na lunakahiko o ke kulanakauhale i kona hiki ana mai, i mai la, I hele mai nei oe me ke aloha?
5 Samuẹli sì dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni àlàáfíà ni; mo wá láti wá rú ẹbọ sí Olúwa. Ẹ ya ara yín sí mímọ́, kí ẹ sì wá rú ẹbọ pẹ̀lú mi.” Nígbà náà ni ó sì ya Jese sí mímọ́ pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀, ó sì pè wọ́n wá sí ibi ìrúbọ náà.
I aku la ia, Me ke aloha no: i hele mai nei au e kaumaha aku ia Iehova; e hoomaemae oukou ia oukou iho, a e hele pu mai me au i ka mohai. Hoomaemae aku la oia ia Iese a me kana mau keiki, a kahea aku la oia ia lakou i ka mohai.
6 Nígbà tí wọ́n dé, Samuẹli rí Eliabu, ó rò nínú ara rẹ̀ pé lóòótọ́ ẹni òróró Olúwa dúró níbí níwájú Olúwa.
A i ko lakou hiki ana mai, nana aku oia ia Eliaba, i iho la, He oiaio imua o'u ka poni a Iehova.
7 Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Samuẹli pé, “Má ṣe wo ti ìrísí rẹ̀ tàbí ti gíga rẹ̀, nítorí èmi ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀. Olúwa kì í wo ohun tí ènìyàn máa ń wò. Ènìyàn máa ń wo òde ara ṣùgbọ́n Olúwa máa ń wo ọkàn.”
A olelo mai la o Iehova ia Samuela, Mai nana oe i kona ano mawaho, aole hoi i ka loihi o kona kino; ua hoole aku au ia ia: no ka mea, aole ma ka mea a ke kanaka i ike; ke nana nei ke kanaka i na helehelena, aka, ke nana nei o Iehova i ka naau.
8 Nígbà náà ni Jese pe Abinadabu, ó sì jẹ́ kí ó rìn kọjá ní iwájú Samuẹli. Ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Olúwa kò yan ẹni yìí.”
A kahea aku la o Iese ia Abinadaba, a hoike ia ia imua o Samuela. I mai la ia, Aole i wae mai o Iehova i keia.
9 Jese sì jẹ́ kí Ṣamma rìn kọjá ní iwájú Samuẹli, ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Olúwa kò yan ẹni yìí náà.”
Hoike aku la o Iese ia Sama. I mai la ia, Aole o Iehova i wae mai i keia.
10 Jese jẹ́ kí àwọn ọmọ rẹ̀ méje rìn kọjá ní iwájú Samuẹli ṣùgbọ́n Samuẹli sọ fún un pé, “Olúwa kò yan àwọn wọ̀nyí.”
Hoike aku la o Iese i kana mau keikikane ehiku imua o Samuela. I mai la o Samuela ia Iese, Aole o Iehova i wae mai ia lakou nei.
11 Nígbà náà ni ó béèrè lọ́wọ́ Jese pé, “Ṣé èyí ni gbogbo àwọn ọmọ rẹ?” Jese dáhùn pé, “Ó ku àbíkẹ́yìn wọn, ó ń tọ́jú agbo àgùntàn.” Samuẹli sì wí pé, “Rán ìránṣẹ́ lọ pè é wá; àwa kò ní jókòó títí òun yóò fi dé.”
Ninau aku la o Samuela ia Iese, O ka pau anei keia o na keiki? I mai la ia, O ka pokii wale no i koe, aia hoi, ke malama nei ia i na hipa. I aku la o Samuela ia Iese, E kii, a lawe mai ia ia: no ka mea, aole kakou e noho iho a hiki mai ia.
12 Ó sì ránṣẹ́ sí i, wọ́n sì mú un wọlé wá, ó jẹ́ ẹni tó mọ́ra, àwọ̀ ara rẹ̀ dùn ún wò, ó jẹ́ arẹwà gidigidi. Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Dìde kí o sì fi òróró yàn án, òun ni ẹni náà.”
Kii aku la ia, a lawe mai ia ia. He ehu, he nani kona mau maka, he maikai ke nana aku. Olelo mai o Iehova, E ku ae oe, a e poni ia ia, no ka mea, oia no ia.
13 Nígbà náà ni Samuẹli mú ìwo òróró, ó sì ta á sí i ní orí ní iwájú àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀, láti ọjọ́ náà lọ, Ẹ̀mí Mímọ́ Olúwa wá sí orí Dafidi nínú agbára. Samuẹli sì lọ sí Rama.
