< 1 Kings 2 >

1 Nígbà tí ọjọ́ ikú Dafidi súnmọ́ etílé, ó pàṣẹ fún Solomoni ọmọ rẹ̀.
Rĩrĩa ihinda rĩa Daudi rĩakuhĩrĩirie rĩa gũkua-rĩ, agĩatha mũriũ Solomoni, akĩmwĩra atĩrĩ,
2 Ó sì wí pé, “Èmi ti fẹ́ lọ sí ọ̀nà gbogbo ayé, nítorí náà jẹ́ alágbára kí o sì fi ara rẹ hàn bí ọkùnrin,
“Rĩu ndĩ hakuhĩ gũthiĩ na njĩra ĩrĩa ĩgeragwo nĩ andũ othe a thĩ; nĩ ũndũ ũcio-rĩ, gĩa na hinya, wonanie atĩ ũrĩ mũndũ mũrũme ki,
3 kí o sì wòye ohun tí Olúwa Ọlọ́run rẹ béèrè, rìn ní ọ̀nà rẹ̀, kí o sì pa àṣẹ àti òfin rẹ̀ mọ́, àti ìdájọ́ rẹ, àti ẹ̀rí rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ nínú ìwé òfin Mose, nítorí kí ìwọ kí ó le è máa ṣe rere ní ohun gbogbo tí ìwọ ṣe, àti ní ibikíbi tí ìwọ bá lọ,
na ũmenyagĩrĩre ũrĩa Jehova Ngai waku endaga: Ũthiiage na njĩra ciake, na ũmenyagĩrĩre irĩra cia watho wake wa kũrũmĩrĩrwo na maathani make, na mawatho make na maũndũ marĩa endaga, o ta ũrĩa maandĩkĩtwo Watho-inĩ wa Musa, nĩgeetha ũgaacĩre maũndũ-inĩ mothe marĩa ũrĩĩkaga na kũrĩa guothe ũrĩthiiaga,
4 kí Olúwa kí ó lè pa ìlérí rẹ̀ tí ó sọ nípa tèmi mọ́ pé, ‘Bí àwọn ọmọ rẹ bá kíyèsi ọ̀nà wọn, tí wọ́n bá sì fi gbogbo àyà wọn àti ọkàn wọn rìn níwájú mi ní òtítọ́, o kì yóò sì kùnà láti ní ọkùnrin kan lórí ìtẹ́ Israẹli.’
nĩgeetha Jehova atũũrie kĩĩranĩro kĩrĩa aanjĩĩrĩire, akiuga ũũ: ‘Njiaro ciaku ingĩkaamenyerera mũtũũrĩre wacio, na ithiiage irĩ na wĩhokeku mbere yakwa na ngoro ciao ciothe, na meciiria macio mothe, gwaku gũtikaga mũndũ wa gũikarĩra gĩtĩ kĩa ũnene gĩa Isiraeli.’
5 “Ìwọ pẹ̀lú sì mọ ohun tí Joabu ọmọ Seruiah ṣe sí mi àti ohun tí ó ṣe sí balógun méjì nínú àwọn ológun Israẹli, sí Abneri ọmọ Neri àti sí Amasa ọmọ Jeteri. Ó sì pa wọ́n, ó sì ta ẹ̀jẹ̀ wọn sílẹ̀ ní ìgbà àlàáfíà bí í ti ojú ogun ó sì fi ẹ̀jẹ̀ náà sí ara àmùrè rẹ̀ tí ń bẹ ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, àti sí ara sálúbàtà rẹ̀ tí ń bẹ ní ẹsẹ̀ rẹ̀.
“Rĩu wee mwene nĩũĩ ũrĩa Joabu mũrũ wa Zeruia aanjĩkire, na ũrĩa eekire anene eerĩ a mbũtũ cia ita cia Isiraeli, nĩo Abineri mũrũ wa Neri, na Amasa mũrũ wa Jetheri. Nĩamooragire, agĩita thakame yao hĩndĩ ya thayũ, o taarĩ hĩndĩ ya mbaara, nayo thakame ĩyo ĩkĩgĩa mũcibi-inĩ wake wa njohero, na iraatũ-inĩ cia magũrũ make.
