< 1 Kings 18 >

1 Ó sì ṣe, lẹ́yìn ọjọ́ púpọ̀, ní ọdún kẹta, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Elijah wá pé, “Lọ, kí o sì fi ara rẹ̀ hàn fún Ahabu, èmi yóò sì rọ òjò sórí ilẹ̀.”
Khohnin muep a koe phoeikah a kum thum dongah BOEIPA ol te Elijah taengla pawk tih, “Cet lamtah Ahab taengah phoe pah, diklai hman ah khotlan kan paek bitni,” a ti nah.
2 Bẹ́ẹ̀ ni Elijah lọ fi ara rẹ̀ han Ahabu. Ìyàn ńlá sì mú ní Samaria,
Te dongah Elijah te Ahab taengah phoe hamla cet. Te vaengah Samaria ah khokha tlung.
3 Ahabu sì ti pe Obadiah, ẹni tí ń ṣe olórí ilé rẹ̀. Obadiah sì bẹ̀rù Olúwa gidigidi.
Te dongah Ahab loh im kah Obadiah te a khue. Te vaengah Obadiah tah BOEIPA bahoeng aka rhih la om.
4 Nígbà tí Jesebeli sì ń pa àwọn wòlíì Olúwa kúrò, Obadiah sì mú ọgọ́rùn-ún wòlíì, ó sì fi wọ́n pamọ́ sínú ihò òkúta, àádọ́ta ní ihò kọ̀ọ̀kan, ó sì fi àkàrà pẹ̀lú omi bọ́ wọn.
BOEIPA kah tonghma rhoek te Jezebel loh a thup ham a om vaengah khaw Obadiah loh tonghma yakhat te a khuen tih amih te lungko pakhat ah hlang sawmnga rhip a thuh. Te phoeiah amih te buh neh tui neh a cangbam.
5 Ahabu sì ti wí fún Obadiah pé, “Lọ sí gbogbo ilẹ̀ sí orísun omi gbogbo àti sí ilẹ̀ gbogbo. Bóyá àwa lè rí koríko láti gba àwọn ẹṣin àti àwọn ìbáaka là, kí a má bá à ṣòfò àwọn ẹranko pátápátá.”
Ahab loh Obadiah te, “Khohmuen kah tuisih tui boeih neh soklong boeih te paan lamtah sulrham khaw m'hmuh khaming. Te daengah ni marhang neh muli-marhang n'hing sak vetih rhamsa khaw n'hlong pawt eh?,” a ti nah.
6 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì pín ilẹ̀ tí wọ́n fẹ́ dé láàrín ara wọn, Ahabu gba ọ̀nà kan lọ, Obadiah sì gba ọ̀nà mìíràn lọ.
Khohmuen tom til hamla amamih tael uh thae. Ahab te amah bueng longpuei pakhat ah cet tih Obadiah khaw amah bueng longpuei pakhat ah cet.
7 Bí Obadiah sì ti ń rìn lọ, Elijah sì pàdé rẹ̀. Obadiah sì mọ̀ ọ́n, ó dojúbolẹ̀, ó sì wí pé, “Ǹjẹ́ ìwọ ni nítòótọ́, Elijah, olúwa mi?”
Obadiah te longpueng ah a om vaengah anih te Elijah loh tapkhoeh a doe. Anih te a hmat coeng dongah a maelhmai dongah buluk tih, “Ka boeipa Elijah nang a te?” a ti nah.
8 Elijah sì dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, lọ kí o sọ fún olúwa rẹ pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’”
Te phoeiah Obadiah te, “Kai ue, cet lamtah na boeipa taengah, 'Elijah ke,’ ti nah,” a ti nah.
9 Obadiah sì béèrè pé, “Ẹ̀ṣẹ̀ kí ni mo ha dá tí ìwọ fi ń fi ìránṣẹ́ rẹ lé Ahabu lọ́wọ́ láti pa?
Te phoeiah, “Kai duek sak hamla Ahab kut ah na sal nan tloeng ham khaw nang balae ka tholh?”
