< 1 Samuel 15 >
1 Samuẹli wí fún Saulu pé, “Èmi ni Olúwa rán láti fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí àwọn ènìyàn rẹ̀ Israẹli; fetísílẹ̀ láti gbọ́ iṣẹ́ tí Olúwa rán mi sí ọ́.
OLELO aku la o Samuela ia Saula, Na Iehova wau i hoouna mai e poni ia oe i alii maluna o kona poe kanaka, o ka Iseraela: ano hoi, e hoolohe oe i ka leo o na olelo a Iehova.
2 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, ‘Èmi yóò jẹ àwọn Amaleki ní yà fún ohun tí wọ́n ti ṣe sí Israẹli nígbà tí wọn dè wọn lọ́nà nígbà tí wọn ń bọ̀ láti Ejibiti.
Ke olelo mai nei o Iehova o ke kaua, peneia, Ke hoomanao nei au i ka mea a ka Amaleka i hana mai ai i ka Iseraela, i kona ku e mai ia ia ma ke ala, i ka manawa i hele mai ai ia mai Aigupita mai.
3 Lọ nísinsin yìí, kí o sì kọlu Amaleki, kí o sì pa gbogbo ohun tí ó bá jẹ́ tiwọn ní à parun. Má ṣe dá wọn sí, pa ọkùnrin àti obìnrin wọn, ọmọ kékeré àti ọmọ ọmú, màlúù àti àgùntàn, ìbákasẹ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn.’”
Ano hoi e hele oe, a e luku aku i ka Ameleka, a e luku aku i ko lakou mea a pau loa, mai minamina ia lakou; aka, e luku aku i ke kane a me ka wahine, i ke keiki a me ka mea omo waiu, i ka bipi a me ka hipa, i ke kamelo a me ka hoki.
4 Bẹ́ẹ̀ ni Saulu kó àwọn ènìyàn jọ, ó sì ka iye wọn ní Talaemu, wọ́n sì jẹ́ ogún ọ̀kẹ́ àwọn ológun ẹlẹ́ṣẹ̀, pẹ̀lú ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá àwọn ọkùnrin Juda.
Houluulu ae la o Saula i na kanaka, a helu aku la ia lakou ma Telaima, elua haneri tausani kanaka koa hele wawae, a he umi tausani kanaka o ka Iuda.
5 Saulu sì lọ sí ìlú Amaleki ó sì gọ dè wọ́n ní àfonífojì kan.
A hele aku la o Saula i ke kulanakauhale o ka Amaleka, a kaua aku la ma ke awawa.
6 Nígbà náà ni ó wí fún àwọn ará Keni pé, “Ẹ lọ, kúrò ní Amaleki kí èmi má ba à run yín pẹ̀lú wọn; nítorí ẹ̀yin fi àánú hàn fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli nígbà tí wọ́n gòkè ti Ejibiti wá.” Bẹ́ẹ̀ ni àwọn Kenaiti lọ kúrò láàrín àwọn Amaleki.
Olelo aku la o Saula i ka poe Keni, E hele aku, e haalele, e iho ilalo mai waena mai o ka Amaleka, o luku aku auanei au ia oukou me lakou: no ka mea, ua lokomaikai oukou i na mamo a Iseraela, ia lakou i hele mai, mai Aigupita mai. Hele aku la ka poe Keni mailoko aku o ka Amaleka.
7 Nígbà náà ni Saulu kọlu àwọn Amaleki láti Hafila dé Ṣuri, tí ó fi dé ìlà-oòrùn Ejibiti.
Luku aku la o Saula i ka Amaleka ma Havila, a hiki aku i Sura e ku pono ana i Aigupita.
8 Ó sì mú Agagi ọba Amaleki láààyè, ó sì fi idà rẹ̀ kọlù gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀.
A lawe ola aku la oia ia Agaga ke alii o ka Amaleka, a luku aku la i na kanaka a pau i ka maka o ka pahikaua.
9 Ṣùgbọ́n Saulu àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ dá Agagi sí àti èyí tí ó dára jùlọ nínú àgùntàn àti màlúù àti ọ̀dọ́-àgùntàn àbọ́pa àti gbogbo nǹkan tó dára. Wọ́n kò sì fẹ́ pa àwọn wọ̀nyí run pátápátá ṣùgbọ́n gbogbo nǹkan tí kò dára tí kò sì níláárí ni wọ́n parun pátápátá.
