< 1 Kings 22 >

1 Fún ọdún mẹ́ta kò sì sí ogun láàrín Aramu àti Israẹli.
Saning thumto thung Syria hoi Israel misa angtukhaih om ai.
2 Ṣùgbọ́n ní ọdún kẹta, Jehoṣafati ọba Juda sọ̀kalẹ̀ lọ láti rí ọba Israẹli.
Toe saning thumto haih naah Judah siangpahrang Jehosaphat loe Israel siangpahrang khaeah caeh.
3 Ọba Israẹli sì ti wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Ǹjẹ́ ẹ̀yin mọ̀ pé ti wa ni Ramoti Gileadi, àwa sì dákẹ́ síbẹ̀, a kò sì gbà á padà lọ́wọ́ ọba Aramu?”
Israel siangpahrang mah a tamnanawk khaeah, Gilead prae ih Ramoth vangpui loe aicae ih prae ah ni oh, tiah na panoek o ai maw? Tipongah Syria siangpahrang ban thung hoiah la let ai ah a oh o duem loe? tiah a naa.
4 Ó sì béèrè lọ́wọ́ Jehoṣafati pé, “Ṣé ìwọ yóò bá mi lọ láti lọ bá Ramoti Gileadi jà?” Jehoṣafati sì dá ọba Israẹli lóhùn pé, “Èmi bí ìwọ, ènìyàn mi bí ènìyàn rẹ, ẹṣin mi bí ẹṣin rẹ.”
To pongah Jehosaphat khaeah, Gilead prae ih Ramoth vangpui tuk hanah nang bomh han maw? tiah a naa. Jehosaphat mah Israel siangpahrang khaeah, Kai doeh nang baktiah ni ka oh; kai ih kaminawk doeh nang ih kaminawk baktiah ni oh o, kai ih hrangnawk doeh nang ih hrang baktiah ni oh, tiah a naa.
5 Ṣùgbọ́n Jehoṣafati sì tún wí fún ọba Israẹli pé, “Kọ́kọ́ béèrè lọ́wọ́ Olúwa.”
Toe Jehosaphat mah Israel siangpahrang khaeah, Angraeng khaeah lokdueng hmaloe ah, tiah a naa.
6 Nígbà náà ni ọba Israẹli kó àwọn wòlíì jọ, bí irinwó ọkùnrin. Ó sì béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Ṣé kí n lọ sí Ramoti Gileadi lọ jagun, tàbí kí èmi kí ó jọ̀wọ́ rẹ̀?” Wọ́n sì dáhùn pé, “Lọ, nítorí tí Olúwa yóò fi lé ọba lọ́wọ́.”
To pongah Israel siangpahrang mah, cumvai palito tahmaanawk to ahmuen maeto ah pakhueng moe, nihcae khaeah, Ramoth Gilead tuk hanah ka caeh han maw? To tih ai boeh loe ka oh duem han? tiah lok a dueng. Nihcae mah, Caeh ah, Angraeng mah siangpahrang ban ah na paek tih hmang, tiah a naa o.
7 Ṣùgbọ́n Jehoṣafati béèrè pé, “Ǹjẹ́ wòlíì Olúwa kan kò sí níhìn-ín, tí àwa ìbá béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?”
Toe Jehosaphat mah, Lokdueng hanah Angraeng ih tahmaa maeto doeh hae ah om ai maw? tiah a naa.
8 Ọba Israẹli dá Jehoṣafati lóhùn pé, “Ọkùnrin kan ṣì wà, lọ́dọ̀ ẹni tí àwa lè béèrè lọ́wọ́ Olúwa, ṣùgbọ́n mo kórìíra rẹ̀ nítorí kì í sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere kan nípa mi, bí kò ṣe ibi. Mikaiah ọmọ Imla ni.” Jehoṣafati sì wí pé, “Kí ọba má ṣe sọ bẹ́ẹ̀.”
Israel siangpahrang mah Jehosaphat khaeah, Angraeng khae lokdueng hanah kami maeto oh vop; toe anih loe ka hoih kai ih akawng to thui vai ai; kasae khue ni a thuih, to pongah anih to ka hnukma; anih loe Imlah capa Mikaiah, tiah a naa. Jehosaphat mah, Siangpahrang loe to tiah lok apaeh han om ai, tiah a naa.
