< 1 Kings 18 >
1 Ó sì ṣe, lẹ́yìn ọjọ́ púpọ̀, ní ọdún kẹta, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Elijah wá pé, “Lọ, kí o sì fi ara rẹ̀ hàn fún Ahabu, èmi yóò sì rọ òjò sórí ilẹ̀.”
Thuutha wa ihinda iraaya, mwaka-inĩ wa gatatũ, kiugo kĩa Jehova gĩgĩkinyĩra Elija, akĩĩrwo atĩrĩ, “Ũkĩra ũthiĩ ũkeyonanie harĩ Ahabu, na thuutha wa ũguo nĩnguuria mbura bũrũri-inĩ ũyũ.”
2 Bẹ́ẹ̀ ni Elijah lọ fi ara rẹ̀ han Ahabu. Ìyàn ńlá sì mú ní Samaria,
Nĩ ũndũ ũcio Elija agĩthiĩ kwĩonania kũrĩ Ahabu. Na rĩrĩ, ngʼaragu yarĩ nene mũno kũu Samaria,
3 Ahabu sì ti pe Obadiah, ẹni tí ń ṣe olórí ilé rẹ̀. Obadiah sì bẹ̀rù Olúwa gidigidi.
nake Ahabu nĩatũmanĩire Obadia ũrĩa warĩ mũrũgamĩrĩri wa nyũmba yake ya ũthamaki. (Obadia aarĩ mwĩtĩkia weheanĩte mũno kũrĩ Jehova.
4 Nígbà tí Jesebeli sì ń pa àwọn wòlíì Olúwa kúrò, Obadiah sì mú ọgọ́rùn-ún wòlíì, ó sì fi wọ́n pamọ́ sínú ihò òkúta, àádọ́ta ní ihò kọ̀ọ̀kan, ó sì fi àkàrà pẹ̀lú omi bọ́ wọn.
Rĩrĩa Jezebeli ooragithagia anabii a Jehova, Obadia nĩoete anabii igana rĩmwe akamahitha ngurunga-inĩ igĩrĩ, o ĩmwe andũ mĩrongo ĩtano, na akamaheaga irio na maaĩ.)
5 Ahabu sì ti wí fún Obadiah pé, “Lọ sí gbogbo ilẹ̀ sí orísun omi gbogbo àti sí ilẹ̀ gbogbo. Bóyá àwa lè rí koríko láti gba àwọn ẹṣin àti àwọn ìbáaka là, kí a má bá à ṣòfò àwọn ẹranko pátápátá.”
Ahabu akĩĩra Obadia atĩrĩ, “Thiũrũrũka bũrũri wothe ũthiĩ ithima-inĩ ciothe, na ituamba-inĩ. No gũkorwo tuona handũ harĩ nyeki ĩngĩtũũria mbarathi na nyũmbũ muoyo, nĩguo tũtikoorage nyamũ o na ĩmwe iitũ.”
6 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì pín ilẹ̀ tí wọ́n fẹ́ dé láàrín ara wọn, Ahabu gba ọ̀nà kan lọ, Obadiah sì gba ọ̀nà mìíràn lọ.
Nĩ ũndũ ũcio makĩgayana bũrũri ũcio o eerĩ o mũndũ kũrĩa egũtuĩkanĩria, Ahabu agĩthiĩ mwena ũmwe na Obadia agĩthiĩ mwena ũrĩa ũngĩ.
7 Bí Obadiah sì ti ń rìn lọ, Elijah sì pàdé rẹ̀. Obadiah sì mọ̀ ọ́n, ó dojúbolẹ̀, ó sì wí pé, “Ǹjẹ́ ìwọ ni nítòótọ́, Elijah, olúwa mi?”
Rĩrĩa Obadia aathiiaga-rĩ, agĩtũngana na Elija. Obadia akĩmũmenya, akĩinamĩrĩra, agĩturumithia ũthiũ thĩ, akĩmũũria atĩrĩ, “Ti-itherũ nĩwe, mwathi wakwa Elija?”
