< 1 Kings 16 >

1 Ó sì ṣe, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jehu ọmọ Hanani wá sí Baaṣa pé,
Hina Gode da balofede dunu Yihiu (Hanainai egefe) ema e da Ba: iasiama amane sia: ma: ne sia: si,
2 “Èmi ti gbé ọ ga láti inú erùpẹ̀ wá, mo sì fi ọ́ ṣe olórí Israẹli ènìyàn mi, ṣùgbọ́n ìwọ sì rìn ní ọ̀nà Jeroboamu, ó sì mú kí Israẹli ènìyàn mi dẹ́ṣẹ̀, láti mú mi bínú nípa ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
“Di da dunu hamedei agoai ba: i. Be Na da di Na fi Isala: ili ouligima: ne ilegei. Be wali di da Yelouboua: me ea hamoi defele, Na fi wadela: le hamoma: ne oule asi dagoi. Ilia da wadela: le hamobeba: le, Na ougi hou da heda: sa.
3 Nítorí náà, èmi yóò mú Baaṣa àti ilé rẹ̀ kúrò, èmi yóò sì ṣe ilé rẹ̀ bí ilé Jeroboamu ọmọ Nebati.
Amaiba: le, Na da Yelouboua: me ea sosogo fi amo wadela: lesi dagoi, amo defele Na da dia sosogo fi wadela: lesimu.
4 Àwọn ajá yóò jẹ ẹni Baaṣa tí ó bá kú ní ìlú, ẹyẹ ojú ọ̀run yóò sì jẹ àwọn tí ó kú ní oko.”
Dia sosogo fi afae da moilai ganodini bogosea da wa: mega mai dagoi ba: mu. Amola sogebi genebogelaga bogosea, buhibaga na dagoi ba: mu.”
5 Àti ìyókù ìṣe Baaṣa, ohun tí ó ṣe àti agbára rẹ̀, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli?
Ba: iasia ea hamonanu huluane, amola ea gesa: i hamosu da “Isala: ili hina bagade ilia Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
6 Baaṣa sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín ní Tirsa. Ela ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Ba: iasia da bogole, Desa moilai bai bagadega uli dogone sali. Egefe Ila da eda bagia, hina bagade hamoi.
7 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì wá nípa ọwọ́ Jehu wòlíì ọmọ Hanani pẹ̀lú sí Baaṣa àti ilé rẹ̀, nítorí gbogbo búburú tí ó ti ṣe níwájú Olúwa, ní mímú un bínú nípa ohun tó ti ṣe àti wíwà bí ilé Jeroboamu, àti nítorí tí ó pa á run pẹ̀lú.
Hina Gode Ea sia: sia: si, amo E da balofede Yihiu ea lafidili Ba: iasia amola ea sosogo fi ilima sia: i, bai Ba: iasia da Hina Godema wadela: le bagade hamobeba: le, agoane sia: i. E da hina bagade Yelouboua: me musa: hamosu defele wadela: le bagade hamobeba: le, Hina Gode da ema ougi galu. Be amo fawane hame. E amolawane Yelouboua: me ea sosogo fi huluane medole legeiba: le, Hina Gode da ougi ba: i.
8 Ní ọdún kẹrìndínlọ́gbọ̀n Asa ọba Juda, Ela ọmọ Baaṣa bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba ní Israẹli, ó sì jẹ ọba ní Tirsa ní ọdún méjì.
Yuda hina bagade A: isa da Yuda fi ode 26 agoane ouligilalu, Ila (Ba: iasia egefe) da Isala: ili ilia hina bagade hamoi. E da Desa moilaiga esala, ode aduna Isala: ili fi ouligilalu.
9 Simri, ọ̀kan nínú àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, olórí ìdajì kẹ̀kẹ́ rẹ̀, dìtẹ̀ sí i. Ela sì wà ní Tirsa nígbà náà, ó sì mu àmupara ní ilé Arsa, ìríjú ilé rẹ̀ ni Tirsa.
