< 1 Kings 20 >

1 Beni-Hadadi ọba Aramu sì gbá gbogbo ogun rẹ̀ jọ. Ọba méjìlélọ́gbọ̀n sì ń bẹ pẹ̀lú rẹ̀ àti ẹṣin àti kẹ̀kẹ́, ó sì gòkè lọ, ó sì dó ti Samaria, ó sì kọlù ú.
Na ka huihuia tana ope katoa e Peneharara kingi o Hiria; e toru tekau ma rua nga kingi ona hoa, me nga hoiho, me nga hariata: na haere ana ia, a whakapaea ana a Hamaria, tauria ana e ia.
2 Ó sì rán àwọn ìránṣẹ́ sí ìlú sí Ahabu ọba Israẹli wí pé, “Báyìí ni Beni-Hadadi wí,
Na ka tonoa etahi karere e ia ki a Ahapa kingi o Iharaira, ki te pa, a ka mea ki a ia, Ko te kupu tenei a Peneharara,
3 ‘Fàdákà àti wúrà rẹ tèmi ni, àti àwọn tí ó dára jùlọ nínú àwọn aya rẹ àti àwọn ọmọ rẹ tèmi ni wọ́n.’”
Ko tau hiriwa, ko tau koura, naku ena: me au wahine, me au tamariki, nga mea papai, naku ena.
4 Ọba Israẹli sì dá a lóhùn pé, “Gẹ́gẹ́ bí ìwọ ṣe wí olúwa mi ọba, èmi àti ohun gbogbo tí mo ní tìrẹ ni.”
Na ka whakahoki te kingi o Iharaira, ka mea, Rite tonu ki tau i mea na, e toku ariki, e te kingi: nau ahau me aku mea katoa.
5 Àwọn oníṣẹ́ náà sì tún padà wá, wọ́n sì wí pé, “Báyìí ni Beni-Hadadi sọ wí pé, ‘Mo ránṣẹ́ láti béèrè fún fàdákà rẹ àti wúrà rẹ, àwọn aya rẹ àti àwọn ọmọ rẹ.
Na ka hoki nga karere, ka mea, Ko te kupu tenei a Peneharara, e ki ana, I tono tangata ano ahau ki a koe hei mea atu, Me homai e koe tau hiriwa, tau koura, au wahine, me au tamariki;
6 Ṣùgbọ́n ní ìwòyí ọ̀la, èmi yóò rán àwọn ìránṣẹ́ mi sí ọ láti wá ilé rẹ wò àti ilé àwọn ìránṣẹ́ rẹ. Wọn yóò gba gbogbo ohun tí ó bá dára lójú rẹ, wọn yóò sì kó o lọ.’”
Na kia penei apopo ka tonoa atu e ahau aku tangata ki a koe, ki te rapu i roto i tou whare, i nga whare ano o au tangata; na, ko nga mea katoa e minaminatia ana e ou kanohi, tera e tangohia mai i o ratou ringa, ka maua mai.
7 Nígbà náà ni ọba Israẹli pe gbogbo àwọn àgbàgbà ìlú, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ wo bí ọkùnrin yìí ti ń fẹ́ ìyọnu! Nígbà tí ó ránṣẹ́ fún àwọn aya mi, àti fún àwọn ọmọ mi, àti fún fàdákà mi, àti fún wúrà mi, èmi kò sì fi dù ú.”
Katahi te kingi o Iharaira ka karanga ki nga kaumatua katoa o te whenua, a ka mea, Kia ata whakaaro koutou, kia kite kei te rapu tenei tangata i te kino: i tono tangata mai hoki ia ki ahau mo aku wahine, mo aku tamariki, mo taku hiriwa, a mo taku koura; a kihai i kaiponuhia e ahau ki a ia.
8 Àwọn àgbàgbà àti gbogbo ènìyàn dá a lóhùn pé, “Má ṣe fi etí sí tirẹ̀ tàbí kí ó gbà fún un.”
Na ka mea nga kaumatua katoa, ratou ko te iwi katoa ki a ia, Kaua e whakarongo, kaua e whakaae.