8 Elijah sì dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, lọ kí o sọ fún olúwa rẹ pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’”
Nake agĩcookia atĩrĩ, “Ĩĩ nĩ niĩ, thiĩ ũkeere Ahabu mwathi waku atĩrĩ, ‘Elija arĩ gũkũ.’”
9 Obadiah sì béèrè pé, “Ẹ̀ṣẹ̀ kí ni mo ha dá tí ìwọ fi ń fi ìránṣẹ́ rẹ lé Ahabu lọ́wọ́ láti pa?
Obadia akĩmũũria atĩrĩ, “Kaĩ njĩkĩte ũũru ũrĩkũ, nĩguo ũũneane niĩ ndungata yaku moko-inĩ ma Ahabu njũragwo?
10 Mo mọ̀ dájú pé bí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti ń bẹ, kò sí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan tí olúwa mi kò ti rán ènìyàn lọ láti wò ọ́. Àti nígbà tí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan bá wí pé o kò sí, òun a sì mú kí wọ́n búra wí pé wọn kò rí ọ.
Ti-itheru o ta ũrĩa Jehova Ngai waku atũũraga muoyo-rĩ, gũtirĩ rũrĩrĩ kana ũthamaki mwathi wakwa atarĩ aatũmana ũgacario. Na rũrĩrĩ kana ũthamaki o wothe woiga ndũrĩ kuo, nake akehĩtithia andũ akuo moige na ma atĩ matikuonete.
11 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìwọ wí fún mi pé kí n lọ sọ́dọ̀ olúwa mi, kí n sì wí pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’
Na rĩu ũranjĩĩra thiĩ kũrĩ mwathi wakwa ngamwĩre atĩrĩ, ‘Elija arĩ gũkũ.’
12 Èmi kò sì mọ ibi tí ẹ̀mí Olúwa yóò gbé ọ lọ nígbà tí mo bá fi ọ́ sílẹ̀. Bí mo bá lọ, tí mo sì sọ fún Ahabu, tí kò sì rí ọ, òun a sì pa mí. Síbẹ̀ èmi ìránṣẹ́ rẹ bẹ̀rù Olúwa láti ìgbà èwe mi wá.
Niĩ ndiũĩ kũrĩa Roho wa Jehova angĩgũtwara twatigana nawe. Ingĩthiĩ njĩĩre Ahabu ũguo na acooke akwage-rĩ, nĩekũnjũraga. No niĩ ndungata yaku ndũire hooyaga Jehova kuuma ndĩ o mũnini.
13 Ṣé Olúwa mi kò ha ti gbọ́ ohun tí mo ṣe nígbà tí Jesebeli ń pa àwọn wòlíì Olúwa? Mo fi ọgọ́rùn-ún wòlíì Olúwa pamọ́ sínú ihò òkúta méjì, àràádọ́ta ní ọ̀kọ̀ọ̀kan, mo sì fi omi àti oúnjẹ bọ́ wọn.
Wee mwathi wakwa-rĩ, kaĩ ũtarĩ waigua ũrĩa ndeekire rĩrĩa Jezebeli ooragaga anabii a Jehova, ũrĩa ndaahithire anabii a Jehova igana rĩmwe ngurunga-inĩ igĩrĩ, o ĩmwe anabii mĩrongo ĩtano, na ngamaheaga irio na maaĩ?
14 Ìwọ sì sọ fún mi nísinsin yìí pé, kí n tọ olúwa mi lọ pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’ Òun a sì pa mí!”
Na rĩu ũranjĩĩra thiĩ kũrĩ mwathi wakwa ngamwĩre atĩrĩ, ‘Elija arĩ gũkũ.’ Nĩekũnjũraga!”
15 Elijah sì wí pé, “Bí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti wà, ẹni tí èmi ń sìn, nítòótọ́ èmi yóò fi ara mi hàn fún Ahabu lónìí.”
