< 1 Peter 5 >

1 Àwọn alàgbà tí ń bẹ láàrín yín ni mo gbànímọ̀ràn, èmi ẹni tí ń ṣe alàgbà bí ẹ̀yin, àti ẹlẹ́rìí ìyà Kristi, àti alábápín nínú ògo tí a ó fihàn.
کھْرِیشْٹَسْیَ کْلیشاناں ساکْشِی پْرَکاشِشْیَمانَسْیَ پْرَتاپَسْیاںشِی پْراچِینَشْچاہَں یُشْماکَں پْراچِینانْ وِنِیییدَں وَدامِ۔
2 Ẹ máa tọ́jú agbo Ọlọ́run tí ń bẹ láàrín yín, ẹ máa bojútó o, kì í ṣe àfipáṣe, bí kò ṣe tìfẹ́tìfẹ́; kó má sì jẹ́ fún èrè ìjẹkújẹ, bí kò ṣe pẹ̀lú ìpinnu tí ó múra tan.
یُشْماکَں مَدھْیَوَرْتِّی یَ اِیشْوَرَسْیَ میشَورِنْدو یُویَں تَں پالَیَتَ تَسْیَ وِیکْشَنَں کُرُتَ چَ، آوَشْیَکَتْوینَ نَہِ کِنْتُ سْویچّھاتو نَ وَ کُلوبھینَ کِنْتْوِچّھُکَمَنَسا۔
3 Bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe bí ẹni tí ń lo agbára lórí ìjọ, ṣùgbọ́n kí ẹ ṣe ara yín ní àpẹẹrẹ fún agbo.
اَپَرَمْ اَںشانامْ اَدھِکارِنَ اِوَ نَ پْرَبھَوَتَ کِنْتُ ورِنْدَسْیَ درِشْٹانْتَسْوَرُوپا بھَوَتَ۔
4 Nígbà tí Olórí Olùṣọ́-àgùntàn bá sì fi ara hàn, ẹ̀yin ó gba adé ògo ti kì í sá.
تینَ پْرَدھانَپالَکَ اُپَسْتھِتے یُویَمْ اَمْلانَں گَورَوَکِرِیٹَں لَپْسْیَدھْوے۔
5 Bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú, ẹ̀yin ọ̀dọ́, ẹ tẹríba fún àwọn alàgbà. Àní, gbogbo yín ẹ máa tẹríba fún ara yín kí ẹ fi ìrẹ̀lẹ̀ wọ ara yín ní aṣọ: nítorí, “Ọlọ́run kọ ojú ìjà sí àwọn agbéraga, ṣùgbọ́n ó ń fi oore-ọ̀fẹ́ fún àwọn onírẹ̀lẹ̀.”
ہے یُوانَح، یُویَمَپِ پْراچِینَلوکاناں وَشْیا بھَوَتَ سَرْوّے چَ سَرْوّیشاں وَشِیبھُویَ نَمْرَتابھَرَنینَ بھُوشِتا بھَوَتَ، یَتَح،آتْمابھِمانِلوکاناں وِپَکْشو بھَوَتِیشْوَرَح۔ کِنْتُ تینَیوَ نَمْریبھْیَح پْرَسادادْ دِییَتے وَرَح۔
6 Nítorí náà, ẹ rẹ ara yin sílẹ̀ lábẹ́ ọwọ́ agbára Ọlọ́run, kí òun lè gbe yín ga lákokò.
اَتو یُویَمْ اِیشْوَرَسْیَ بَلَوَتْکَرَسْیادھو نَمْرِیبھُویَ تِشْٹھَتَ تینَ سَ اُچِتَسَمَیے یُشْمانْ اُچِّیکَرِشْیَتِ۔
7 Ẹ máa kó gbogbo àníyàn yín lé e; nítorí tí òun ń ṣe ìtọ́jú yín.
یُویَں سَرْوَّچِنْتاں تَسْمِنْ نِکْشِپَتَ یَتَح سَ یُشْمانْ پْرَتِ چِنْتَیَتِ۔
8 Ẹ máa wà ni àìrékọjá, ẹ máa ṣọ́ra; nítorí èṣù ọ̀tá yín, bí i kìnnìún tí ń ké ramúramù, ó ń rìn káàkiri, ó ń wa ẹni tí yóò pajẹ.