6 Ṣe sí í gẹ́gẹ́ bí ọgbọ́n rẹ̀, ṣùgbọ́n má ṣe jẹ́ kí ewú orí rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ sí isà òkú ní àlàáfíà. (Sheol h7585)
Ĩka ũrĩa ũkuona kwagĩrĩire kũringana na ũũgĩ waku, no ndũkanareke mũtwe ũcio wake ũrĩ mbuĩ ũkinye mbĩrĩra-inĩ na thayũ. (Sheol h7585)
7 “Ṣùgbọ́n fi inú rere hàn sí àwọn ọmọ Barsillai, ti Gileadi, jẹ́ kí wọn wà lára àwọn tí ó ń jẹun lórí tábìlì rẹ̀. Wọ́n dúró tì mí nígbà tí mo sá kúrò níwájú Absalomu arákùnrin rẹ.
“No ariũ a Barizilai wa Gileadi ũmatugage wega, na ũreke matuĩke amwe a arĩa mũrĩrĩĩaga nao metha-inĩ yaku. Nĩo mandũgamĩrĩire rĩrĩa ndooragĩra mũrũ wa thoguo Abisalomu.
8 “Àti kí o rántí, Ṣimei ọmọ Gera ẹ̀yà Benjamini tí Bahurimu wà pẹ̀lú rẹ̀, tí ó bú mi ní èébú tí ó korò ní ọjọ́ tí mo lọ sí Mahanaimu. Nígbà tí ó sọ̀kalẹ̀ wá pàdé mi ní Jordani, mo fi Olúwa búra fún un pé, ‘Èmi kì yóò fi idà pa ọ́.’
“Na ũririkane Shimei mũrũ wa Gera, ũrĩa Mũbenjamini kuuma Bahurimu, arĩ gũkũ nawe, na nĩwe wanumire na irumi ndũrũ mũthenya ũrĩa ndaathiiaga Mahanaimu. Rĩrĩa ookire kũndũnga hau Jorodani, nĩndehĩtire kũrĩ we na rĩĩtwa rĩa Jehova, ngĩmwĩra atĩrĩ, ‘Ndigakũũraga na rũhiũ rwa njora.’
9 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, má ṣe kíyèsi í gẹ́gẹ́ bí aláìlẹ́ṣẹ̀, ọkùnrin ọlọ́gbọ́n ni ìwọ ṣe; ìwọ yóò mọ ohun tí ìwọ yóò ṣe sí i. Mú ewú orí rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ sínú isà òkú pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀.” (Sheol h7585)
No rĩrĩ, tiga kuona ta atarĩ na ihĩtia. Wee ũrĩ mũndũ mũũgĩ; nĩũkamenya ũrĩa ũkaamwĩka. Ndũkanareke mũtwe ũcio wake ũrĩ mbuĩ ũgaathikwo ũtarĩ na thakame.” (Sheol h7585)
10 Nígbà náà ni Dafidi sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín ní ìlú Dafidi.
Na rĩrĩ, Daudi akĩhurũka hamwe na maithe make, na agĩthikwo thĩinĩ wa Itũũra inene rĩa Daudi.
11 Dafidi ti jẹ ọba lórí Israẹli ní ogójì ọdún, ọdún méje ni Hebroni àti ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ní Jerusalẹmu.
Aathamakĩire Isiraeli mĩaka mĩrongo ĩna: mĩaka mũgwanja aathamakire arĩ Hebironi, nayo mĩaka mĩrongo ĩtatũ na ĩtatũ agĩthamaka arĩ Jerusalemu.
12 Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi baba rẹ̀, ìjọba rẹ̀ sì fi ìdí múlẹ̀ gidigidi.
Nĩ ũndũ ũcio Solomoni agĩikarĩra gĩtĩ kĩa ũnene kĩa ithe Daudi, naguo wathani wake ũkĩĩhaanda, ũkĩrũma biũ.
13 Wàyí, Adonijah ọmọ Haggiti tọ Batṣeba, ìyá Solomoni wá. Batṣeba sì bi í pé, “Àlàáfíà ni o bá wa bí?” Ó sì dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, àlàáfíà ni.”