Elija akĩmwĩra atĩrĩ, “O ta ũrĩa Jehova Mwene-Hinya-Wothe ũrĩa ndungatagĩra atũũraga muoyo-rĩ, ti-itherũ nĩngwĩonithania niĩ mwene kũrĩ Ahabu ũmũthĩ.”
16 Bẹ́ẹ̀ ni Obadiah sì lọ láti pàdé Ahabu, ó sì sọ fún un, Ahabu sì lọ láti pàdé Elijah.
Nĩ ũndũ ũcio Obadia agĩthiĩ gũtũnga Ahabu akĩmwĩra ũhoro ũcio, nake Ahabu agĩthiĩ gũtũnga Elija.
17 Nígbà tí Ahabu sì rí Elijah, ó sì wí fún un pé, “Ṣé ìwọ nìyìí, ìwọ tí ń yọ Israẹli lẹ́nu?”
Rĩrĩa Ahabu onire Elija, akĩmwĩra atĩrĩ, “Wee nĩwe, wee mũnyariiri wa Isiraeli?”
18 Elijah sì dá a lóhùn pé, “Èmi kò yọ Israẹli lẹ́nu, bí kò ṣe ìwọ àti ilé baba rẹ. Ẹ ti kọ òfin Olúwa sílẹ̀, ẹ sì ń tọ Baali lẹ́yìn.
Elija akĩmũcookeria atĩrĩ, “Niĩ ndinyariirĩte Isiraeli. No wee na nyũmba ya thoguo, nĩ inyuĩ mwĩkĩte ũguo. Nĩmwatiganĩirie maathani ma Jehova na mũkĩrũmĩrĩra Baali.
19 Nísinsin yìí kó gbogbo Israẹli jọ láti pàdé mi lórí òkè Karmeli. Àti kí o sì mú àádọ́ta lé ní irinwó àwọn wòlíì Baali àti irinwó àwọn wòlíì òrìṣà Aṣerah tí wọ́n ń jẹun ní tábìlì Jesebeli.”
Rĩu tũmana andũ moime Isiraeli guothe, moke tũcemanie nao Kĩrĩma-inĩ gĩa Karimeli. Na ũrehe anabii arĩa a Baali magana mana ma mĩrongo ĩtano na anabii a Ashera magana mana, arĩa marĩĩagĩra metha-inĩ ya Jezebeli.”
20 Bẹ́ẹ̀ ni Ahabu ránṣẹ́ sí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ó sì kó àwọn wòlíì jọ sí orí òkè Karmeli.
Nĩ ũndũ ũcio Ahabu agĩtũmana Isiraeli guothe na agĩcookanĩrĩria anabii Kĩrĩma-inĩ gĩa Karimeli.
21 Elijah sì lọ síwájú gbogbo àwọn ènìyàn, ó sì wí pé, “Yóò ti pẹ́ tó tí ẹ̀yin yóò máa ṣiyèméjì? Bí Olúwa bá ni Ọlọ́run, ẹ máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, ṣùgbọ́n bí Baali bá ni Ọlọ́run, ẹ máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.” Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà kò sì wí ohun kan.
Elija agĩthiĩ mbere ya andũ akĩmeera atĩrĩ, “Nĩ nginya rĩ mũgũtũũra mũthanganagĩria njĩra igĩrĩ? Angĩkorwo Jehova nĩwe Ngai-rĩ, mũrũmĩrĩrei, no angĩkorwo Baali nĩwe Ngai-rĩ, mũkĩmũrũmĩrĩre we.” No andũ acio matiamũcookeirie ũndũ o na ũmwe.
22 Nígbà náà ni Elijah wí fún wọn pé, “Èmi nìkan ṣoṣo ni ó kù ní wòlíì Olúwa, ṣùgbọ́n, àádọ́ta lé ní irinwó ni wòlíì Baali.