10 Mo mọ̀ dájú pé bí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti ń bẹ, kò sí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan tí olúwa mi kò ti rán ènìyàn lọ láti wò ọ́. Àti nígbà tí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan bá wí pé o kò sí, òun a sì mú kí wọ́n búra wí pé wọn kò rí ọ.
Nang kah Pathen BOEIPA kah hingnah dongah, nang tlap pahoi ham ka boei loh n'tueih pawh, namtom neh ram om voel pawh. Nang m'hmuh pawt te, “Om pawh,” a ti uh vaengah ram neh namtom khaw a toemngam coeng.
11 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìwọ wí fún mi pé kí n lọ sọ́dọ̀ olúwa mi, kí n sì wí pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’
Tedae nang loh, 'Na boei taengah cet lamtah 'Elijah he,’ ti nah,’ na ti mai.
12 Èmi kò sì mọ ibi tí ẹ̀mí Olúwa yóò gbé ọ lọ nígbà tí mo bá fi ọ́ sílẹ̀. Bí mo bá lọ, tí mo sì sọ fún Ahabu, tí kò sì rí ọ, òun a sì pa mí. Síbẹ̀ èmi ìránṣẹ́ rẹ bẹ̀rù Olúwa láti ìgbà èwe mi wá.
Kai he nang taeng lamloh ka nong tih BOEIPA kah Mueihla loh ka ming nah pawt la nang n'khuen khaming. Ahab taengla puen ham ka caeh vaengah nang m'hmu pawt mai koinih kai n'ngawn ni ta. Tedae na sal he ka camoe lamloh BOEIPA te ka rhih ngawn ne.
13 Ṣé Olúwa mi kò ha ti gbọ́ ohun tí mo ṣe nígbà tí Jesebeli ń pa àwọn wòlíì Olúwa? Mo fi ọgọ́rùn-ún wòlíì Olúwa pamọ́ sínú ihò òkúta méjì, àràádọ́ta ní ọ̀kọ̀ọ̀kan, mo sì fi omi àti oúnjẹ bọ́ wọn.
Jezebel loh BOEIPA kah tonghma rhoek a ngawn vaengah ka saii te ka boeipa taengla ha puen pawt nim? BOEIPA tonghma hlang yakhat te lungko pakhat ah hlang sawmnga, sawmnga rhip ka thuh tih amih te buh neh tui neh ka cangbam coeng.
14 Ìwọ sì sọ fún mi nísinsin yìí pé, kí n tọ olúwa mi lọ pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’ Òun a sì pa mí!”
Tedae tahae ah, “Cet lamtah na boei rhoek taengah 'Elijah he 'ti nah na ti vaengah kai n'ngawn pawn ni,” a ti nah.
15 Elijah sì wí pé, “Bí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti wà, ẹni tí èmi ń sìn, nítòótọ́ èmi yóò fi ara mi hàn fún Ahabu lónìí.”
Elijah loh, “Caempuei BOEIPA kah hingnah bangla amah mikhmuh ah ka pai coeng. Tihnin ah Ahab taengla ka phoe kuekluek ni,” a ti nah.
16 Bẹ́ẹ̀ ni Obadiah sì lọ láti pàdé Ahabu, ó sì sọ fún un, Ahabu sì lọ láti pàdé Elijah.
Obadiah te Ahab doe hamla cet tih a taengah a puen pah. Te dongah Ahab khaw Elijah doe hamla cet.
17 Nígbà tí Ahabu sì rí Elijah, ó sì wí fún un pé, “Ṣé ìwọ nìyìí, ìwọ tí ń yọ Israẹli lẹ́nu?”
Ahab loh Elijah te a hmuh vaengah Ahab loh anih te, “Israel aka lawn te nang nama?” a ti nah.