Na rĩrĩ, Adonija mũrũ wa Hagithu, agĩthiĩ harĩ Bathisheba nyina wa Solomoni. Bathisheba akĩmũũria atĩrĩ, “Ũũkĩte na thayũ?” Nake agĩcookia atĩrĩ, “Ĩĩ, ndooka na thayũ.”
14 Nígbà náà ni ó sì fi kún un pé, “Mo ní ohun kan láti sọ fún ọ.” Batṣeba sì wí pé, “Máa wí.”
Agĩcooka akiuga atĩrĩ, “Ndĩ na ũndũ ngũkwĩra.” Nake akĩmũcookeria atĩrĩ, “Njĩĩra.”
15 Ó wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí o ti mọ̀, ti tèmi ni ìjọba náà. Gbogbo Israẹli ti wò mí bí ọba wọn. Ṣùgbọ́n nǹkan yípadà, ìjọba náà sì ti lọ sí ọ̀dọ̀ arákùnrin mi, nítorí ó ti wá sọ́dọ̀ rẹ̀ láti ọwọ́ Olúwa wá.
Agĩkiuga atĩrĩ, “O ta ũrĩa wee ũũĩ-rĩ, ũthamaki ũyũ warĩ wakwa. Andũ a Isiraeli othe nĩ niĩ meetagĩrĩra nduĩke mũthamaki wao. No maũndũ makĩgarũrũka, naguo ũthamaki nĩũthiĩte kũrĩ mũrũ wa Baba; tondũ ũheanĩtwo kũrĩ we nĩ Jehova.
16 Nísinsin yìí mo ní ìbéèrè kan láti bi ọ́, má ṣe kọ̀ fún mi.” Ó wí pé, “O lè wí.”
Na rĩrĩ, ndĩ na ihooya ngwenda gũkũhooya, na ndũkarege.” Nake akĩmũcookeria atĩrĩ, “No ũrĩhooye.”
17 Bẹ́ẹ̀ ni ó sì tẹ̀síwájú pé, “Mo bẹ̀ ọ́, jọ̀wọ́ sọ fún Solomoni ọba (òun kì yóò kọ̀ fún ọ́) kí ó fún mi ní Abiṣagi ará Ṣunemu ní aya.”
Agĩthiĩ na mbere, akiuga atĩrĩ, “Ĩtĩkĩra kũũria Mũthamaki Solomoni, nĩ ũndũ wee ndangĩkũregera, aahe Abishagi ũrĩa Mũshunami atuĩke mũtumia wakwa.”
18 Batṣeba sì dáhùn pé, “Ó dára èmi yóò bá ọba sọ̀rọ̀ nítorí rẹ̀.”
Bathisheba agĩcookia atĩrĩ, “Nĩ wega, nĩ ngũkwarĩrĩria harĩ mũthamaki.”
19 Nígbà tí Batṣeba sì tọ Solomoni ọba lọ láti bá a sọ̀rọ̀ nítorí Adonijah, ọba sì dìde láti pàdé rẹ̀, ó sì tẹríba fún un, ó sì jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀. Ó sì tẹ́ ìtẹ́ kan fún ìyá ọba, ó sì jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Rĩrĩa Bathisheba aathiire kũrĩ Mũthamaki Solomoni akamũhe ũhoro wa Adonija-rĩ, mũthamaki agĩũkĩra na igũrũ akĩmũtũnga, akĩmũinamĩrĩra, na agĩikarĩra gĩtĩ gĩake kĩa ũnene. Akĩrehithĩria nyina gĩtĩ kĩa ũnene, nake nyina akĩmũikara guoko gwake kwa ũrĩo.
20 Ó sì wí pé, “Mo ní ìbéèrè kékeré kan láti béèrè lọ́wọ́ rẹ, má ṣe kọ̀ fún mi.” Ọba sì dáhùn wí pé, “Béèrè, ìyá mi; èmi kì yóò kọ̀ ọ́.”