Aka, o Saula a me na kanaka i hoola aku la ia Agaga, a i na mea maikai o ka poe hipa, a o ka poe bipi, a i na mea maikai iki iho, a i na keiki hipa, a i na mea maikai a pau, aole i luku aku ia lakou: aka, o na mea i hoowahawahaia, a me na mea ino, ua pau loa ia mea i ka lukuia e lakou.
10 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Samuẹli wá pé,
Alaila hiki mai ka olelo a Iehova ia Samuela, i mai la,
11 “Èmi káàánú gidigidi pé mo fi Saulu jẹ ọba, nítorí pé ó ti yípadà kúrò lẹ́yìn mi, kò sì pa ọ̀rọ̀ mi mọ́.” Inú Samuẹli sì bàjẹ́ gidigidi, ó sì ké pe Olúwa ní gbogbo òru náà.
Ke mihi nei au i kuu hoonoho ana ia Saula i alii: no ka mea, ua huli ae ia mai ka hahai ana ia'u, aole ia i hooko i ka'u mau kauoha. Huhu iho la o Samuela; a kahea aku la ia ia Iehova ia po a pau.
12 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù Samuẹli sì dìde láti lọ pàdé Saulu, ṣùgbọ́n wọ́n sọ fún un pé, “Saulu ti wá sí Karmeli. Ó ti kọ́ ibìkan fún ara rẹ̀ níbẹ̀, ó sì ti yípadà, ó sì ti sọ̀kalẹ̀ lọ sí Gilgali.”
I ka wanaao, ala ae la o Samuela e halawai me Saula i kakahiaka, ua haiia mai ia Samuela, i mai la, Ua hiki mai o Saula ma Karemela, a ua kukulu i mea hoomanao nona, a ua huli ae, a ua hele aku, a ua iho ilalo i Gilegala.
13 Nígbà tí Samuẹli sì dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, Saulu sì wí fún un pé, “Olúwa bùkún fún ọ, mo ti ṣe ohun tí Olúwa pàṣẹ.”
A hele aku la o Samuela io Saula la; i mai la o Saula ia ia, Pomaikai oe ia Iehova; ua hooko no wau i ka olelo a Iehova.
14 Ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Èwo wá ni igbe àgùntàn tí mo ń gbọ́ ní etí mi? Kí ni igbe màlúù ti mo ń gbọ́ yìí?”
I aku la o Samuela, No ke aha keia alala ana o na hipa ma kuu pepeiao, a me ka uwo ana o na bipi a'u e lohe nei?
15 Saulu sì dáhùn pé, “Àwọn ọmọ-ogun ní o mú wọn láti Amaleki wá, wọ́n dá àwọn àgùntàn, àti màlúù tí ó dára jùlọ sí láti fi rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ, ṣùgbọ́n a pa àwọn tókù run pátápátá.”
I mai la o Saula, Ua lawe mai lakou ia mau mea mai ka Amaleka mai: no ka mea, ua hoola na kanaka i na mea maikai o ka poe hipa, a me na bipi, i mea e kaumaha aku ai ia Iehova, i kou Akua; a o na mea e ae, ua pau ia makou i ka lukuia.
16 Samuẹli sí wí fún Saulu pé, “Dákẹ́ ná, jẹ́ kí èmi kí ó sọ ohun tí Olúwa wí fún mi ní alẹ́ àná fún ọ.” Saulu sì wí pé, “Sọ fún mi.”
Olelo aku la o Samuela ia Saula, Alia, a e hai aku au ia oe i ka mea a Iehova i olelo mai ai ia'u i neia po. I mai la kela ia ia, E hai mai.
17 Samuẹli sì wí pé, “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ fi ìgbà kan kéré lójú ara rẹ, ǹjẹ́ ìwọ kò ha di olórí ẹ̀yà Israẹli? Olúwa fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli.
I aku la o Samuela, I ka wa i uuku ai oe i kou maka, aole anei i lilo oe i luna no na ohana o ka Iseraela, a i poni mai hoi o Iehova ia oe i alii maluna o ka Iseraela?
18 Olúwa sì rán ọ níṣẹ́ wí pé, ‘Lọ, kí o sì pa àwọn ènìyàn búburú ará Amaleki run pátápátá; gbóguntì wọ́n títí ìwọ yóò fi run wọ́n.’