Hĩndĩ ĩyo Elija akĩmeera atĩrĩ, “Niĩ nyiki no niĩ ndigĩtwo ndĩ mũnabii wa Jehova, no Baali arĩ na anabii magana mana ma mĩrongo ĩtano.
23 Ẹ fún wa ní ẹgbọrọ akọ màlúù méjì. Jẹ́ kí wọn kí ó sì yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara wọn, kí wọn kí ó sì gé e sí wẹ́wẹ́, kí wọn kí ó sì tò ó sí orí igi, kí wọn kí ó má ṣe fi iná sí i. Èmi yóò sì tún ẹgbọrọ akọ màlúù kejì ṣe, èmi yóò sì tò ó sórí igi, èmi kì yóò sì fi iná sí i.
Tũreherei ndegwa igĩrĩ. Reke methuurĩre ndegwa ĩmwe, na mamĩtinangie icunjĩ, macooke mamĩigĩrĩre ngũ igũrũ, no matigaakie mwaki. Na niĩ haarĩrie ndegwa ĩyo ĩngĩ, na ndĩmĩigĩrĩre ngũ igũrũ, na ndigwakia mwaki.
24 Nígbà náà ẹ ó sì ké pe orúkọ àwọn Ọlọ́run yín, èmi yóò sì ké pe orúkọ Olúwa. Ọlọ́run náà tí ó fi iná dáhùn, òun ni Ọlọ́run.” Nígbà náà ni gbogbo àwọn ènìyàn náà sì wí pé, “Ohun tí ìwọ sọ dára.”
Ningĩ mũcooke mũkaĩre rĩĩtwa rĩa ngai wanyu, na niĩ ngaĩre rĩĩtwa rĩa Jehova. Na ngai ũrĩa ũgũcookia mahooya na ũndũ wa kũrehe mwaki-rĩ, ũcio nĩwe Ngai.” Nao andũ othe makiuga atĩrĩ, “Ũguo woiga nĩ wega.”
25 Elijah sì wí fún àwọn wòlíì Baali wí pé, “Ẹ yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara yín, kí ẹ sì tètè kọ́ ṣe é, nítorí ẹ̀yin pọ̀. Ẹ ké pe orúkọ àwọn ọlọ́run yín, ṣùgbọ́n ẹ má ṣe fi iná sí i.”
Elija akĩĩra anabii a Baali atĩrĩ, “Thuurai ndegwa ĩmwe, mwambĩrĩrie kũmĩhaarĩria, tondũ nĩ inyuĩ mũkĩrĩ aingĩ. Mũkaĩre rĩĩtwa rĩa ngai wanyu, na mũtigaakie mwaki.”
26 Nígbà náà ni wọ́n sì mú ẹgbọrọ akọ màlúù náà, tí a ti fi fún wọn, wọ́n sì ṣe é. Nígbà náà ni wọ́n sì ké pe orúkọ Baali láti òwúrọ̀ títí di ọ̀sán gangan wí pé, “Baali! Dá wa lóhùn!” Wọ́n sì ń kégbe. Ṣùgbọ́n kò sí ìdáhùn; kò sí ẹnìkan tí ó sì dáhùn. Wọ́n sì jó yí pẹpẹ náà ká, èyí tí wọ́n tẹ́.
Tondũ ũcio makĩoya ndegwa ĩrĩa maaheirwo makĩmĩhaarĩria. Magĩkaĩra rĩĩtwa rĩa Baali kuuma rũciinĩ nginya mĩaraho, makĩanĩrĩra makiugaga atĩrĩ, “Wee Baali tũigue!” No matiigana gũcookerio, tondũ gũtiarĩ mũndũ wa kũmacookeria. Nao makĩrũgarũga, makĩinaga, na magĩthiũrũrũkaga kĩgongona kĩu maathondekete.
27 Ní ọ̀sán gangan, Elijah bẹ̀rẹ̀ sí ń fi wọ́n ṣe ẹlẹ́yà ó sì wí pé, “Ẹ kígbe lóhùn rara Ọlọ́run sá à ni òun! Bóyá ó ń ṣe àṣàrò, tàbí kò ráyè, tàbí ó re àjò. Bóyá ó sùn, ó yẹ kí a jí i.”