9 Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli sì pe ìránṣẹ́ kan, ó sì wí pé, “Lọ yára mú Mikaiah, ọmọ Imla wá.”
To pongah Israel siangpahrang mah angmah ih angraeng maeto kawk moe, Imlah capa Mikaiah to karangah hae ah kawk oh, tiah a naa.
10 Ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda jókòó lórí ìtẹ́ wọn, wọ́n wọ aṣọ ìgúnwà wọn ní ìta ẹnu ibodè Samaria, gbogbo àwọn wòlíì náà sì ń sọtẹ́lẹ̀ níwájú wọn.
Israel siangpahrang hoi Judah siangpahrang Jehosaphat loe, siangpahrang kahni to angkhuk hoi moe, Samaria vangpui akunhaih khongkha hmaa ah, angraeng tangkhang nuiah anghnut hoi; tahmaanawk boih mah nihnik hmaa ah lokthuih pae o.
11 Sedekiah ọmọ Kenaana sì ṣe ìwo irin fún ara rẹ̀, ó sì wí pé, “Báyìí ni Olúwa wí: ‘Wọ̀nyí ni ìwọ yóò fi kan àwọn ará Aramu títí ìwọ yóò fi run wọ́n.’”
Kenanah capa Zedekiah mah angmah hanah sum hoiah takii to sak moe, Angraeng mah, Syria kaminawk nam rosak boih ai karoek to, hae ih takiinawk hoiah nihcae to na tanawt tih, tiah a thuih, tiah a naa.
12 Gbogbo àwọn wòlíì tókù sì ń sọtẹ́lẹ̀ ohun kan náà wí pé, “Kọlu Ramoti Gileadi, kí o sì ṣẹ́gun.” Wọ́n sì wí pé, “Nítorí tí Olúwa yóò fi lé ọba lọ́wọ́.”
Kalah tahmaaanawk mah doeh, Ramoth Gilead to tuh ah, na pazawk tih; Angraeng mah siangpahrang ban ah paek tih, tiah thuih pae o boih.
13 Ìránṣẹ́ tí ó lọ pe Mikaiah wí fún un pé, “Wò ó, ẹnu kan náà ni ọ̀rọ̀ àwọn wòlíì fi jẹ́ rere fún ọba. Jẹ́ kí ọ̀rọ̀ rẹ bá ti àwọn tókù mu, kí o sì sọ rere.”
Mikaiah kawk han patoeh ih laicaeh mah anih khaeah, Khenah, kalah tahmaanawk boih mah loe siangpahrang khaeah, kahoih lok maeto ah ni thuih pae o; nang doeh nihcae ih lok to paroi ah loe, kahoih lok to thui toeng ah, tiah a naa.
14 Ṣùgbọ́n Mikaiah wí pé, “Bí Olúwa ti wà, ohun tí Olúwa bá sọ fún mi ni èmi yóò sọ fún un.”
Toe Mikaiah mah, Angraeng loe hing baktih toengah, Angraeng mah thuih ih lok khue ni ka thuih han, tiah a naa.
15 Nígbà tí ó sì dé, ọba sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Mikaiah, ṣé kí a lọ bá Ramoti Gileadi jagun, tàbí kí a jọ̀wọ́ rẹ̀?” Ó sì dáhùn wí pé, “Lọ, kí o sì ṣẹ́gun, nítorí Olúwa yóò fi lé ọba lọ́wọ́.”
Anih siangpahrang khaeah angzoh naah, siangpahrang mah, Mikaiah, Ramoth Gilead tuk hanah ka caeh han maw, ka caeh mak ai? tiah a dueng. Anih mah siangpahrang khaeah, Caeh ah, na pazawk tih, Angraeng mah siangpahrang ban ah na paek tih, tiah a naa.
16 Ọba sì wí fún un pé, “Ìgbà mélòó ni èmi yóò fi ọ bú pé kí o má ṣe sọ ohun kan fún mi bí kò ṣe òtítọ́ ní orúkọ Olúwa?”
Siangpahrang mah anih khaeah, Angraeng ih ahmin hoiah kamsoem ai hmuen tidoeh thui hmah, kamsoem hmuen khue to thuih hanah, vai nazetto maw lokkamhaih kang saksak han? tiah a naa.
