< 1 Peter 4 >

1 Ǹjẹ́ bí Kristi ti jìyà fún wa nípa ti ará, irú kan náà ni kí ẹ̀yin fi hámọ́ra; nítorí ẹni tí ó bá ti jìyà nípa ti ara, ó ti bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀.
Nantele amwene O Kilisti ayembele nubele, hwikwatizi eshi zijilo zyazili nanshizila. Zyayembele ashilile obele ayepene ne mbibhi.
2 Kí ẹ̀yin má ṣe fi ìgbà ayé yín ìyókù wà nínú ara mọ́ sí ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ènìyàn bí kò ṣe sí ìfẹ́ Ọlọ́run.
Omtu ono sagahwedelela nantele olwizyo nenyonyo ezyebele, shasongwelwe Ongolobhe, husiku zyakwe zyazisangeye.
3 Nítorí ìgbà tí ó ti kọjá ti tó fún ṣíṣe ìfẹ́ àwọn aláìkọlà, rínrìn nínú ìwà wọ̀bìà, ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́, ọtí àmupara, ìréde òru, kíkó ẹ̀gbẹ́ ọ̀mùtí, àti ìbọ̀rìṣà tí í ṣe ohun ìríra.
zyazibhalile ziyiye hulenganye embombo zyasaga bhaputa bhahaza abhombe embibhi, nebibhi omweezi, olyavi eshikulukulu eshabha sebhaputa nezwa huzimu zyuzivisya.
4 Èyí tí ó yà wọ́n lẹ́nu pé ẹ̀yin kò ba wọn súré sínú irú àṣejù ìwà wọ̀bìà wọ́n, tí wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ yín ní búburú.
Bhasebha eje pamhwoyefwa abhombe embombo ne pamo nabho enya bhayanga amabhibhi huli mwe.
5 Àwọn ẹni tí yóò jíyìn fún ẹni tí ó ti múra láti ṣe ìdájọ́ alààyè àti òkú.
Bhafumye ebazye hwamwene yalihani alonje bhabhali bhomi na bhafwe.
6 Nítorí èyí ní a sá ṣe wàásù ìyìnrere fún àwọn òkú, kí a lè ṣe ìdájọ́ wọn gẹ́gẹ́ bí ènìyàn nípa ti ara, ṣùgbọ́n kí wọ́n lè wà láààyè si Ọlọ́run nípa tí Ẹ̀mí.
Huje endombelo zyaga ngwilwe nabhene bhabhafwye hata nkashile bhali bhalongwilwe alongane nombele gwabho noshi abhatu aje bhawezye akhale alingane no Ngolobhi no mpepo.
7 Ṣùgbọ́n òpin ohun gbogbo kù sí dẹ̀dẹ̀; nítorí náà kí ẹ̀yin wà ní àìrékọjá, kí ẹ sì máa ṣọ́ra nínú àdúrà.
Humalezwo owembombo zyoti uhwenza, nantele mubhanje nenjele zyazili shiza, nantele mubhanje nahatu ahiza hahali neshiputo shenyu.
8 Ju gbogbo rẹ̀ lọ, ẹ ní ìfẹ́ tí ó gbóná láàrín ara yín, nítorí ìfẹ́ ni ń bo ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀ṣẹ̀ mọ́lẹ̀.
Sazisele anongwa zyoti mubhe nadigane hulugano oolwa Mtuomo alenganeje olugano saluhwaza akwikule amabhibhi agabhanje.
9 Ẹ máa ṣe ara yín ni àlejò láìsí ìkùnsínú.
Lanji opezi hwamtu omo nantele muganje anungunishe.
10 Bí olúkúlùkù ti rí ẹ̀bùn gbà, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ máa ṣe ìpín fún ni rẹ̀ láàrín ara yín, bí ìríjú rere tí onírúurú oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.
Nashi omo owenyo shahambilile eshi paji, itumilinashahwavwane nashi abhemelezi abhiza ashipaji eshinji zyazifumile wene no Ngolobhi.