Hoouna aku la o Iehova ia oe ma ke ala, i aku la, E hele, a e luku loa aku i ka poe hewa o ka Amaleka, a e kaua aku ia lakou, a pau lakou i ka lukuia.
19 Èéṣe tí ìwọ kò fi gbọ́ ti Olúwa? Èéṣe tí ìwọ fi sáré sí ìkógun tí o sì ṣe búburú níwájú Olúwa?”
No ke aha la oe i hoolohe ole ai i ka leo o Iehova, a ua lawe hewa oe i ka waiwai pio, a ua hana hewa oe imua o Iehova.
20 Saulu sì wí fún Samuẹli pé, “Ṣùgbọ́n èmi ti ṣe ìgbọ́ràn sí Olúwa, èmi sì ti lọ ní ọ̀nà tí Olúwa rán mi. Mo sì ti pa àwọn ará Amaleki run pátápátá, mo sì ti mú Agagi ọba wọn padà wá.
I mai la o Saula ia Samuela, Ua hoolohe no wau i ka leo o Iehova, a ua hele au ma ke ala a Iehova i hoouna aku ai ia'u, a ua lawe mai au ia Agaga, i ke alii o ka Amaleka, a ua luku loa aku au i ka Amaleka.
21 Àwọn ọmọ-ogun ti mú àgùntàn àti màlúù lára ìkógun èyí tí ó dára láti fi fún Olúwa láti fi rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ ní Gilgali.”
Aka, ua lawe na kanaka i ka waiwai pio, i ka hipa, a me ka bipi, i na mea maikai o na mea laa, i mea e kaumaha aku ai ia Iehova i kou Akua ma Gilegala.
22 Ṣùgbọ́n Samuẹli dáhùn pé, “Olúwa ha ní inú dídùn sí ẹbọ sísun àti ẹbọ ju kí a gba ohùn Olúwa gbọ́? Ìgbọ́ràn sàn ju ẹbọ lọ, ìfetísílẹ̀ sì sàn ju ọ̀rá àgbò lọ.
I aku la o Samuela, Ua like anei ka oluolu o Iehova i na mohaikuni, a i na alana, me ka hoolohe ana i ka leo o Iehova? Aia hoi, ua oi aku ka pono o ka hoolohe ana, mamua o ka mohai, a o ka maliu ana, mamua o ka momona o na hipakane.
23 Nítorí pé ìṣọ̀tẹ̀ dàbí ẹ̀ṣẹ̀ àfọ̀ṣẹ, àti ìgbéraga bí ẹ̀ṣẹ̀ ìbọ̀rìṣà. Nítorí tí ìwọ ti kọ ọ̀rọ̀ Olúwa, Òun sì ti kọ̀ ọ́ ní ọba.”
No ka mea, o ke kipi, ua like ia me ka hewa o ka anaana, a o ka hoopaakiki, me ka lapuwale o ka hoomanakii: no kou haalele ana i ka olelo a Iehova, ua haalele mai ia ia oe, aole oe ke alii.
24 Nígbà náà ni Saulu wí fún Samuẹli pé, “Èmi ti ṣẹ̀. Mo ti rú òfin Olúwa àti ọ̀rọ̀ rẹ̀. Èmi sì bẹ̀rù àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀ ni èmi sì gba ohùn wọn gbọ́.
I mai la o Saula ia Samuela, Ua hewa au; no ka mea, ua malama ole au i ke kauoha a Iehova, a me kau mau olelo, no kuu makau ana i na kanaka, a ua hoolohe au i ko lakou leo.
25 Mo bẹ̀ ọ́ nísinsin yìí, dárí ẹ̀ṣẹ̀ mi jì, kí ó sì yípadà pẹ̀lú mi, kí èmi kí ó lè sin Olúwa.”
Ano hoi, ke noi aku nei au ia oe, e kala mai oe i kuu hewa, a e huli ae me au, a e hoomana aku ia Iehova.
26 Ṣùgbọ́n Samuẹli wí fún un pé, “Èmi kò ní bá ọ padà. Ìwọ ti kọ ọ̀rọ̀ Olúwa sílẹ̀, Olúwa sì ti kọ̀ ọ́ ní ọba lórí Israẹli!”