17 Mikaiah sì dáhùn pé, “Mo rí gbogbo Israẹli túká kiri lórí àwọn òkè bí àgùntàn tí kò ní olùṣọ́, Olúwa sì wí pé, ‘Àwọn wọ̀nyí kò ní olúwa. Jẹ́ kí olúkúlùkù padà sí ilé rẹ̀ ní àlàáfíà.’”
To naah Maikaiah mah, Tuu toepkung om ai, kamhet phang tuunawk baktiah, mae nuiah kamhet phang Israel kaminawk to ka hnuk; Angraeng mah, Hae kaminawk loe angraeng tawn o ai pongah, nihcae loe angmacae im ah amlaem o boih nasoe, tiah a thuih, tiah a naa.
18 Ọba Israẹli sì wí fún Jehoṣafati pé, “Ǹjẹ́ èmi kò sọ fún ọ pé kò sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìre kan sí mi rí bí kò ṣe ibi?”
Israel siangpahrang mah Jehosaphat khaeah, Hae kami mah kai hanah kahoih hmuen tidoeh thui vai ai, kasae khue ni a thuih, tiah ka thuih na ai maw? tiah a naa.
19 Mikaiah sì tún wí pé, “Nítorí náà gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa. Mo rí Olúwa jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú gbogbo ogun ọ̀run dúró ní apá ọ̀tún àti ní apá òsì rẹ̀.
Mikaiah mah, To pongah Angraeng ih lok to tahngai ah, angmah ih angraeng tangkhang pongah anghnu Angraeng hoi a taeng ah banqoi bantang angdoe van misatuh kaminawk to ka hnuk.
20 Olúwa sì wí pé, ‘Ta ni yóò tan Ahabu láti kọlu Ramoti Gileadi? Kí ó sì tọ ikú rẹ̀ lọ níbẹ̀?’ “Ẹnìkan wí báyìí, ẹlòmíràn sì sọ òmíràn.
Angraeng mah, Ahab loe Ramoth Gilead ah misatuk moe, to ah duek hanah mi mah maw zoek thai tih? tiah a naa. To naah kami maeto mah hae tiah thuih moe, kalah maeto bae mah hae tiah thuih pae.
21 Ẹ̀mí kan sì jáde wá, ó sì dúró níwájú Olúwa, ó sì wí pé, ‘Èmi yóò tàn án.’
Hnukkhuem ah muithla maeto angzoh, Angraeng hmaa ah angdoet moe, kai mah ka zoek han hmang, tiah a naa.
22 “Olúwa sì béèrè pé, ‘Báwo?’ “Ó sì wí pé, ‘Èmi yóò jáde lọ, èmi yóò sì di ẹ̀mí èké ní ẹnu gbogbo àwọn wòlíì rẹ̀.’ “Olúwa sì wí pé, ‘Ìwọ yóò tàn án, ìwọ yóò sì borí, jáde lọ, kí o sì ṣe bẹ́ẹ̀.’
Angraeng mah, Kawbangmaw na zoek han loe? tiah a dueng. Anih mah, Ka caeh moe, angmah ih tahmaanawk pakha ah amsawnlok kathui muithla ah ka oh pae han, tiah a naa. Angraeng mah, Nang mah na zoek thai tih, caeh loe, sah ah, tiah a naa.
23 “Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa ti fi ẹ̀mí èké sí ẹnu gbogbo àwọn wòlíì rẹ wọ̀nyí. Olúwa sì ti sọ ibi sí ọ.”
To pongah Angraeng mah nangmah ih tahmaanawk ih pakha ah amsawnlok thui thaih muithla to suek moe, nam ro hanah Angraeng mah lok takroek boeh, tiah a naa.
24 Nígbà náà ni Sedekiah ọmọ Kenaana sì dìde, ó sì gbá Mikaiah lójú, ó sì wí pé, “Ọ̀nà wo ni ẹ̀mí Olúwa gbà lọ kúrò lọ́dọ̀ mi láti bá ọ sọ̀rọ̀?”
Toe Kananah capa Zedekiah loe caeh tahang moe, Mikaiah to mikhmai ah tabaeng pacoengah, Angraeng ih Muithla loe kai khae hoi tacawt ueloe, nang khaeah lokthui tih maw? tiah a naa.