یُویَں پْرَبُدّھا جاگْرَتَشْچَ تِشْٹھَتَ یَتو یُشْماکَں پْرَتِوادِی یَح شَیَتانَح سَ گَرْجَّنَکارِی سِںہَ اِوَ پَرْیَّٹَنْ کَں گْرَسِشْیامِیتِ مرِگَیَتے،
9 Ẹ kọ ojú ìjà sí i pẹ̀lú ìdúró ṣinṣin nínú ìgbàgbọ́, bí ẹ̀yin ti mọ̀ pé ìyà kan náà ni àwọn ará yín tí ń bẹ nínú ayé ń jẹ.
اَتو وِشْواسے سُسْتھِراسْتِشْٹھَنْتَسْتینَ سارْدّھَں یُدھْیَتَ، یُشْماکَں جَگَنِّواسِبھْراترِشْوَپِ تادرِشاح کْلیشا وَرْتَّنْتَ اِتِ جانِیتَ۔
10 Ọlọ́run oore-ọ̀fẹ́ gbogbo, tí ó ti pè yín sínú ògo rẹ̀ tí kò nípẹ̀kun nínú Kristi Jesu, nígbà tí ẹ̀yin bá ti jìyà díẹ̀, òun tìkára rẹ̀, yóò sì ṣe yín ní àṣepé, yóò fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀, yóò fún yín lágbára, yóò fi ìdí yín kalẹ̀. (aiōnios g166)
کْشَنِکَدُحکھَبھوگاتْ پَرَمْ اَسْمَبھْیَں کھْرِیشْٹینَ یِیشُنا سْوَکِییانَنْتَگَورَوَدانارْتھَں یوسْمانْ آہُوتَوانْ سَ سَرْوّانُگْراہِیشْوَرَح سْوَیَں یُشْمانْ سِدّھانْ سْتھِرانْ سَبَلانْ نِشْچَلاںشْچَ کَروتُ۔ (aiōnios g166)
11 Tìrẹ ni ògo àti agbára títí láé. Àmín. (aiōn g165)
تَسْیَ گَورَوَں پَراکْرَمَشْچانَنْتَکالَں یاوَدْ بھُویاتْ۔ آمینْ۔ (aiōn g165)
12 Nítorí Sila, arákùnrin wa olóòtítọ́ gẹ́gẹ́ bí mo ti kà á sí, ni mo kọ̀wé kúkúrú sí i yín, tí mo ń gbà yín níyànjú, tí mo sì ń jẹ́rìí pé, èyí ni òtítọ́ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run: ẹ dúró ṣinṣin nínú rẹ̀.
یَح سِلْوانو (مَنْیے) یُشْماکَں وِشْواسْیو بھْراتا بھَوَتِ تَدْواراہَں سَںکْشیپینَ لِکھِتْوا یُشْمانْ وِنِیتَوانْ یُویَنْچَ یَسْمِنْ اَدھِتِشْٹھَتھَ سَ ایویشْوَرَسْیَ سَتْیو نُگْرَہَ اِتِ پْرَمانَں دَتَّوانْ۔
13 Ìjọ tí ń bẹ ní Babeli, tí a yàn, pẹ̀lú kí yín, bẹ́ẹ̀ sì ni Marku ọmọ mi pẹ̀lú.
یُشْمابھِح سَہابھِرُچِتا یا سَمِتِ رْبابِلِ وِدْیَتے سا مَمَ پُتْرو مارْکَشْچَ یُشْمانْ نَمَسْکارَں ویدَیَتِ۔
14 Ẹ fi ìfẹ́nukonu ìfẹ́ kí ara, yín. Àlàáfíà fún gbogbo yín tí ẹ wà nínú Kristi.
یُویَں پْریمَچُمْبَنینَ پَرَسْپَرَں نَمَسْکُرُتَ۔ یِیشُکھْرِیشْٹاشْرِتاناں یُشْماکَں سَرْوّیشاں شانْتِ رْبھُویاتْ۔ آمینْ۔

< 1 Peter 5 >