11 Bí ẹnikẹ́ni ba ń sọ̀rọ̀, kí o máa sọ bí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, bí ẹnikẹ́ni bá ń ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́, kí ó ṣe é bí agbára tí Ọlọ́run fi fún un, kí a lè máa yin Ọlọ́run lógo ní ohun gbogbo nípa Jesu Kristi, ẹni tí ògo àti ìjọba wà fún láé àti láéláé. Àmín. (aiōn g165)
Nashi omtu nkagavwe ebhanje nashi enguvu zya pehwilwa no Ngolobhi, eshi humbombo zyoti Ongolobhi ayande ahwiozvye ashelele oYesu Kilisti otutumu ne nguvu zili na mwene wila wila. Amina (aiōn g165)
12 Olùfẹ́, ẹ má ṣe ka ìdánwò gbígbóná ti ń bẹ láàrín yín láti dán yín wò bi ẹni pé ohun àjèjì ni ó dé bá yín.
Mwaganwi muganjebhazye endengo zyasaga obhalenjele nashi ahatu aeshijenyi hahtumilanga hafumila hulimwi.
13 Ṣùgbọ́n níwọ̀n bí ẹ̀yin tí jẹ́ alábápín ìyà Kristi, ẹ máa yọ̀, kí ẹ̀yin lè yọ ayọ̀ púpọ̀ nígbà tí a bá fi ògo rẹ̀ hàn.
Nantele kadili shammanya apate ahwele we humayemba gakilisti. Songwaji shisangwaji nantele owigule owa otutumu wakwe.
14 Bí a bá gàn yín nítorí orúkọ Kristi, ẹni ìbùkún ni yín: nítorí Ẹ̀mí Ògo àti ti Ọlọ́run bà lé yín.
Nkashememli gwilwe hitawa lwa Kilisti, osailwe hulengane no mpepo awangolobhi akhaka pamwanya palimwe.
15 Ṣùgbọ́n ẹ má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni nínú yín jìyà bí apànìyàn, tàbí bí olè, tàbí bí olùṣe búburú, tàbí bí ẹni tí ń tojú bọ̀ ọ̀ràn ẹlòmíràn.
Nantele agajibhe wawonti yayemba nashi obudi, omwibhayabhomba embimbi nantele ahwibhovye nembombo ezaabhaje.
16 Ṣùgbọ́n bí ó bá jìyà bí Kristiani kí ojú má ṣe tì í, ṣùgbọ́n kí ó kúkú yin Ọlọ́run lógo nítorí ti o orúkọ yìí.
Nantele nkashele amtu ayemba nashi Okilisti, ganje lole esoni nantele tutumele Ongolobhi hwitawa elyo.
17 Nítorí ti ìgbà náà dé, tí ìdájọ́ yóò bẹ̀rẹ̀ láti ilé Ọlọ́run wá, bí ó bá sì tètè tí ọ̀dọ̀ wa bẹ̀rẹ̀, ìgbẹ̀yìn àwọn tí kò gba ìyìnrere Ọlọ́run yó ha ti rí?
Nantele esiku zifishile hulongwe ahwandile mungumba eyaNgolobhi. Nkashele ehwandila hulitii ehwandila hulitii ehaibhawe hwabhala bha sebhahwogopa idombelelo zwa Ngolobhi?
18 “Bí ó bá ṣe pé agbára káká ni a fi gba olódodo là, níbo ni aláìwà-bí-Ọlọ́run àti ẹlẹ́ṣẹ̀ yóò yọjú sí?”
Nkashe huwali afwolwa ashilile amamkhame shaibhawele hwantu waswe wilwoliowe mbibhi?”
19 Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí àwọn tí ń jìyà gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Ọlọ́run ni ṣíṣe rere, fi ọkàn wọn lè Ẹlẹ́dàá olóòtítọ́ lọ́wọ́.
Bhonti bhaghayemba afumilane no Ngolobhi khabhishe omoyo gobho hwa bhombi omwiza ohubhabho mbanje amiza.

< 1 Peter 4 >