25 Mikaiah sì dáhùn pé, “Ìwọ yóò ṣe ìwádìí ní ọjọ́ tí ìwọ yóò sá pamọ́ sínú ìyẹ̀wù.”
Mikaiah mah, Khenah, imthung ah nang hawk na niah, na panoek tih, tiah a naa.
26 Ọba Israẹli sì pàṣẹ pé, “Ẹ mú Mikaiah, kí ẹ sì mú un padà sọ́dọ̀ Amoni, olórí ìlú, àti sọ́dọ̀ Joaṣi ọmọ ọba
To naah Israel siangpahrang mah, Mikaiah to hoi oh loe, vangpui ukkung Ammon hoi siangpahrang capa Joash khaeah caeh o haih ah.
27 kí ẹ sì wí pé, ‘Báyìí ni ọba wí: Ẹ fi eléyìí sínú túbú, kí ẹ sì fi oúnjẹ ìpọ́njú àti omi ìpọ́njú bọ́ ọ, títí èmi yóò fi padà bọ̀ ní àlàáfíà.’”
Siangpahrang mah, Hae kami hae thongim thungah pakhrah oh, lunghoihta hoiah kang zo ai karoek to, takaw hoi tui khue ai ah loe, tidoeh paek o hmah, tiah a thuih, tiah thui paeh, tiah a naa.
28 Mikaiah sì wí pé, “Bí ìwọ bá padà bọ̀ ní àlàáfíà, Olúwa kò ti ipa mi sọ̀rọ̀.” Ó sì tún wí pé, “Ẹ kíyèsi ọ̀rọ̀ mi, ẹ̀yin ènìyàn gbogbo!”
Mikaiah mah, Lunghoihta hoiah nam laem let nahaeloe, Angraeng mah kai khaeah lokthui ai ah ni om tih; Aw kaminawk boih, ka thuih ih lok hae pakuem oh, tiah a naa.
29 Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda gòkè lọ sí Ramoti Gileadi.
To pongah Israel siangpahrang hoi Judah siangpahrang Jehosaphat loe Gilead prae Ramoth vangpui ah caeh hoi tahang.
30 Ọba Israẹli sì wí fún Jehoṣafati pé, “Èmi yóò pa aṣọ dà, èmi yóò sì lọ sí ojú ìjà, ṣùgbọ́n ìwọ yóò wọ aṣọ ìgúnwà rẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli pa aṣọ dà, ó sì lọ sí ojú ìjà.
Israel siangpahrang mah Jehosaphat khaeah, Kai loe krang angthlaeng moe, misa angtukhaih ahmuen ah ka caeh han; toe nang loe siangpahrang khukbuen to angkhuk ah, tiah a naa. Israel siangpahrang loe krang angthlaeng moe, misa angtukhaih ahmuen ah caeh.
31 Ọba Aramu ti pàṣẹ fún àwọn olórí kẹ̀kẹ́ rẹ̀ méjìlélọ́gbọ̀n wí pé, “Ẹ má ṣe bá ẹnìkankan jà, ẹni kékeré tàbí ẹni ńlá, bí kò ṣe ọba Israẹli nìkan.”
Toe Syria siangpahrang mah angmah ih hrang lakok ukkung angraeng quithumto pacoeng, hnettonawk khaeah, Israel siangpahrang khue ai ah loe, kami kalen doeh, kathoeng doeh, tuh o hmah, tiah a naa.
32 Nígbà tí àwọn olórí kẹ̀kẹ́ sì rí Jehoṣafati, wọ́n sì wí pé, “Dájúdájú ọba Israẹli ni èyí.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n yípadà láti bá a jà, ṣùgbọ́n nígbà tí Jehoṣafati sì kígbe sókè,
Hrang lakok ukkung ih angraengnawk mah Jehosaphat to hnuk o naah, Hae kami loe Israel siangpahrang kalang boeh mue, tiah poek o. To pongah anih to tuk hanah patom o; to naah Jehosaphat loe hangh.
33 àwọn olórí kẹ̀kẹ́ sì rí i pé kì í ṣe ọba Israẹli, wọ́n sì padà kúrò lẹ́yìn rẹ̀.
Hrang ukkung angraengnawk mah anih loe, Israel siangpahrang na ai ni, tiah panoek o naah, patom ai ah toengh o sut.