Similai da hina bagade Ila ea ‘sa: liode’ wa: i mogili, la: idi ouligisu dunu ba: i. E da Ila medole legema: ne, sadoga sia: dalu ilegei. Eso afaega Desa moilaiga, Ila da dunu ea dio amo Asa (e da hina bagade diasu ouligisu) amo ea diasuga adini maiga feloai.
10 Simri sì wọlé, ó sì kọlù ú, ó sì pa á ní ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n Asa, ọba Juda, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Similai da amo diasu golili sa: ili, Ila medole legei. Amalalu, e da Ila bagia Isala: ili hina bagade hamoi. Amo hou da Yuda hina bagade A: isa ea Yuda fi ode 27 ouligilalu, ba: i.
11 Bí ó sì ti bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba, bí ó sì ti jókòó lórí ìtẹ́, ó lu gbogbo ilé Baaṣa pa, kò ku ọkùnrin kan sílẹ̀, bóyá ìbátan tàbí ọ̀rẹ́.
Similai da hina bagade hamonoba, e da Ba: iasia ea sosogo fi amo ganodini dunumusu huluane medole lelegei. Amola Ba: iasia sosogo fi ilia sasamalali huluane medole legei.
12 Bẹ́ẹ̀ ni Simri pa gbogbo ilé Baaṣa run, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ sí Baaṣa nípa ọwọ́ Jehu wòlíì:
Amaiba: le Hina Gode da balofede dunu Yihiu ea lafidili Ba: iasiama sia: i amo defele, Similai da Ba: iasia ea sosogo fi huluane medole legei.
13 nítorí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí Baaṣa àti Ela ọmọ rẹ̀ ti ṣẹ̀ àti tí wọ́n ti mú Israẹli ṣẹ̀, tí wọ́n fi mú Olúwa Ọlọ́run Israẹli bínú, wọ́n mú u bínú nípa òrìṣà asán wọn.
Bai ilia da wadela: i ogogosu ‘gode’ma nodone sia: ne gadobeba: le, amola ilia da Isala: ili fi dunu amo wadela: i hou hamoma: ne oule asi. Ba: iasia amola egefe Ila, elea da Isala: ili ilia Hina Gode Ea ougima: ne, agoane hamoi.
14 Ìyókù ìṣe Ela àti gbogbo ohun tí ó ṣe, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli?
Liligi huluane Ila ea hamoi da “Isala: ili hina bagade ilia Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
15 Ní ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n Asa ọba Juda, ni Simri jẹ ọba ọjọ́ méje ní Tirsa. Àwọn ọmọ-ogun sì dó ti Gibetoni, ìlú àwọn ará Filistini.
Yuda hina bagade A: isa da ode 27 agoane Yuda fi ouligilalu, Similai da Desa moilaiga esala, Isala: ili fi eso fesuale fawane ouligi. Isala: ili dadi gagui wa: i da Gibidone moilai bai bagade, Filisidini soge ganodini, amo doagala: lebe ba: i.
16 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli tí ó dó tì gbọ́ wí pé Simri ti dìtẹ̀ sí ọba, ó sì ti pa á, wọ́n kéde Omri, olórí ogun, bí ọba lórí Israẹli ní ọjọ́ náà ní ibùdó.
Ilia da Similai da Isala: ili hina bagade medoma: ne sadoga sia: sa: ili, e medole legei dagoi, amo nababeba: le, ilia esalusuadafa amoga ilia dadi gagui wa: i ouligisu Omelima Isala: ili hina bagade hamoma: ne ilegei.
17 Nígbà náà ni Omri àti gbogbo Israẹli pẹ̀lú rẹ̀ kúrò ní Gibetoni, wọ́n sì dó ti Tirsa.
Omeli amola ea dadi gagui wa: i da Gibidone doagala: lalu yolesili, asili, Desa moilai doagala: i.