9 Nígbà náà ni ó sọ fún àwọn oníṣẹ́ Beni-Hadadi pé, “Sọ fún olúwa mi ọba pé, ‘Ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò ṣe ohun gbogbo tí ó ránṣẹ́ fún látètèkọ́ṣe, ṣùgbọ́n nǹkan yìí ni èmi kò le ṣe.’” Wọ́n padà lọ, wọ́n sì mú èsì padà wá fún Beni-Hadadi.
Katahi ia ka mea ki nga karere a Peneharara, Mea atu ki toku ariki, ki te kingi, Ko nga mea katoa i tono mai ai koe ki tau pononga i te tuatahi, ka meatia e ahau: ko tenei mea ia e kore e taea e ahau te mea. Na haere ana nga karere ki te whakahok i i te kupu.
10 Beni-Hadadi sì tún rán oníṣẹ́ mìíràn sí Ahabu wí pé, “Kí àwọn òrìṣà kí ó ṣe bẹ́ẹ̀ sí mi àti jù bẹ́ẹ̀ lọ pẹ̀lú bí eruku Samaria yóò tó fún ìkúnwọ́ fún gbogbo ènìyàn tí ń tẹ̀lé mi.”
Na ka tono tangata ano a Peneharara, ka mea, Kia meatia mai tenei e nga atua ki ahau, me era atu mea, ki te rato i te puehu o Hamaria nga ringa o te hunga katoa e whai ana i ahau.
11 Ọba Israẹli sì dáhùn wí pé, “Sọ fún un pé, ‘Má jẹ́ kí ẹni tí ń hámọ́ra halẹ̀ bí ẹni tí ń bọ́ ọ sílẹ̀.’”
Na ka whakahoki te kingi o Iharaira, ka mea, Ki atu ki a ia, Kaua te tangata e whitiki ana i tona pukupuku, e whakamanamana, e pera me te tangata e wewete ana.
12 Beni-Hadadi sì gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí nígbà tí òun àti àwọn ọba ń mu ọtí nínú àgọ́ wọn, ó sì pàṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ wí pé, “Ẹ ṣígun sí ìlú náà.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ṣe tan láti kọlu ìlú náà.
I te rongonga o Peneharara i tenei kupu, i a ia e inu ana, ratou ko nga kingi i roto i nga teneti, ka mea ia ki ana tangata, Whakatikaia a koutou ngohi. Na whakatikaia ana a ratou ngohi hei whawhai ki te pa.
13 Sì kíyèsi i, wòlíì kan tọ Ahabu ọba Israẹli wá, ó sì wí pé, “Báyìí ni Olúwa wí: ‘Ìwọ rí gbogbo ọ̀pọ̀lọpọ̀ ogun yìí? Èmi yóò fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́ lónìí, nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa.’”
Na, ka whakatata mai tetahi poropiti ki a Ahapa kingi o Iharaira, ka mea, Ko ta Ihowa kupu tenei, Ka kite koe i tenei ope nui katoa? Nana, ka hoatu ratou e ahau aianei ki tou ringa, a ka mohio koe ko Ihowa ahau.
14 Ahabu sì béèrè pé, “Ṣùgbọ́n ta ni yóò ṣe èyí?” Wòlíì náà sì dáhùn wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Nípa ìpẹ́ẹ̀rẹ̀ àwọn ìjòyè ìgbèríko.’” Nígbà náà ni ó wí pé. “Ta ni yóò bẹ̀rẹ̀ ogun náà?” Wòlíì sì dalóhùn pé, “Ìwọ ni yóò ṣe é.”
A ka mea a Ahapa, Ma wai? Ano ra ko tera, Ko ta Ihowa kupu tenei, Ma nga taitama o nga rangatira o nga kawanatanga. A ka mea ia, Ma wai e timata te whawhai? A ka mea tera, Mau.
15 Nígbà náà ni Ahabu ka àwọn ìjòyè kéékèèké ìgbèríko, wọ́n sì jẹ́ igba ó lé méjìlélọ́gbọ̀n. Nígbà náà ni ó sì kó gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tókù jọ, gbogbo wọn sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin.