18 Elijah sì dá a lóhùn pé, “Èmi kò yọ Israẹli lẹ́nu, bí kò ṣe ìwọ àti ilé baba rẹ. Ẹ ti kọ òfin Olúwa sílẹ̀, ẹ sì ń tọ Baali lẹ́yìn.
Te vaengah, “Israel te ka lawn pawt tih namah neh na pa imkhui loh na lawn. BOEIPA olpaek te na toeng uh tih Baal hnukah na pongpa uh.
19 Nísinsin yìí kó gbogbo Israẹli jọ láti pàdé mi lórí òkè Karmeli. Àti kí o sì mú àádọ́ta lé ní irinwó àwọn wòlíì Baali àti irinwó àwọn wòlíì òrìṣà Aṣerah tí wọ́n ń jẹun ní tábìlì Jesebeli.”
Karmel tlang la kamah taengah Israel pum neh Baal tonghma rhoek ya li sawmnga, Jezebel caboei aka vael Asherah tonghma ya li te khue lamtah coi laeh,” a ti nah.
20 Bẹ́ẹ̀ ni Ahabu ránṣẹ́ sí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ó sì kó àwọn wòlíì jọ sí orí òkè Karmeli.
Ahab loh Israel ca boeih te a tah tih tonghma rhoek neh Karmel tlang ah a tingtun sak.
21 Elijah sì lọ síwájú gbogbo àwọn ènìyàn, ó sì wí pé, “Yóò ti pẹ́ tó tí ẹ̀yin yóò máa ṣiyèméjì? Bí Olúwa bá ni Ọlọ́run, ẹ máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, ṣùgbọ́n bí Baali bá ni Ọlọ́run, ẹ máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.” Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà kò sì wí ohun kan.
Te vaengah Elijah te pilnam pum taengla mop tih, “Pomnah panit dongah ah me hil nim na ingang uh ve? Pathen Yahweh kah van atah a hnukah rhep pongpa uh. Tedae Baal kah van atah anih hnukah rhep pongpa uh,” a ti nah vaengah pilnam loh anih te ol doo pawh.
22 Nígbà náà ni Elijah wí fún wọn pé, “Èmi nìkan ṣoṣo ni ó kù ní wòlíì Olúwa, ṣùgbọ́n, àádọ́ta lé ní irinwó ni wòlíì Baali.
Elijah loh pilnam taengah, “Kai he kamah bueng ni BOEIPA kah tonghma la ka cul coeng. Tedae Baal kah tonghma rhoek tah hlang ya li sawmnga lo.
23 Ẹ fún wa ní ẹgbọrọ akọ màlúù méjì. Jẹ́ kí wọn kí ó sì yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara wọn, kí wọn kí ó sì gé e sí wẹ́wẹ́, kí wọn kí ó sì tò ó sí orí igi, kí wọn kí ó má ṣe fi iná sí i. Èmi yóò sì tún ẹgbọrọ akọ màlúù kejì ṣe, èmi yóò sì tò ó sórí igi, èmi kì yóò sì fi iná sí i.
Kaimih ham vaito pumnit m'pae uh laeh. Vaito pumat te amih ham coelh uh saeh lamtah top uh saeh. Te phoeiah thing soah tloeng uh saeh lamtah hmai toih uh boel saeh. Kai khaw vaito pakhat te ka ngawn vetih thing soah ka tloeng van ni, tedae hmai toih van mahpawh.
24 Nígbà náà ẹ ó sì ké pe orúkọ àwọn Ọlọ́run yín, èmi yóò sì ké pe orúkọ Olúwa. Ọlọ́run náà tí ó fi iná dáhùn, òun ni Ọlọ́run.” Nígbà náà ni gbogbo àwọn ènìyàn náà sì wí pé, “Ohun tí ìwọ sọ dára.”
Na pathen rhoek kah ming te khue uh lamtah kai khaw Yahweh ming te ka khue eh. Tedae hmai neh aka doo Pathen te tah Pathen tang la om ni,” a ti nah. Te vaengah pilnam pum loh a doo tih, “Ol then ni,” a ti uh.