Alaila lalau aku la o Samuela i ka pepeiaohao aila, a poni ia ia iwaena o kona mau hoahanau: a hiki mai la ka Uhane o Iehova maluna o Davida ia la, a ma ia hope aku. Ku ae la o Samuela, a hele aku ma Rama.
14 Nísinsin yìí, ẹ̀mí Olúwa ti kúrò lára Saulu, ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Olúwa sì ń yọ ọ́ lẹ́nu.
A haalele ka Uhane o Iehova ia Saula, a hikilele mai ka uhane ino maluna ona na Iehova mai.
15 Àwọn ìránṣẹ́ Saulu sì wí fún un pé, “Wò ó, ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ń yọ ọ́ lẹ́nu.
I mai la na kauwa a Saula ia ia, Aia hoi, ano ua hiki wawe mai ka uhane ino i ou la na ke Akua mai.
16 Jẹ́ kí olúwa wa pàṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ tí ó wà níhìn-ín láti wa ẹnìkan tí ó lè fi dùùrù kọrin. Yóò sì ṣe é nígbà tí ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run bá bà lé ọ, ìwọ yóò sì sàn.”
Ano, e ko makou haku, e olelo mai i kau mau kauwa imua ou, e imi lakou i kanaka akamai i ka hookani i ka lira: a i hiki mai ka uhane ino maluna ou na ke Akua mai; alaila oia e hookani ai me kona lima, a ola oe.
17 Nígbà náà ni Saulu wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Ẹ wá ẹnìkan tí ó lè kọrin dáradára kí ẹ sì mú u wá fún mi.”
I aku la o Saula i kana mau kauwa, Ano e imi oukou no'u i kanaka akamai i ka hookani, a e lawe mai io'u nei.
18 Ọ̀kan nínú ìránṣẹ́ náà dáhùn pé, “Èmi ti ri ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Jese ti Bẹtilẹhẹmu tí ó mọ orin kọ, ó jẹ́ alágbára àti ológun. Ó ní ọgbọ́n ọ̀rọ̀ òun sì dára ní wíwò. Olúwa sì wà pẹ̀lú u rẹ̀.”
Alaila olelo mai kekahi o na kauwa, i mai la, Aia hoi, ua ike au i kekahi keiki a Iese no Betelehema, ua akamai i ka hookani, a ua koa loa, a he kanaka kaua, a me ke akamai i ka olelo, a he helehelena maikai, a me ia no o Iehova.
19 Saulu sì rán oníṣẹ́ sí Jese wí pé, “Rán Dafidi ọmọ rẹ sí mi, ẹni tí ó ń ṣọ́ àgùntàn.”
Hoouna aku la o Saula i na elele io Iese la, i aku la, E hoouna mai io'u nei ia Davida, i kau keiki, aia no ia me ka poe hipa.
20 Jese sì mú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ti a di ẹrù lé àti ìgò ọtí wáìnì àti ọmọ ewúrẹ́; ó sì rán wọn nípa ọwọ́ Dafidi ọmọ rẹ̀ sí Saulu.
Lawe ae la o Iese i ka hoki, me ka berena, a me ka hue waina, a me kahi keikikao, a hoouna aku la ma ka lima o Davida, kana keiki, io Saula la.
21 Dafidi sì tọ Saulu lọ, ó sì dúró níwájú rẹ̀, òun sì fẹ́ ẹ gidigidi, Dafidi sì wá di ọ̀kan nínú àwọn tí ń ru ìhámọ́ra rẹ̀.
Hele aku la o Davida io Saula la, a ku imua ona: a ua nui kona aloha mai ia ia: a lilo ia i mea halihali i kana mea kaua.
22 Nígbà náà ni Saulu ránṣẹ́ sí Jese pé, “Jẹ́ kí Dafidi dúró níwájú mi, nítorí tí ó wù mí.”
Hoouna aku la o Saula io Iese la, i aku la, Ke noi aku nei au ia oe, e ae mai oe, e ku o Davida imua o'u: no ka mea, ua loaa ia ia ke aloha imua o ko'u maka.
23 Ó sì ṣe, nígbà tí ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá bá dé sí Saulu, Dafidi a sì fi ọwọ́ rẹ̀ kọrin lára dùùrù: a sì san fún Saulu, ara rẹ̀ a sì dá; ẹ̀mí búburú náà a sì fi sílẹ̀.
A i ka manawa i hiki mai ai ka uhane ino maluna o Saula na ke Akua mai, lalau aku la o Davida i ka lira, a hookani aku la me kona lima; a ua oluolu o Saula, a ua ola hoi, a haalele ka uhane ino ia ia.

< 1 Samuel 16 >