Na ka whakaemia e ia nga taitama a nga rangatira o nga kawanatanga, e rua rau e toru tekau ma rua ratou: i muri i a ratou i whakaemia ano e ia te iwi katoa, ara nga tama katoa a Iharaira, e whitu mano.
16 Wọ́n sì jáde lọ ní ọ̀sán gangan, nígbà tí Beni-Hadadi àti àwọn ọba méjìlélọ́gbọ̀n tí ń ràn án lọ́wọ́ ń mu àmupara nínú àgọ́.
Na puta ana ratou i te poutumarotanga. Ko Peneharara ia i te inu i roto i nga teneti, a haurangi iho, a ia me nga kingi, ara ko nga kingi e toru tekau ma rua, ona whakauru.
17 Àwọn ìjòyè kéékèèké ìgbèríko tètè kọ́ jáde lọ. Beni-Hadadi sì ránṣẹ́ jáde, wọ́n sì sọ fún un wí pé, “Àwọn ọkùnrin ń ti Samaria jáde wá.”
Na ka puta tuatahi ko nga taitama a nga rangatira o nga kawanatanga: na ka tono tangata a Peneharara; a ka korero ratou ki a ia, ka mea, He tangata enei kua puta mai i Hamaria.
18 Ó sì wí pé, “Bí wọ́n bá bá ti àlàáfíà jáde wá, ẹ mú wọn láààyè; bí ti ogun ni wọ́n bá bá jáde, ẹ mú wọn láààyè.”
Ano ra ko tera, Ki te mea he hohou rongo i puta mai ai ratou, hopukia oratia: ki te mea ano he whawhai i puta mai ai, hopukia oratia.
19 Àwọn ìjòyè kéékèèké wọ̀nyí ti àwọn ìjòyè ìgbèríko jáde ti ìlú wá, àti ogun tí ó tẹ̀lé wọn.
Heoi puta ana enei ki waho o te pa, nga taitamariki o nga kawanatanga, me te ope i muri i a ratou.
20 Olúkúlùkù sì pa ọkùnrin kọ̀ọ̀kan. Àwọn ará Aramu sì sá, Israẹli sì lépa wọn. Ṣùgbọ́n Beni-Hadadi ọba Aramu sì sálà lórí ẹṣin pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́ṣin.
Na patua ana e ratou tana tangata, tana tangata; a rere ana nga Hiriani, whaia ana e Iharaira; ko Peneharara ia kingi o Hiria, i mawhiti i runga i te hioho, ratou ko nga kaieke hioho.
21 Ọba Israẹli sì jáde lọ, ó sì kọlu àwọn ẹṣin àti kẹ̀kẹ́, ó pa àwọn ará Aramu ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.
Na ka puta te kingi o Iharaira, a patua iho nga hoiho me nga hariata; heoi patua ana nga Hiriani, nui atu te parekura.
22 Lẹ́yìn náà, wòlíì náà sì wá sọ́dọ̀ ọba Israẹli, ó sì wí pé, “Lọ, mú ara rẹ gírí, kí o sì mọ̀, kí o sì wo ohun tí ìwọ yóò ṣe, nítorí ní àmọ́dún ọba Aramu yóò tún gòkè tọ̀ ọ́ wá.”
Na ka haere te poropiti ki te kingi o Iharaira, a ka mea ki a ia, Haere ki te whakakaha i a koe; kia mohio hoki, kia mahara ki tau e mea ai; ka taka hoki te tau, ka whakaekea koe e te kingi o Hiria.
23 Àwọn ìránṣẹ́ ọba Aramu sì wí fún un pé, “Ọlọ́run wọn, ọlọ́run òkè ni. Ìdí nìyìí tí wọ́n ṣe ní agbára jù wá lọ. Ṣùgbọ́n bí a bá bá wọn jà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, àwa yóò ní agbára jù wọ́n lọ dájúdájú.
Na ka mea nga tangata a te kingi o Hiria ki a ia, He atua maunga o ratou atua; koia ratou i kaha ai i a tatou; kia whawhai ia tatou ki a ratou i te mania, ka kaha tatou i a ratou.