25 Elijah sì wí fún àwọn wòlíì Baali wí pé, “Ẹ yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara yín, kí ẹ sì tètè kọ́ ṣe é, nítorí ẹ̀yin pọ̀. Ẹ ké pe orúkọ àwọn ọlọ́run yín, ṣùgbọ́n ẹ má ṣe fi iná sí i.”
Te phoeiah Elijah loh Baal tonghma rhoek taengah, “Namamih ham vaito pumat ah tuek uh. Na yet uh dongah lamhma la saii lamtah na pathen ming te khue uh. Tedae hmai tah toih uh boeh,” a ti nah.
26 Nígbà náà ni wọ́n sì mú ẹgbọrọ akọ màlúù náà, tí a ti fi fún wọn, wọ́n sì ṣe é. Nígbà náà ni wọ́n sì ké pe orúkọ Baali láti òwúrọ̀ títí di ọ̀sán gangan wí pé, “Baali! Dá wa lóhùn!” Wọ́n sì ń kégbe. Ṣùgbọ́n kò sí ìdáhùn; kò sí ẹnìkan tí ó sì dáhùn. Wọ́n sì jó yí pẹpẹ náà ká, èyí tí wọ́n tẹ́.
Te dongah vaito a khuen uh te amih taengah a paek uh tih a ngawn uh. Baal ming te mincang lamloh khothun hil a khue uh. “Baal, kaimih n'doo lah,” a ti uh. Tedae ol a om pawt tih a doo pawt dongah a saii hmueihtuk taengah ingang uh.
27 Ní ọ̀sán gangan, Elijah bẹ̀rẹ̀ sí ń fi wọ́n ṣe ẹlẹ́yà ó sì wí pé, “Ẹ kígbe lóhùn rara Ọlọ́run sá à ni òun! Bóyá ó ń ṣe àṣàrò, tàbí kò ráyè, tàbí ó re àjò. Bóyá ó sùn, ó yẹ kí a jí i.”
Khothun a pha vaengah Elijah tah amih taengah omsaa tih, “Ol a len la pang uh, na pathen te kohuetnah om khaming, anih te bitok khaming, anih te yiin mai khaming, anih te muelh ip mai khaming, haeng uh dae,” a ti nah.
28 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì kígbe lóhùn rara, wọ́n sì fi ọ̀bẹ àti ọ̀kọ̀ ya ara wọn gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn, títí tí ẹ̀jẹ̀ fi tú jáde ní ara wọn.
Te dongah ol a len la pang uh. Amih kah khosing bangla a pum dongkah thii a long hil cunghang neh cai neh a hlap uh.
29 Nígbà tí ọjọ́ yẹ àtàrí, wọ́n sì ń fi òmùgọ̀ sọtẹ́lẹ̀ títí di àkókò ìrúbọ àṣálẹ́, ṣùgbọ́n kò sí ohùn, kò sì ṣí ìdáhùn, kò sì ṣí ẹni tí ó kà á sí.
Khothun a poeng tih khocang nawn hil khaw tonghma uh. Tedae ol om pawt tih a doo voel pawt dongah hnatungnah khaw om pawh.
30 Nígbà náà ni Elijah wí fún gbogbo àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ súnmọ́ mi.” Wọ́n sì súnmọ́ ọn, ó sì tún pẹpẹ Olúwa tí ó ti wó lulẹ̀ ṣe.
Elijah loh pilnam boeih te, “Kai taengla ha thoeih uh,” a ti nah. Te dongah pilnam pum te anih taengla thoeih uh tih BOEIPA kah hmueihtuk a koengloeng tangtae te a tlaih uh.
31 Elijah sì mú òkúta méjìlá, ọ̀kọ̀ọ̀kan fún ẹ̀yà ọmọ Jakọbu kan, ẹni tí ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ wá wí pé, “Israẹli ni orúkọ rẹ̀ yóò máa jẹ́.”