Nake nyina akiuga atĩrĩ, “Ndĩ na kaũndũ kanini ngwenda gũkũhooya, na ndũkae kũrega.” Mũthamaki akĩmũcookeria atĩrĩ, “Maitũ, ũria ndikũrega.”
21 Nígbà náà ni ó wí pé, “Jẹ́ kí a fi Abiṣagi ará Ṣunemu fún Adonijah arákùnrin rẹ ní aya.”
Nĩ ũndũ ũcio nyina akiuga atĩrĩ, “Reke Abishagi ũrĩa Mũshunami ahikio nĩ mũrũ wa thoguo Adonija.”
22 Solomoni ọba sì dá ìyá rẹ̀ lóhùn pé, “Èéṣe tí ìwọ fi béèrè Abiṣagi ará Ṣunemu fún Adonijah! Ìwọ ìbá sì béèrè ìjọba fún un pẹ̀lú nítorí ẹ̀gbọ́n mi ní í ṣe, fún òun pàápàá àti fún Abiatari àlùfáà àti fun Joabu ọmọ Seruiah!”
Mũthamaki Solomoni akĩĩra nyina atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩgũtũma ũrie Abishagi ũrĩa Mũshunami ahikio nĩ Adonija? Ndũkĩmũũrĩrie ũthamaki o naguo, o na ti we ũkĩrĩ mũkũrũ kũrĩ niĩ, ĩĩ-ni, ũgĩtuĩke wake, na wa Abiatharu ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai na wa Joabu mũrũ wa Zeruia!”
23 Nígbà náà ni Solomoni ọba fi Olúwa búra pé, “Kí Ọlọ́run ki ó jẹ mí ní yà, àti jù bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú, bí Adonijah kò bá ní fi ẹ̀mí rẹ̀ san ìbéèrè yìí!
Hĩndĩ ĩyo Mũthamaki Solomoni akĩĩhĩta na rĩĩtwa rĩa Jehova, akiuga ũũ: “Ngai arooherithia o na anjĩhĩre mũno, aakorwo Adonija ndekũrĩha na muoyo wake nĩ ũndũ wa ũndũ ũcio orĩtie!
24 Àti nísinsin yìí, bí ó ti dájú pé Olúwa wà láààyè, ẹni tí ó ti mú mi jókòó lórí ìtẹ́ baba mi Dafidi, àti tí ó sì ti kọ́ ilé fún mi bí ó ti ṣèlérí, lónìí ni a ó pa Adonijah!”
Na rĩrĩ, ti-itherũ o ta ũrĩa Jehova atũũraga muoyo, o we ũtũmĩte ngaacĩre ũthamaki-inĩ wa baba, Daudi, na agetĩkĩra nduĩke wa rũciaro rwa nyũmba ya ũthamaki, o ta ũrĩa eranĩire-rĩ, Adonija no ekũũragwo ũmũthĩ!”
25 Solomoni ọba sì pàṣẹ fún Benaiah ọmọ Jehoiada, ó sì kọlu Adonijah, ó sì kú.
Nĩ ũndũ ũcio Mũthamaki Solomoni agĩatha Benaia mũrũ wa Jehoiada, nake agĩthiĩ akĩgũtha Adonija, akĩmũũraga.
26 Ọba sì wí fún Abiatari àlùfáà pé, “Padà lọ sí pápá rẹ ni Anatoti, ó yẹ fún ọ láti kú, ṣùgbọ́n èmi kì yóò pa ọ́ nísinsin yìí, nítorí o ti gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa Olódùmarè níwájú Dafidi baba mi, o sì ti ní ìpín nínú gbogbo ìyà tí baba mi jẹ.”
Mũthamaki akĩĩra Abiatharu ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai atĩrĩ, “Cooka mũgũnda-inĩ gwaku kũu Anathothu. Wee wagĩrĩirwo nĩ gũkua, no ndigũkũũraga rĩu, tondũ nĩwakuuaga ithandũkũ rĩa Mwathani Jehova hĩndĩ ya baba Daudi, na nĩwagwatanĩire na baba moritũ-inĩ make mothe.”