34 Ṣùgbọ́n ẹnìkan sì fa ọrun rẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀, ó sì ta ọba Israẹli láàrín ìpàdé ẹ̀wù irin. Ọba Israẹli sì wí fún olùtọ́jú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ pé, “Yí ọwọ́ rẹ dà, kí o sì mú mi jáde kúrò nínú ogun. Èmi ti gbọgbẹ́.”
Toe kami maeto mah pala to lak moe, kah naah, Israel siangpahrang ih aphaw salakah cop; to naah siangpahrang mah hrang lakok mong kami khaeah, Karangah angqoih loe, misatukhaih ahmuen hoiah na cawn haih ah, ahmaa ka caak boeh, tiah a naa.
35 Ogun náà sì le ní ọjọ́ náà, a sì dá ọba dúró nínú kẹ̀kẹ́ kọjú sí àwọn ará Aramu. Ẹ̀jẹ̀ sì sàn jáde láti inú ọgbẹ́ rẹ̀ sí àárín kẹ̀kẹ́ náà, ó sì kú ní àṣálẹ́.
To na ni loe misatuk paroeai nung. Siangpahrang loe Syria kaminawk hoi misa angtuk nathung hrang lakok nuiah kami to amha moe oh; ahma hoi tacawt athii loe hrang lakok thung ah long tathuk boih, duembang phak naah loe a duek.
36 A sì kéde la ibùdó já ní àkókò ìwọ̀-oòrùn wí pé, “Olúkúlùkù sí ìlú rẹ̀ àti olúkúlùkù sí ilẹ̀ rẹ̀!”
Duembang tue phak naah loe, Kami boih angmacae vangpui hoi angmacae prae ah caeh o boih ah, tiah misatuh kaminawk thungah lok taphonghaih to sak o.
37 Bẹ́ẹ̀ ni ọba kú, a sì gbé e wá sí Samaria, wọ́n sì sin ín ní Samaria.
Siangpahrang loe duek moe, Samaria ah aput o pacoengah, to ah aphum o.
38 Wọ́n sì wẹ kẹ̀kẹ́ náà ní adágún Samaria, àwọn ajá sì lá ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, àwọn àgbèrè sì wẹ ara wọn nínú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa ti sọ.
Samaria ih tuili maeto ah, maiphaw maica hoi hrangleengnawk to pasaeh o. Angraeng mah thuih ih lok baktih toengah, uinawk mah anih ih athii to palaeh o.
39 Ní ti ìyókù ìṣe Ahabu, àti gbogbo èyí tí ó ṣe, àti ilé eyín erin tí ó kọ́, àti gbogbo ìlú tí ó tẹ̀dó, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli?
Ahab siangpahrang ah oh nathung kaom hmuennawk hoi a sak ih hmuennawk, tasaino hoi sak ih siangpahrang im, sipae hoi thungh ih vangpuinawk loe, Israel siangpahrangnawk ahmin pakuemhaih cabu thungah tarik o na ai maw?
40 Ahabu sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀. Ahasiah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Ahab loe ampanawk khaeah anghak; anih zuengah a capa Ahaziah to siangpahrang ah oh.
41 Jehoṣafati ọmọ Asa, sì bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba lórí Juda ní ọdún kẹrin Ahabu ọba Israẹli.
Israel siangpahrang Ahab siangpahrang ah ohhaih saning palito naah, Asa capa Jehosaphat to Judah siangpahrang ah oh.
42 Jehoṣafati sì jẹ́ ẹni ọdún márùndínlógójì nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ń jẹ ọba ní ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ní Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Asuba ọmọbìnrin Silihi.
Jehosaphat siangpahrang ah oh naah, saning quithumto pacoeng, saning pangato oh boeh; anih loe Jerusalem ah saning pumphae pangato thung siangpahrang ah oh. Amno ih ahmin loe, Shilhi canu Azubah.
43 Ó sì rìn nínú gbogbo ọ̀nà Asa baba rẹ̀, kò sì yípadà kúrò nínú rẹ̀; ó sì ṣe èyí tí ó tọ́ ní ojú Olúwa. Kìkì àwọn ibi gíga ni a kò mú kúrò, àwọn ènìyàn sì ń rú ẹbọ, wọ́n sì ń sun tùràrí níbẹ̀.