Mĩaraho yakinya-rĩ, Elija akĩambĩrĩria kũmanyũrũria, akĩmeera atĩrĩ, “Anĩrĩrai mũno! Ti-itherũ we akĩrĩ ngai! No gũkorwo e na maũndũ areciiria, kana e na mĩhangʼo, kana agathiĩ rũgendo. No gũkorwo nĩakomete na no nginya okĩrio.”
28 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì kígbe lóhùn rara, wọ́n sì fi ọ̀bẹ àti ọ̀kọ̀ ya ara wọn gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn, títí tí ẹ̀jẹ̀ fi tú jáde ní ara wọn.
Tondũ ũcio makĩanĩrĩra mũno, na magĩĩtemanga na hiũ cia njora na matimũ, nginya thakame ĩkĩambĩrĩria kũnyũrũrũka, tondũ ũcio nĩguo warĩ mũtugo wao.
29 Nígbà tí ọjọ́ yẹ àtàrí, wọ́n sì ń fi òmùgọ̀ sọtẹ́lẹ̀ títí di àkókò ìrúbọ àṣálẹ́, ṣùgbọ́n kò sí ohùn, kò sì ṣí ìdáhùn, kò sì ṣí ẹni tí ó kà á sí.
Na rĩrĩ, mĩaraho yahĩtũka-rĩ, magĩthiĩ o na mbere na ũrathi wao wa matũhũhũ nginya ihinda rĩa igongona rĩa hwaĩ-inĩ. No gũtiarĩ na macookio, na gũtiarĩ o na ũmwe wa kũmacookeria, na gũtiarĩ o na ũmwe wa kũmarũmbũiya.
30 Nígbà náà ni Elijah wí fún gbogbo àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ súnmọ́ mi.” Wọ́n sì súnmọ́ ọn, ó sì tún pẹpẹ Olúwa tí ó ti wó lulẹ̀ ṣe.
Ningĩ Elija akĩĩra andũ othe atĩrĩ, “Okokaai hakuhĩ na niĩ” Nao andũ acio magĩthiĩ hakuhĩ nake. Elija agĩcookereria kĩgongona kĩa Jehova tondũ nĩgĩathũkangĩtio.
31 Elijah sì mú òkúta méjìlá, ọ̀kọ̀ọ̀kan fún ẹ̀yà ọmọ Jakọbu kan, ẹni tí ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ wá wí pé, “Israẹli ni orúkọ rẹ̀ yóò máa jẹ́.”
Elija akĩoya mahiga ikũmi na meerĩ kũringana na mĩhĩrĩga ya njiarwa cia Jakubu, ũrĩa wakinyĩirwo nĩ kiugo kĩa Jehova akĩĩrwo atĩrĩ, “Ũrĩĩtagwo Isiraeli.”
32 Ó sì tẹ́ pẹpẹ pẹ̀lú àwọn òkúta wọ̀nyí ní orúkọ Olúwa, ó sì wa yàrá yí pẹpẹ náà ká, tí ó lè gba ìwọ̀n òsùwọ̀n irúgbìn méjì.
Nake agĩaka kĩgongona na mahiga macio rĩĩtwa-inĩ rĩa Jehova, na akĩenja mũtaro mwariĩ ũngĩiganĩra ibaba igĩrĩ cia mbegũ, ũkĩrigiicĩria kĩgongona kĩu.
33 Ó sì to igi náà dáradára, ó sì ké ẹgbọrọ akọ màlúù náà wẹ́wẹ́, ó sì tò ó sórí igi. Nígbà náà ni ó sì wí fún wọn wí pé, “Ẹ fi omi kún ìkòkò mẹ́rin, kí ẹ sì tu sórí ẹbọ sísun àti sórí igi náà.”