27 Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni yọ Abiatari kúrò nínú iṣẹ́ àlùfáà Olúwa, kí ó lè mú ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó ti sọ nípa ilé Eli ní Ṣilo ṣẹ.
Nĩ ũndũ ũcio Solomoni akĩeheria Abiatharu atige gũtuĩka mũthĩnjĩri-Ngai wa Jehova, nakĩo kiugo kĩa Jehova kĩrĩa aarĩirie kũu Shilo, gĩkoniĩ nyũmba ya Eli, gĩkĩhinga.
28 Nígbà tí ìròyìn sì dé ọ̀dọ̀ Joabu, ẹni tí ó ti dìtẹ̀ pẹ̀lú Adonijah bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò wà pẹ̀lú Absalomu, ó sì sálọ sínú àgọ́ Olúwa, ó sì di ìwo pẹpẹ mú.
Rĩrĩa ũhoro ũcio wakinyĩire Joabu, ũrĩa waciirĩire gwĩka ũũru marĩ na Adonija, o na gũtuĩka ndaanyiitanĩire na Abisalomu, akĩũrĩra hema-inĩ ya Jehova na akĩĩnyiitĩrĩra hĩa cia kĩgongona.
29 A sì sọ fún Solomoni ọba pé Joabu ti sálọ sínú àgọ́ Olúwa àti pé ó wà ní ẹ̀gbẹ́ pẹpẹ. Nígbà náà ni Solomoni pàṣẹ fún Benaiah ọmọ Jehoiada pé, “Lọ, kí o sì kọlù ú.”
Mũthamaki Solomoni akĩĩrwo atĩ Joabu orĩire hema-inĩ ya Jehova na aarĩ hakuhĩ na kĩgongona. Hĩndĩ ĩyo Solomoni agĩatha Benaia mũrũ wa Jehoiada atĩrĩ, “Thiĩ, ũmũũrage!”
30 Benaiah sì wọ inú àgọ́ Olúwa, ó sì wí fún Joabu pé, “Ọba sọ wí pé, ‘Jáde wá.’” Ṣùgbọ́n ó dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, èmi yóò kú níhìn-ín.” Benaiah sì mú èsì fún ọba, “Báyìí ni Joabu ṣe dá mi lóhùn.”
Nĩ ũndũ ũcio Benaia akĩingĩra hema ĩyo ya Jehova akĩĩra Joabu atĩrĩ, “Mũthamaki oiga atĩrĩ, ‘Uma na nja!’” No Joabu agĩcookia atĩrĩ, “Aca, ngũkuĩra haha.” Benaia agĩcookeria mũthamaki ũhoro, akĩmwĩra atĩrĩ, “Joabu anjĩĩra ũna na ũna.”
31 Ọba sì pàṣẹ fún Benaiah pé, “Ṣe bí ó ti wí. Kọlù ú, kí o sì sin ín, kí o sì mú ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi àti kúrò lọ́dọ̀ ilé baba mi, tí Joabu ti ta sílẹ̀.
Hĩndĩ ĩyo mũthamaki agĩatha Benaia, akĩmwĩra atĩrĩ, “Ĩka o ũguo oiga. Mũũrage na ũmũthike, nĩgeetha niĩ na nyũmba ya baba tũthirwo nĩ ihĩtia rĩa thakame ĩrĩa yaitirwo tũhũ nĩ Joabu.
32 Olúwa yóò sì san ẹ̀jẹ̀ tí ó ti ta sílẹ̀ padà fún un, nítorí tí ó kọlu ọkùnrin méjì, ó sì fi idà rẹ̀ pa wọ́n, Dafidi baba mi kò sì mọ̀. Àwọn méjèèjì ni Abneri ọmọ Neri olórí ogun Israẹli, àti Amasa ọmọ Jeteri olórí ogun Juda, wọ́n jẹ́ olódodo, wọ́n sì sàn ju òun fúnra rẹ̀ lọ.