18 Nígbà tí Simri sì ri pé a ti gba ìlú, ó sì wọ inú ààfin ilé ọba lọ, ó sì tẹ iná bọ ilé ọba lórí ara rẹ̀, ó sì kú,
Similai da ba: loba, moilai mogi na: iyado hasalabeba: le, e da hina bagade diasu ganodini gagili sali sesei amogano golili sa: ili, hina bagade ea diasu ulagisilalu, amo lalu gona: su da: iya hina: bogola sa: i.
19 nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ tí ó ti ṣẹ̀, ní ṣíṣe búburú níwájú Olúwa àti ní rírìn ní ọ̀nà Jeroboamu àti nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ tí ó ti ṣe àti tí ó ti mú Israẹli ṣẹ̀.
E da Hina Godema bagadewane wadela: le hamoi. Amaiba: le, e da bogoi dagoi. Ea da Yelouboua: me defele, wadela: le hamoi amola Isala: ili fi wadela: le hamoma: ne, oule asi. Amaiba: le, Hina Gode da ema hahawane hame ba: i.
20 Ní ti ìyókù ìṣe Simri, àti ọ̀tẹ̀ rẹ̀ tí ó dì, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli?
Similai ea hou huluane amola e da Ila medoma: ne sadoga ilegele, Ila medole legei, amo da “Isala: ili hina bagade ilia Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
21 Nígbà náà ní àwọn ènìyàn Israẹli dá sí méjì; apá kan wọn ń tọ Tibni ọmọ Ginati lẹ́yìn, láti fi í jẹ ọba, apá kan tókù sì ń tọ Omri lẹ́yìn.
Isala: ili dunu fi da dogoa mogi. Oda ilia da Dibini (Gina: de egefe) amo hina bagade hamoma: ne dawa: i, amola oda ilia da Omeli hanai.
22 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn tí ń tọ Omri lẹ́yìn borí àwọn tí ń tọ Tibni ọmọ Ginati lẹ́yìn. Bẹ́ẹ̀ ni Tibni kú, Omri sì jẹ ọba.
Amo sia: dalu fa: no, Omelima hanai dunu ilia baligi. Dibini da bogobeba: le, Omeli da hina bagade dunu hamoi.
23 Ní ọdún kọkànlélọ́gbọ̀n Asa ọba Juda, Omri bẹ̀rẹ̀ sí ń jẹ ọba lórí Israẹli, ó sì jẹ ọba ní ọdún méjìlá, ọdún mẹ́fà ní Tirsa.
Amaiba: le, Yuda fi ilia hina bagade A: isa da Yuda fi ode31 ouligilalu, Omeli da Isala: ili hina bagade hamoi. E da ode fagoyale ouligilalu. Bisili ode gafeyale agoanega, e da Desa moilaiga esala, ouligilalu.
24 Ó sì ra òkè Samaria lọ́wọ́ Ṣemeri ní tálẹ́ǹtì méjì fàdákà, ó sì kọ́ ìlú sórí rẹ̀, ó sì pe ìlú náà ní Samaria, nípa orúkọ Ṣemeri, orúkọ ẹni tí ó kọ́kọ́ ni òkè náà.
Amalalu, e da Samelia agolo amo silifa fage 6,000 agoane amoga dunu ea dio amo Simia ema bidi lai. Omeli da amo agolo gagili salalu, amogai moilai gaheabolo gagui. E da musa: agolo gagui dunu Simia ea dio dabua, amoma Samelia dio asuli.
25 Ṣùgbọ́n Omri sì ṣe búburú níwájú Olúwa, Ó sì ṣe búburú ju gbogbo àwọn tí ó wà ṣáájú rẹ̀ lọ.
Omeli da Hina Godema wadela: le hamoi da musa: Isala: ili hina bagade dunu huluane ilia wadela: i hou baligi.
26 Ó rìn ní gbogbo ọ̀nà Jeroboamu ọmọ Nebati àti nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èyí tí ó ti mú Israẹli ṣẹ̀, láti fi ohun asán wọn mú Olúwa, Ọlọ́run Israẹli bínú.