Anih loe a sak ih hmuen boih ah, ampa Asa ih loklam to caeh taak ai, pazui boih; Angraeng mikhnuk ah katoeng hmuen to a sak; toe hmuensangnawk to phrae ai; to pongah kaminawk mah to ahmuen ah angbawnhaih sak o moe, hmuihoihnawk to a thlaek o.
44 Jehoṣafati sì wà ní àlàáfíà pẹ̀lú ọba Israẹli.
Jehosaphat loe Israel siangpahrang hoi angdaehhaih to sak.
45 Ní ti ìyókù ìṣe Jehoṣafati àti ìṣe agbára rẹ̀ tí ó ṣe, àti bí ó ti jagun sí, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda?
Jehosaphat siangpahrang ah oh nathung kaom hmuennawk, a thacakhaih hoi misa angtukhaihnawk loe, Judah siangpahrangnawk ahmin pakuemhaih cabu thungah tarik o na ai maw?
46 Ó pa ìyókù àwọn ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà ní ọjọ́ Asa baba rẹ̀ run kúrò ní ilẹ̀ náà.
Anih loe ampa Asa hing nathung kaom kanghmat tangyat zaw nongpanawk to prae thung hoiah haek boih.
47 Nígbà náà kò sí ọba ní Edomu; adelé kan ni ọba.
To naah Edom ah siangpahrang om ai; siangpahrang bomkung mah ni prae to uk.
48 Jehoṣafati kan ọkọ̀ Tarṣiṣi láti lọ sí Ofiri fún wúrà, ṣùgbọ́n wọn kò lọ, nítorí àwọn ọkọ̀ náà fọ́ ní Esioni-Geberi.
Jehosaphat loe Ophir ah sui phawh hanah Tarshish palongpui to sak; toe palongpui loe Ezion-Geber vangpui ah amro ving pongah, vaito doeh tuipui hoiah kholong caeh vai ai.
49 Ní ìgbà náà Ahasiah ọmọ Ahabu wí fún Jehoṣafati pé, “Jẹ́ kí àwọn ìránṣẹ́ mi bá àwọn ìránṣẹ́ rẹ lọ nínú ọkọ̀,” ṣùgbọ́n Jehoṣafati kọ̀.
To naah Ahab capa Ahaziah mah Jehosaphat khaeah, Na tamnanawk hoi kai ih tamnanawk palongpui thungah nawnto caeh o nasoe, tiah a naa. Toe Jehosaphat mah angmak pae.
50 Nígbà náà ni Jehoṣafati sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ ní ìlú Dafidi, baba rẹ. Jehoramu ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
To pacoengah Jehosaphat loe ampanawk khaeah anghak moe, ampa David vangpui thungah aphum o. Anih zuengah a capa Jehoram to siangpahrang ah oh.
51 Ahasiah ọmọ Ahabu bẹ̀rẹ̀ sí jẹ ọba lórí Israẹli ní Samaria ní ọdún kẹtàdínlógún Jehoṣafati ọba Juda, ó sì jẹ ọba ní ọdún méjì lórí Israẹli.
Judah siangpahrang Jehosaphat siangpahrang ah ohhaih saning hatlaisarihto naah, Ahab capa Ahaziah to Israel siangpahrang ah oh; saning hnetto thung Israel siangpahrang ah oh.
52 Ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, nítorí tí ó rìn ní ọ̀nà baba rẹ̀, àti ní ọ̀nà ìyá rẹ̀, àti ní ọ̀nà Jeroboamu ọmọ Nebati, tí ó mú Israẹli dẹ́ṣẹ̀.
Anih loe Angraeng mikhnuk ah kahoih ai hmuen to sak; Israel kaminawk zaehaih sahsakkung, Nabat capa Jeroboam caehhaih loklam, amno hoi ampa caehhaih loklam to pazui.
53 Ó sì sin Baali, ó sì ń bọ Baali, ó sì mú Olúwa, Ọlọ́run Israẹli bínú, gẹ́gẹ́ bí i baba rẹ̀ ti ṣe.
Ampa mah sak ih hmuen baktih toengah, Baal ih tok to sak pae moe, anih to bok pongah, Israel Angraeng Sithaw to palungphuisak.

< 1 Kings 22 >