Akĩara ngũ, agĩtinangia ndegwa ĩyo icunjĩ, na akĩmĩigĩrĩra ngũ igũrũ. Ningĩ akĩmeera atĩrĩ, “Iyũriai mĩtũngi ĩna mĩnene maaĩ, mũmaitĩrĩrie igũrũ rĩa iruta na igũrũ rĩa ngũ.”
34 Ó sì wí pe, “Ẹ ṣe é ní ìgbà kejì.” Wọ́n sì ṣe é ní ìgbà kejì. Ó sì tún wí pé, “Ṣe é ní ìgbà kẹta.”
Akĩmeera atĩrĩ, “Ĩkai ũguo rĩngĩ,” nao magĩĩka o ro ũguo. Akĩmaatha akĩmeera atĩrĩ, “Ĩkai ũguo riita rĩa gatatũ,” nao magĩĩka ũguo riita rĩa gatatũ.
35 Omi náà sì sàn yí pẹpẹ náà ká, ó sì fi omi kún yàrá náà pẹ̀lú.
Namo maaĩ macio magĩtherera gũthiũrũrũka kĩgongona, o na makĩiyũra mũtaro.
36 Ó sì ṣe, ní ìrúbọ àṣálẹ́, wòlíì Elijah sì súnmọ́ tòsí, ó sì gbàdúrà wí pé, “Olúwa, Ọlọ́run Abrahamu, Isaaki àti Israẹli, jẹ́ kí ó di mí mọ̀ lónìí pé ìwọ ni Ọlọ́run ní Israẹli àti pé èmi ni ìránṣẹ́ rẹ, àti pé mo ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí nípa àṣẹ rẹ.
Ihinda rĩa kũruta igongona-rĩ, mũnabii Elija agĩokooka hau mbere na akĩhooya atĩrĩ: “Wee Jehova Ngai wa Iburahĩmu, na Isaaka, na Isiraeli, reke kũmenyeke ũmũthĩ atĩ Wee nĩwe Ngai thĩinĩ wa Isiraeli, na ningĩ atĩ niĩ ndĩ ndungata yaku na njĩkĩte maũndũ maya mothe o ta ũrĩa ũnjathĩte.
37 Gbọ́ ti èmi, Olúwa, gbọ́ ti èmi, kí àwọn ènìyàn wọ̀nyí lè mọ̀ pé ìwọ Olúwa ni Ọlọ́run àti pé ìwọ tún yí ọkàn wọn padà.”
Njigua, Wee Jehova, njigua, nĩgeetha andũ aya mamenye atĩ Wee Jehova nĩwe Ngai, na atĩ nĩũkũgarũra ngoro ciao igũcookerere.”
38 Nígbà náà ni iná Olúwa bọ́ sílẹ̀, ó sì sun ẹbọ sísun náà àti igi, àti àwọn òkúta, àti erùpẹ̀, ó sì tún lá omi tí ń bẹ nínú yàrá náà.
Naguo mwaki wa Jehova ũgĩikũrũka ũgĩcina igongona, na ngũ icio, na mahiga, o na tĩĩri, ningĩ ũkĩngʼaria maaĩ marĩa maarĩ mũtaro.
39 Nígbà tí gbogbo àwọn ènìyàn sì rí èyí, wọ́n da ojú wọn bolẹ̀, wọ́n sì kígbe pé, “Olúwa, òun ni Ọlọ́run! Olúwa, òun ni Ọlọ́run!”
Hĩndĩ ĩrĩa andũ othe moonire ũndũ ũcio, makĩgũa, magĩturumithia mothiũ thĩ, makĩanĩrĩra makiuga atĩrĩ, “Jehova nĩwe Ngai! Jehova nĩwe Ngai!”
40 Nígbà náà ni Elijah sì pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ mú àwọn wòlíì Baali. Ẹ má ṣe jẹ́ kí ọ̀kan nínú wọn kí ó sálọ!” Wọ́n sì mú wọn, Elijah sì mú wọn sọ̀kalẹ̀ sí àfonífojì Kiṣoni, ó sì pa wọ́n níbẹ̀.