A taengah BOEIPA ol pawk tih, “Na ming he Israel la om saeh,” a ti nah vanbangla Jakob ca rhoek kah koca tarhing ah Elijah loh lungto hlai nit a loh.
32 Ó sì tẹ́ pẹpẹ pẹ̀lú àwọn òkúta wọ̀nyí ní orúkọ Olúwa, ó sì wa yàrá yí pẹpẹ náà ká, tí ó lè gba ìwọ̀n òsùwọ̀n irúgbìn méjì.
BOEIPA ming neh hmueihtuk lung te koep a khoeng tih hmueihtuk kaep ah cangti sum nit cet la tuilong a saii.
33 Ó sì to igi náà dáradára, ó sì ké ẹgbọrọ akọ màlúù náà wẹ́wẹ́, ó sì tò ó sórí igi. Nígbà náà ni ó sì wí fún wọn wí pé, “Ẹ fi omi kún ìkòkò mẹ́rin, kí ẹ sì tu sórí ẹbọ sísun àti sórí igi náà.”
Thing te a hawn phoeiah vaito te a top tih thing soah a tloeng.
34 Ó sì wí pe, “Ẹ ṣe é ní ìgbà kejì.” Wọ́n sì ṣe é ní ìgbà kejì. Ó sì tún wí pé, “Ṣe é ní ìgbà kẹta.”
Te phoeiah amrhaeng pali dongah tui than uh lamtah hmueihhlutnah soah khaw, thing soah khaw, bueih uh,” a ti nah. Te phoeiah, “Talh dae,” a ti nah tih a talh uh. Te phoeiah, “Voei thum,” a ti nah tih voei thum a saiiuh.
35 Omi náà sì sàn yí pẹpẹ náà ká, ó sì fi omi kún yàrá náà pẹ̀lú.
Tui te hmueihtuk kaepvai la long tih tuilong ah pataeng tui bae.
36 Ó sì ṣe, ní ìrúbọ àṣálẹ́, wòlíì Elijah sì súnmọ́ tòsí, ó sì gbàdúrà wí pé, “Olúwa, Ọlọ́run Abrahamu, Isaaki àti Israẹli, jẹ́ kí ó di mí mọ̀ lónìí pé ìwọ ni Ọlọ́run ní Israẹli àti pé èmi ni ìránṣẹ́ rẹ, àti pé mo ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí nípa àṣẹ rẹ.
Khocang nawn tue a pha vaengah tonghma Elijah te thoeih tih, “Abraham, Isaak neh Israel Pathen Yahweh aw, tihnin ah namah te Pathen la Israel khuiah m'ming saeh. Na ol vanbangla kai he namah kah sal ni. Na ol bangla he hno cungkuem he ka saii.
37 Gbọ́ ti èmi, Olúwa, gbọ́ ti èmi, kí àwọn ènìyàn wọ̀nyí lè mọ̀ pé ìwọ Olúwa ni Ọlọ́run àti pé ìwọ tún yí ọkàn wọn padà.”
Kai he n'doo lah, BOEIPA aw kai n'doo lah. Te daengah ni he pilnam loh nang Yahweh Pathen neh namah loh a hnuk la amih lungbuei na mael sak ham khaw a ming uh eh,” a ti nah.
38 Nígbà náà ni iná Olúwa bọ́ sílẹ̀, ó sì sun ẹbọ sísun náà àti igi, àti àwọn òkúta, àti erùpẹ̀, ó sì tún lá omi tí ń bẹ nínú yàrá náà.
Te vaengah BOEIPA kah hmai suntla tih hmueihhlutnah neh thing khaw, lungto neh laipi khaw a hlawp tih tuilong kah tui te a laeh.
39 Nígbà tí gbogbo àwọn ènìyàn sì rí èyí, wọ́n da ojú wọn bolẹ̀, wọ́n sì kígbe pé, “Olúwa, òun ni Ọlọ́run! Olúwa, òun ni Ọlọ́run!”