24 Nǹkan yìí ni kí o sì ṣe, mú àwọn ọba kúrò, olúkúlùkù kúrò ní ipò rẹ̀, kí o sì fi baálẹ̀ sí ipò wọn.
Na ko tenei tau e mea ai; whakawateatia atu nga kingi, tenei, tenei i tona wahi; a whakaritea etahi rangatira hei whakakapi mo ratou.
25 Kí o sì tún kó ogun jọ fún ara rẹ bí èyí tí ó ti sọnù; ẹṣin fún ẹṣin, kẹ̀kẹ́ fún kẹ̀kẹ́; kí a bá lè bá Israẹli jà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀. Nítòótọ́ àwa yóò ní agbára jù wọ́n lọ.” Ó sì gba tiwọn, ó sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Na taua tetahi ope, kia rite ki tenei au kua hinga nei, he hoiho, he hoiho, he hariata, he hariata, a ka whawhai tatou ki a ratou ki te mania: tera tatou e kaha i a ratou. Na rongo tonu ia ki to ratou reo, a peratia ana e ia.
26 Ó sì ṣe ní àmọ́dún, Beni-Hadadi ka iye àwọn ará Aramu, ó sì gòkè lọ sí Afeki, láti bá Israẹli jagun.
Na, i te takanga o te tau, ka whakaemia e Peneharara nga Hiriani, a haere ana ki Apeke ki te whawhai ki a Iharaira.
27 Nígbà tí a sì ka àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì pèsè oúnjẹ, wọ́n sì lọ pàdé wọn. Àwọn ọmọ Israẹli sì dó ní òdìkejì wọn gẹ́gẹ́ bí agbo ọmọ ewúrẹ́ kékeré méjì, nígbà tí àwọn ará Aramu kún ilẹ̀ náà.
Na ka taua ano nga tama a Iharaira, a ka whai kai, a ka haere ki te tu i a ratou: a noho ana nga tama a Iharaira i to ratou ritenga atu, koia ano kei nga kahui iti e rua o nga kuao koati; ko nga Hiriani ia, kapi ana te whenua i a ratou.
28 Ènìyàn Ọlọ́run kan sì gòkè wá, ó sì sọ fún ọba Israẹli pé, “Báyìí ni Olúwa wí: ‘Nítorí tí àwọn ará Aramu rò pé Olúwa, Ọlọ́run òkè ni, ṣùgbọ́n òun kì í ṣe Ọlọ́run àfonífojì, nítorí náà èmi ó fi gbogbo ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn yìí lé ọ lọ́wọ́, ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
Na ka haere te tangata a te Atua, a ka korero ki te kingi o Iharaira, ka mea, Ko te kupu tenei a Ihowa, Kua mea nei nga Hiriani, He atua maunga a Ihowa, ehara ia i te atua raorao, na ka hoatu e ahau tenei ope nui katoa ki tou ringa, a ka mohio k outou ko Ihowa ahau.
29 Wọ́n sì dó sí òdìkejì ara wọn fún ọjọ́ méje, àti ní ọjọ́ keje, wọ́n pàdé ogun. Àwọn ọmọ Israẹli sì pa ọ̀kẹ́ márùn-ún ẹlẹ́ṣẹ̀ nínú àwọn ará Aramu ní ọjọ́ kan.
Na noho ana ratou, tetahi, tetahi, anga atu, anga mai, e whitu nga ra. A i te whitu o nga ra ka pipiri ki te whawhai. Na patua iho o nga Hiriani e nga tama a Iharaira kotahi rau mano i taua ra kotahi.
30 Àwọn tókù sì sá àsálà lọ sí Afeki, sínú ìlú tí odi ti wó lù ẹgbàá mẹ́tàlá lé ẹgbẹ̀rún nínú wọn. Beni-Hadadi sì sálọ sínú ìlú, ó sì fi ara pamọ́ sínú ìyẹ̀wù.
Ko nga morehu ia i rere ki Apeke, ki roto ki te pa; a horo iho ana te taiepa ku runga ki nga mano e rua tekau ma whitu o nga morehu; ko Peneharara ia i rere, a haere ana ki roto ki te pa ki tetahi ruma i roto rawa.