E da Yelouboua: me ea hou defele, Isala: ili Hina Gode ougima: ne, wadela: le bagade hamoi, amola Isala: ili fi wadela: le hamoma: ne oule asi.
27 Ìyókù ìṣe àti ohun tí Omri ṣe, àti agbára rẹ tí ó fihàn, a kò ha kọ, wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli?
Hou huluane Omeli da hamonanusu, amola ea hamoi liligi huluane da “Isala: ili hina bagade ilia Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
28 Omri sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sì sin ín ní Samaria. Ahabu ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Omeli da bogole, Samelia soge ganodini uli dogone sali. Amola egefe A: iha: be da eda bagia hina bagade hamoi.
29 Ní ọdún kejìdínlógójì Asa ọba Juda, Ahabu ọmọ Omri jẹ ọba ní Israẹli, o si jẹ ọba lórí Israẹli ní Samaria ní ọdún méjìlélógún.
Yuda hina bagade A: isa da Yuda soge ode 38 agoane ouligilalu, A:iha: be (Omeli egefe) da Isala: ili hina bagade hamoi. E da Samelia soge amo ganodini ode 22 agoane, Isala: ili ouligilalu.
30 Ahabu ọmọ Omri sì ṣe búburú ní ojú Olúwa ju gbogbo àwọn tí ó wà ṣáájú rẹ̀ lọ.
E da Hina Godema wadela: le hamoi, amo da musa: Isala: ili hina bagade ilia wadela: i hou huluane baligi dagoi.
31 Ó sì ṣe bí ẹni pé ó ṣe ohun kékeré fún un láti máa rìn nínú ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, ó sì mú Jesebeli, ọmọbìnrin Etibaali, ọba àwọn ará Sidoni ní aya, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ń sin Baali, ó sì bọ ọ́.
E da Yelouboua: me ea wadela: i hou hamoi defele hamoi, amola amo baligi. E da baligiliwane wadela: i hamonanu asili, Yesebele (Saidone hina bagade Edeba: ile ea idiwi) amo lale, Ba: ile ogogosu ‘gode’ma nodone sia: ne gadosu.
32 Ó sì tẹ́ pẹpẹ kan fún Baali nínú ilé Baali tí ó kọ́ sí Samaria.
E da Samelia soge ganodini, Ba: ilema nodone sia: ne gadoma: ne, debolo diasu gaguli, Ba: ilema oloda hamone, amo debolo diasu ganodini sali.
33 Ahabu sì túnṣe ère òrìṣà Aṣerah, ó sì ṣe púpọ̀ láti mú Olúwa Ọlọ́run Israẹli bínú ju èyí tí gbogbo ọba Israẹli tí ó ti wà ṣáájú rẹ̀ ti ṣe lọ.
Amola e da ogogole uda ‘gode’ Asila agoaila hahamone, bugisi. E da Isala: ili Hina Gode Ea ougima: ne wadela: le hamoi, da musa: Isala: ili hina bagade Gode Ea ougima: ne wadela: i hou hamoi amo baligidafa.
34 Ní ìgbà ayé Ahabu, Hieli ará Beteli kọ́ Jeriko. Ó fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lé ilẹ̀ ní Abiramu, àkọ́bí rẹ, ó sì gbé àwọn ìlẹ̀kùn ibodè rẹ̀ kọ́ ní Segubu àbíkẹ́yìn rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó ti ipa Joṣua ọmọ Nuni sọ.
Ea ouligilaloba, Bedele dunu Haiyele da Yeligou moilai bai bagade bu gagui. Hina Gode da Yosiua (Nane egefe) amo ea lafidili sia: i defele, Haiyele da Yeligou ea bai fa: loba, ea magobo mano Abaila: me fisi. Amola e da moilai gagoi logo ga: su hamonoba, ea ufi mano Sigabe fisi dagoi ba: i.

< 1 Kings 16 >