Pilnam cungkuem loh a hmuh vaengah a maelhmai dongla buluk uh tih, “Yahweh amah tah Pathen ni, Yahweh amah tah Pathen ni,” a ti uh.
40 Nígbà náà ni Elijah sì pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ mú àwọn wòlíì Baali. Ẹ má ṣe jẹ́ kí ọ̀kan nínú wọn kí ó sálọ!” Wọ́n sì mú wọn, Elijah sì mú wọn sọ̀kalẹ̀ sí àfonífojì Kiṣoni, ó sì pa wọ́n níbẹ̀.
Elijah loh amih taengah, “Baal tonghma rhoek te tu uh, amih hlang te loeih boel saeh,” a ti nah. Amih te a tuuk uh phoeiah tah Elijah loh Kishon soklong la a suntlak puei tih pahoi a ngawn.
41 Elijah sì wí fún Ahabu pé, “Lọ, jẹ, kí o sì mu, nítorí ìró ọ̀pọ̀lọpọ̀ òjò ń bọ̀.”
Te phoeiah Elijah loh Ahab te, “Khonal tlanthim ol halo coeng. Te dongah cet laeh, ca lamtah o laeh,” a ti nah.
42 Bẹ́ẹ̀ ni Ahabu gòkè lọ láti jẹ àti láti mu. Ṣùgbọ́n Elijah gun orí òkè Karmeli lọ ó sì tẹríba, ó sì fi ojú rẹ̀ sí agbede-méjì eékún rẹ̀.
Te dongah Ahab te caak ham neh ok hamla cet. Tedae Elijah tah Karmel som la luei. Te phoeiah diklai la kuisu uh tih a maelhmai te a khuklu neh a khuklu laklo ah a khueh.
43 Ó sì wí fún ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé, “Lọ, kí o sì wo ìhà Òkun, òun sì gòkè lọ, ó sì wò.” Ó sì wí pé, “Kò sí nǹkan níbẹ̀.” Ó sì wí pé, “Tún lọ nígbà méje.”
Te phoeiah amah kah a tueihyoeih te, “Cet laeh lamtah tuipuei longpuei ke paelki,” a ti nah. Cet tih a paelki phoeiah, “Pakhat khaw om pawh,” a ti nah dongah voei rhih hil, “Mael dae,” a ti nah.
44 Nígbà keje, ìránṣẹ́ náà sì wí pé, “Àwọsánmọ̀ kékeré kan dìde láti inú Òkun, gẹ́gẹ́ bí ọwọ́ ènìyàn.” Elijah sì wí pé, “Lọ, kí o sọ fún Ahabu pé, ‘Di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ, kí o sì sọ̀kalẹ̀ lọ, kí òjò ó má ba à dá ọ dúró.’”
A voei rhih dongla a pha vaengah tah, “Khomai ca, tuipuei lamloh hlang kut bangla ha luei ke,” a ti nah. Te dongah, “Cet lamtah Ahab te, 'Hlah uh lamtah suntla laeh. Te daengah ni nang te khonal loh n'khaih pawt eh?,” ti nah,’ a ti nah.
45 Ó sì ṣe, nígbà díẹ̀ sí i, ọ̀run sì ṣú fún àwọsánmọ̀, ìjì sì dìde, òjò púpọ̀ sì rọ̀, Ahabu sì gun kẹ̀kẹ́ lọ sí Jesreeli.
Rhaih, rhaih a om phoeiah tah vaan ah khomai hmuep tih khohli neh khonal tlanthim ha pawk. Ahab khaw a ngol neh Jezreel la cet.
46 Agbára Olúwa sì ń bẹ lára Elijah; ó sì di àmùrè ẹ̀gbẹ́ rẹ, ó sì sáré níwájú Ahabu títí dé Jesreeli.
BOEIPA kut te Elijah soah a om dongah a cinghen te a yen tih, nang, Jezreel la aka pawk ham Ahab hmai ah yong coeng.

< 1 Kings 18 >