Jehova nĩegũtũma acookererwo nĩ thakame ĩrĩa aaitire, tondũ nĩatharĩkĩire andũ eerĩ, na akĩmooraga na rũhiũ rwa njora, baba Daudi atooĩ akĩmooraga marĩ eerĩ, Abineri mũrũ wa Neri, ũrĩa warĩ mũnene wa mbũtũ cia ita cia Isiraeli, na Amasa mũrũ wa Jetheri, ũrĩa warĩ mũnene wa mbũtũ cia ita cia Juda, nao maarĩ andũ ega na arũngĩrĩru kũmũkĩra.
33 Kí ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ wọn wá sórí Joabu àti sórí irú-ọmọ rẹ̀ títí láé. Ṣùgbọ́n sórí Dafidi àti irú-ọmọ rẹ̀, sí ilé rẹ̀ àti sí ìtẹ́ rẹ̀, ni kí àlàáfíà Olúwa wà títí láé.”
Ihĩtia rĩu rĩa gũita thakame yao rĩrocookerera Joabu na njiaro ciake nginya tene. No kũrĩ Daudi na njiaro ciake, na nyũmba yake na ũthamaki wake, thayũ wa Jehova ũrogĩa kũrĩ o nginya tene.”
34 Bẹ́ẹ̀ ni Benaiah ọmọ Jehoiada sì gòkè lọ, ó sì kọlu Joabu, ó sì pa á, a sì sin ín ní ilẹ̀ ibojì ara rẹ̀ ní aginjù.
Nĩ ũndũ ũcio Benaia mũrũ wa Jehoiada agĩthiĩ akĩgũtha Joabu akĩmũũraga, nake agĩthikwo mũgũnda-inĩ wake kũu werũ-inĩ.
35 Ọba sì fi Benaiah ọmọ Jehoiada jẹ olórí ogun ní ipò Joabu àti Sadoku àlùfáà ní ipò Abiatari.
Mũthamaki akĩnenehia Benaia mũrũ wa Jehoiada akĩmũtua mũnene wa mbũtũ cia ita handũ ha Joabu, na agĩcookia Zadoku atuĩke mũthĩnjĩri-Ngai ithenya rĩa Abiatharu.
36 Nígbà náà ni ọba ránṣẹ́ sí Ṣimei, ó sì wí fún un pé, “Kọ́ ilé fún ara rẹ ní Jerusalẹmu, kí o sì máa gbé ibẹ̀, ṣùgbọ́n kí o má sì ṣe lọ sí ibòmíràn.
Ningĩ mũthamaki agĩtũmana Shimei eetwo, akĩmwĩra atĩrĩ, “Wĩakĩre nyũmba Jerusalemu na ũtũũre kuo, no ndũkanathiĩ kũndũ kũngĩ.
37 Ọjọ́ tí ìwọ bá jáde, tí o sì kọjá àfonífojì Kidironi, kí ìwọ kí ó mọ̀ dájúdájú pé ìwọ yóò kú; ẹ̀jẹ̀ rẹ yóò sì wà lórí ara rẹ.”
Mũthenya ũrĩa ũkoima kuo ũringe Mũkuru wa Kidironi, ũmenye wega no ũgaakua; nayo thakame yaku nĩĩgagũcookerera wee mwene.”
38 Ṣimei sì dá ọba lóhùn pé, “Ohun tí ìwọ sọ dára. Ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe bí olúwa mi ọba ti wí.” Ṣimei sì gbé ní Jerusalẹmu fún ìgbà pípẹ́.
Shimei agĩcookeria mũthamaki atĩrĩ, “Ũguo woiga nĩ wega. Ndungata yaku nĩĩgwĩka o ta ũrĩa mũthamaki mwathi wakwa oiga.” Nake Shimei agĩikara Jerusalemu ihinda iraaya.
39 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ọdún mẹ́ta, àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ Ṣimei méjì sì sálọ sọ́dọ̀ Akiṣi ọmọ Maaka, ọba Gati, a sì sọ fún Ṣimei pé, “Àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ méjì wà ní Gati.”
No mĩaka ĩtatũ yathira-rĩ, ngombo igĩrĩ cia Shimei ikĩũra igĩthiĩ kwa Akishi, mũrũ wa Maaka, mũthamaki wa Gathu, nake Shimei akĩĩrwo atĩrĩ, “Ngombo ciaku irĩ Gathu.”