I aku la o Samuela ia Saula, Aole au e huli ae me oe; no ka mea, ua haalele oe i ke kauoha a Iehova, a ua haalele mai o Iehova ia oe, aole oe ke alii maluna o ka Iseraela.
27 Bí Samuẹli sì ti fẹ́ yípadà láti lọ, Saulu sì di ẹ̀wù ìlekè rẹ̀ mú, ó sì fàya;
A i ka huli ana ae o Samuela e hele aku, lalau mai la kela i ka lepa o kona aahu, a nahae iho la ia.
28 Samuẹli sì wí fún un pé, “Olúwa ti fa ìjọba Israẹli ya kúrò lọ́wọ́ ọ̀ rẹ lónìí, ó sì ti fi fún aládùúgbò rẹ kan tí ó sàn jù ọ́ lọ.
I aku la o Samuela ia ia, Ua hoonahae mai o Iehova i ke aupuni mai ou aku la i keia la, a ua haawi aku ia mea i kekahi hoalauna ou, ua oi aku kona pono i kou.
29 Ẹni tí ó ń ṣe ògo Israẹli, kì í purọ́, bẹ́ẹ̀ ni kì í yí ọkàn rẹ̀ padà; nítorí kì í ṣe ènìyàn tí yóò yí ọkàn rẹ̀ padà.”
Aole no hoi e hoopunipuni ka Oiaio o ka Iseraela, aole hoi ia e mihi; no ka mea, aole no ia he kanaka, i mihi ai oia.
30 Saulu sì wí pé, “Èmi ti ṣẹ̀, ṣùgbọ́n jọ̀wọ́ bu ọlá fún mi níwájú àwọn àgbàgbà ènìyàn mi, àti níwájú u Israẹli, yípadà pẹ̀lú mi, kí èmi kí ó lè tẹríba fún Olúwa Ọlọ́run rẹ.”
I mai la ia, Ua hewa au; ke noi aku nei au ia oe, ano e hoomaikai mai oe ia'u imua o na lunakahiko o kuu poe kanaka, a imua hoi o ka Iseraela, a e huli hou ae me au, i hoomana aku ai au ia Iehova i kou Akua.
31 Bẹ́ẹ̀ ni Samuẹli sì yípadà pẹ̀lú Saulu, Saulu sì sin Olúwa.
A huli hou ae la o Samuela mahope o Saula, a hoomana aku la o Saula ia Iehova.
32 Nígbà náà ni Samuẹli wí pé, “Mú Agagi ọba àwọn ará Amaleki wá fún mi.” Agagi sì tọ̀ ọ́ wá ní ìgboyà pẹ̀lú èrò pé, “Nítòótọ́ ìkorò ikú ti kọjá.”
Alaila, i aku la o Samuela, E kaina mai o Agaga, ke alii o ka Amaleka i o'u nei: a hele olioli mai o Agaga, i mai la, He oiaio, ua hala aku la ka awaawa o ka make.
33 Ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Bí idà rẹ ti sọ àwọn obìnrin di aláìní ọmọ bẹ́ẹ̀ ni ìyá rẹ yóò sì di aláìní ọmọ láàrín obìnrin.” Samuẹli sì pa Agagi níwájú Olúwa ni Gilgali.
I aku la o Samuela, E like me kau pahikaua i hoonele ai i na wahine i keiki ole, pela hoi e hooneleia'i kou makuwahine i ke keiki ole iwaena o na wahine. Oki liilii iho la o Samuela ia Agaga imua o Iehova ma Gilegala.
34 Nígbà náà ni Samuẹli lọ sí Rama, Saulu sì gòkè lọ sí ilé e rẹ̀ ní Gibeah tí Saulu.
A hele aku la o Samuela ma Rama; a pii ae la o Saula i kona hale ma Gibea o Saula.
35 Samuẹli kò sì padà wá mọ́ láti wo Saulu títí ó fi di ọjọ́ ikú u rẹ̀, ṣùgbọ́n Samuẹli káàánú fún Saulu. Ó sì dun Olúwa pé ó fi Saulu jẹ ọba lórí Israẹli.
Aole hele hou o Samuela e ike ia Saula, a hiki i kona la e make ai; aka, uwe iho la o Samuela ia Saula: a mihi iho la o Iehova i kona hooalii ana ia Saula maluna o ka Iseraela.