31 Àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ sì wí fún un pé, “Wò ó, a ti gbọ́ pé àwọn ọba ilẹ̀ Israẹli jẹ́ ọba aláàánú, mo bẹ̀ ọ́ jẹ́ kí àwa kí ó tọ̀ ọ́ lọ pẹ̀lú aṣọ ọ̀fọ̀ ní ẹ̀gbẹ́ wa, àti okùn yí orí wa ká. Bóyá òun yóò gba ẹ̀mí rẹ là.”
Na ka mea ana tangata ki a ia, Nana, kua rongo matou he kingi tohu tangata nga kingi o te whare o Iharaira: tena, kia maka iho e matou he kakahu taratara ki o matou hope, me etahi taura ki o matou matenga, a kia haere atu ki te kingi o Iharaira: tera pea koe e whakaorangia e ia.
32 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n di aṣọ ọ̀fọ̀ mọ́ ẹ̀gbẹ́ wọn, wọ́n sì fi okùn yí orí wọn ká, wọ́n sì tọ ọba Israẹli wá, wọ́n sì wí pé, “Ìránṣẹ́ rẹ Beni-Hadadi wí pé, ‘Èmi bẹ̀ ọ́ jẹ́ kí èmi kí ó yè.’” Ọba sì dáhùn wí pé, “Ó ń bẹ láààyè bí? Arákùnrin mi ni òun.”
Heoi whitikiria ana e ratou he kakahu taratara ki o ratou hope, he taura hoki ki o ratou matenga; a ka haere ki te kingi o Iharaira, ka mea, E mea ana tau pononga a Peneharara, Tena ra, kia ora ahau. A ka mea tera, Kei te ora ano ranei ia? ko to ku tuakana ia.
33 Àwọn ọkùnrin náà sì ṣe àkíyèsí gidigidi, wọ́n sì yára gbá ọ̀rọ̀ rẹ̀ mú, wọ́n sì wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, Beni-Hadadi arákùnrin rẹ.” Ọba sì wí pé, “Ẹ lọ mú u wá.” Nígbà tí Beni-Hadadi jáde tọ̀ ọ́ wá, Ahabu sì mú u gòkè wá sínú kẹ̀kẹ́.
Na i ata whakarongo aua tangata ki tana, a hohoro tonu te hopu i tona whakaaro, a ka mea, Ko tou tuakana ra, a Peneharara. Ano ra ko ia, Haere koutou, tikina atu ia. Heoi ka puta mai a Peneharara ki a ia, a ka mea tera kia eke ia ki te hariata.
34 Beni-Hadadi sì wí pé, “Èmi yóò dá àwọn ìlú tí baba mi ti gbà lọ́wọ́ baba rẹ padà, ìwọ sì le la ọ̀nà fún ara rẹ ní Damasku, bí baba mi ti ṣe ní Samaria.” Ahabu sì wí pé, “Èmi yóò rán ọ lọ pẹ̀lú májẹ̀mú yìí.” Bẹ́ẹ̀ ni ó ba dá májẹ̀mú, ó sì rán an lọ.
Na ka mea a Peneharara ki a ia, Ko nga pa i tangohia e toku papa i tou papa me whakahoki atu e ahau; a mau e hanga etahi huanui mau ki Ramahiku kia rite ki a toku papa i hanga ai ki Hamaria. Ano ra ko Ahapa, Me tuku koe e ahau i runga i tenei ka wenata. Na, whakaritea ana he kawenata e raua, a tukua ana ia.
35 Nípa ọ̀rọ̀ Olúwa, ọkùnrin kan nínú àwọn ọmọ àwọn wòlíì sì wí fún èkejì rẹ̀ pé, “Jọ̀ ọ́, lù mí,” ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti lù ú.
Na ka mea tetahi tangata o nga tama a nga poropiti ki tona hoa, he mea ki na Ihowa, Tena, patua ahau. Heoi kihai taua tangata i pai ki te patu i a ia.
36 Nígbà náà ni ó wí pé, “Nítorí tí ìwọ kò gba ohùn Olúwa gbọ́, kíyèsi i, bí ìwọ bá kúrò ní ọ̀dọ̀ mi, kìnnìún yóò pa ọ́.” Bí ó ti jáde lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, kìnnìún kan rí i, ó sì pa á.