40 Fún ìdí èyí, ó sì di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ní gàárì, ó sì lọ sọ́dọ̀ Akiṣi ní Gati láti wá àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni Ṣimei sì lọ, ó sì mú àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ padà bọ̀ láti Gati.
Kũigua ũguo-rĩ, Shimei agĩtandĩka ndigiri yake, agĩthiĩ kwa Akishi kũu Gathu gwetha ngombo ciake. Nĩ ũndũ ũcio Shimei agĩthiĩ na agĩcookia ngombo ciake kuuma Gathu.
41 Nígbà tí a sì sọ fún Solomoni pé Ṣimei ti lọ láti Jerusalẹmu sí Gati, ó sì ti padà.
Rĩrĩa Solomoni eerirwo atĩ Shimei nĩoimĩte Jerusalemu agathiĩ Gathu na agacooka-rĩ,
42 Ọba pe Ṣimei lẹ́jọ́, ó wí fún un pé, “Ǹjẹ́ èmi kò ti mú ọ búra ní ti Olúwa, èmi sì ti kìlọ̀ fún ọ pé, ‘Ní ọjọ́ tí ìwọ bá kúrò láti lọ sí ibikíbi, kí o mọ̀ dájú pé ìwọ yóò kú.’ Nígbà náà ni ìwọ sì sọ fún mi pé, ‘Ohun tí ìwọ sọ dára. Èmi yóò ṣe ìgbọ́ràn.’
mũthamaki agĩtũmanĩra Shimei, akĩmwĩra atĩrĩ, “Githĩ ndiakwĩhĩtithirie na rĩĩtwa rĩa Jehova na ngĩgũkaania, ngĩkwĩra atĩrĩ, ‘Mũthenya ũrĩa ũkoimagara ũthiĩ handũ hangĩ, ũmenye kũna no ũgaakua’? Nawe hĩndĩ ĩyo ũkĩnjookeria atĩrĩ, ‘Ũguo woiga nĩ wega. Niĩ nĩngwathĩka.’
43 Èéṣe, nígbà náà tí ìwọ kò pa ìbúra Olúwa mọ́, àti kí o sì ṣe ìgbọ́ràn sí àṣẹ tí mo pa fún ọ?”
Rĩu-rĩ, nĩ kĩĩ gĩtũmĩte wage kũhingia mwĩhĩtwa waku harĩ Jehova, na wathĩkĩre watho ũrĩa ndaakũheire?”
44 Ọba sì tún wí fún Ṣimei pé, “Ìwọ mọ̀ ní ọkàn rẹ gbogbo búburú tí ìwọ ti ṣe sí Dafidi baba mi. Báyìí, Olúwa yóò san gbogbo ìṣe búburú rẹ padà fún ọ.
Ningĩ mũthamaki akĩĩra Shimei atĩrĩ, “Wee nĩũũĩ ngoro-inĩ yaku ũũru ũrĩa wothe wekire baba Daudi. Rĩu Jehova nĩegũtũma ũcookererwo nĩ ũũru waku.
45 Ṣùgbọ́n a ó sì bùkún fún Solomoni ọba, ìtẹ́ Dafidi yóò sì wà láìfòyà níwájú Olúwa títí láéláé.”
No Mũthamaki Solomoni nĩekũrathimwo, nakĩo gĩtĩ kĩa ũnene wa Daudi gĩtũũre gĩkĩgitĩre mbere ya Jehova nginya tene.”
46 Nígbà náà ni ọba pàṣẹ fún Benaiah ọmọ Jehoiada, ó sì jáde lọ, ó sì kọlu Ṣimei, ó sì pa á. Ìjọba náà sì wá fi ìdí múlẹ̀ ní ọwọ́ Solomoni.
Hĩndĩ ĩyo mũthamaki agĩatha Benaia mũrũ wa Jehoiada, nake agĩthiĩ akĩgũtha Shimei akĩmũũraga. Ũthamaki naguo ũkĩĩhaanda ũrũmĩte biũ moko-inĩ ma Solomoni.

< 1 Kings 2 >