Nake Elija agĩatha andũ acio akĩmeera atĩrĩ, “Nyiitai anabii acio a Baali. Mũtikareke o na ũmwe wao oore!” Nao makĩmanyiita, nake Elija akiuga maikũrũkio gĩtuamba-inĩ gĩa Kishoni mooragĩrwo kuo.
41 Elijah sì wí fún Ahabu pé, “Lọ, jẹ, kí o sì mu, nítorí ìró ọ̀pọ̀lọpọ̀ òjò ń bọ̀.”
Nake Elija akĩĩra Ahabu atĩrĩ, “Thiĩ ũrĩe na ũnyue tondũ kũrĩ na mũhũyũko wa mbura nene.”
42 Bẹ́ẹ̀ ni Ahabu gòkè lọ láti jẹ àti láti mu. Ṣùgbọ́n Elijah gun orí òkè Karmeli lọ ó sì tẹríba, ó sì fi ojú rẹ̀ sí agbede-méjì eékún rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio Ahabu agĩthiĩ, akĩrĩa na akĩnyua, nowe Elija akĩambata Kĩrĩma igũrũ gĩa Karimeli, akĩinamĩrĩra nginya thĩ, agĩtoonyia mũtwe gatagatĩ ka maru make.
43 Ó sì wí fún ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé, “Lọ, kí o sì wo ìhà Òkun, òun sì gòkè lọ, ó sì wò.” Ó sì wí pé, “Kò sí nǹkan níbẹ̀.” Ó sì wí pé, “Tún lọ nígbà méje.”
Nake akĩĩra ndungata yake atĩrĩ, “Thiĩ ũcũthĩrĩrie iria-inĩ,” nayo ĩkĩambata ĩgĩcũthĩrĩria. Ĩkiuga atĩrĩ, “Hatirĩ kĩndũ.” Nake Elija akĩmĩĩra ĩcooke ho rĩngĩ na rĩngĩ maita mũgwanja.
44 Nígbà keje, ìránṣẹ́ náà sì wí pé, “Àwọsánmọ̀ kékeré kan dìde láti inú Òkun, gẹ́gẹ́ bí ọwọ́ ènìyàn.” Elijah sì wí pé, “Lọ, kí o sọ fún Ahabu pé, ‘Di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ, kí o sì sọ̀kalẹ̀ lọ, kí òjò ó má ba à dá ọ dúró.’”
Riita rĩa mũgwanja ndungata ĩyo ĩkĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩ harĩ na gatu kanini kaigana guoko kwa mũndũ karoimĩra kuuma iria-inĩ.” Nĩ ũndũ ũcio Elija akĩmĩĩra atĩrĩ, “Thiĩ ũkeere Ahabu atĩrĩ, ‘Ohania ngaari yaku ya ita, ũikũrũke ũtanahingĩrĩrio nĩ mbura.’”
45 Ó sì ṣe, nígbà díẹ̀ sí i, ọ̀run sì ṣú fún àwọsánmọ̀, ìjì sì dìde, òjò púpọ̀ sì rọ̀, Ahabu sì gun kẹ̀kẹ́ lọ sí Jesreeli.
Hĩndĩ ĩyo igũrũ rĩgĩthimba nĩ ũndũ wa matu, na rũhuho rũkĩhurutana, gũkiura mbura nene, nake Ahabu akĩhaica ngaari yake agĩthiĩ Jezireeli.
46 Agbára Olúwa sì ń bẹ lára Elijah; ó sì di àmùrè ẹ̀gbẹ́ rẹ, ó sì sáré níwájú Ahabu títí dé Jesreeli.
Naguo hinya wa Jehova ũgĩũka igũrũ rĩa Elija, akĩĩhotora akĩrũmia nguo yake na mũcibi, akĩhanyũka e mbere ya Ahabu, o nginya Jezireeli.