Katahi ka mea tera ki a ia, i te mea kihai koe i whakarongo ki te reo o Ihowa, na, mawehe atu ana koe i konei, ka patua koe e te raiona. A, no te haerenga atu i tona taha, ka tutaki tetahi raiona ki a ia, patua iho.
37 Wòlíì náà sì rí ọkùnrin mìíràn, ó sì wí fún un pé, “Jọ̀ ọ́, lù mí.” Bẹ́ẹ̀ ni ọkùnrin náà sì lù ú, ó sì pa á lára.
Katahi ka tutaki ia ki tetahi atu tangata, a ka mea, Tena, patua ahau. Na ka patu taua tangata i a ia, he patu i motu ai.
38 Wòlíì náà sì lọ, ó sì dúró de ọba ní ojú ọ̀nà. Ó pa ara rẹ̀ dà ní fífi eérú bo ojú.
Heoi haere ana taua poropiti, a tu ana i te ara, he whanga i te kingi; i whakaahua ke hoki i a ia, ko tona tipare ki tona mata.
39 Bí ọba sì ti ń rékọjá, wòlíì náà ké sí i, ó sì wí pé, “Ìránṣẹ́ rẹ jáde wọ àárín ogun lọ, ẹnìkan sì wá sí ọ̀dọ̀ mi pẹ̀lú ìgbèkùn kan, ó sì wí pé, ‘Pa ọkùnrin yìí mọ́. Bí a bá fẹ́ ẹ kù, ẹ̀mí rẹ yóò lọ dípò ẹ̀mí rẹ̀, tàbí kí ìwọ san tálẹ́ǹtì fàdákà kan.’
A, i te kingi e haere ana, ka karanga ia ki te kingi, ka mea, I haere tau pononga ki waenganui o te whawhai: na ko te pekanga mai o tetahi tangata, kawea mai ana e ia tetahi tangata ki ahau, ka mea, Tiakina tenei tangata: ki te mea ka riro ia, k o koe ka mate hei ritenga mo tona matenga: me utu ranei e koe kia kotahi taranata hiriwa.
40 Nígbà tí ìránṣẹ́ rẹ̀ sì ní ìṣe níhìn-ín àti lọ́hùn ún, a fẹ́ ẹ kù.” Ọba Israẹli sì wí fún un pé, “Bẹ́ẹ̀ ni ìdájọ́ rẹ yóò rí, ìwọ fúnra rẹ̀ ti dá a.”
A, i tau pononga e mea noa ana i tenei mea, i tera mea, kua riro tera. Na ka mea te kingi o Iharaira ki a ia, Me pena te tikanga mou; kua tika mai na i a koe.
41 Nígbà náà ni wòlíì náà yára, ó sì mú eérú kúrò ní ojú rẹ̀, ọba Israẹli sì mọ̀ ọ́n pé ọ̀kan nínú àwọn wòlíì ni ó ń ṣe.
Na hohoro tonu te tango a tera i te tipare i ona kanohi, a ka mohio te kingi o Iharaira ki a ia ko tetahi o nga poropiti.
42 Ó sì wí fún ọba pé, “Báyìí ni Olúwa wí: ‘Ìwọ ti jọ̀wọ́ ọkùnrin tí èmi ti yàn sí ìparun pátápátá lọ́wọ́ lọ. Nítorí náà, ẹ̀mí rẹ yóò lọ fún ẹ̀mí rẹ, ènìyàn rẹ fún ènìyàn rẹ̀.’”
Na ka mea tera ki a ia, Ko te kupu tenei a Ihowa, Kua tukua atu nei i roto i tou ringa taku tangata i tukua putia atu nei e ahau ki te mate; na ko tou matenga hei ritenga mo tona matenga, me tou iwi hei utu mo tona iwi.
43 Ọba Israẹli sì lọ sí ilé rẹ̀ ní wíwú gbọ́, inú rẹ sì bàjẹ́, ó sì wá sí Samaria.
Na pouri ana, riri ana, te kingi o Iharaira, a haere ana ki tona whare; tae tonu atu ki Hamaria.

< 1 Kings 20 >