< 1 Corinthians 8 >

1 Ní ìsinsin yìí, nípa tí oúnjẹ ti a fi rú ẹbọ sí òrìṣà, a mọ̀ pé gbogbo wa ni a ní ìmọ̀. Imọ̀ a máa fẹ́ mu ní gbéraga, ṣùgbọ́n ìfẹ́ ní gbé ni ró.
دیوَپْرَسادے سَرْوّیشامْ اَسْماکَں جْنانَماسْتے تَدْوَیَں وِدْمَح۔ تَتھاپِ جْنانَں گَرْوَّں جَنَیَتِ کِنْتُ پْریمَتو نِشْٹھا جایَتے۔
2 Bí ẹnikẹ́ni bá ró pé òun mọ ohun kan, kò tí ì mọ̀ bí ó ti yẹ kí ó mọ̀.
اَتَح کَشْچَنَ یَدِ مَنْیَتے مَمَ جْنانَماسْتَ اِتِ تَرْہِ تینَ یادرِشَں جْنانَں چیشْٹِتَوْیَں تادرِشَں کِمَپِ جْنانَمَدْیاپِ نَ لَبْدھَں۔
3 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó fẹ́ràn Ọlọ́run nítòótọ́, òun ni ẹni tí Ọlọ́run mọ.
کِنْتُ یَ اِیشْوَرے پْرِییَتے سَ اِیشْوَریناپِ جْنایَتے۔
4 Nítorí náà, ǹjẹ́ ó yẹ kí a jẹ àwọn oúnjẹ ti a fi rú ẹbọ sí àwọn òrìṣà bí? Láìṣe àní àní, gbogbo wá mọ̀ pé àwọn ère òrìṣà kì í ṣe Ọlọ́run rárá, ohun asán ni wọn ni ayé. A sì mọ̀ dájúdájú pé Ọlọ́run kan ṣoṣo ní ń bẹ, kò sì ṣí ọlọ́run mìíràn bí kò ṣe ọ̀kan ṣoṣo.
دیوَتابَلِپْرَسادَبھَکْشَنے وَیَمِدَں وِدْمو یَتْ جَگَنْمَدھْیے کوپِ دیوو نَ وِدْیَتے، ایکَشْچیشْوَرو دْوِتِییو ناسْتِیتِ۔
5 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, à ní ọ̀pọ̀ ọlọ́run kéékèèké mìíràn ní ọ̀run àti ní ayé (gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ “ọlọ́run” ṣe wa náà ní ọ̀pọ̀ “olúwa” wa).
سْوَرْگے پرِتھِوْیاں وا یَدْیَپِ کیشُچِدْ اِیشْوَرَ اِتِ ناماروپْیَتے تادرِشاشْچَ بَہَوَ اِیشْوَرا بَہَوَشْچَ پْرَبھَوو وِدْیَنْتی
6 Ṣùgbọ́n fún àwa Ọlọ́run kan ní ó wa, Baba, lọ́wọ́ ẹni tí ó dá ohun gbogbo, àti ti ẹni tí gbogbo wa í ṣe, àti Olúwa kan ṣoṣo Jesu Kristi, nípasẹ̀ ẹni tí ohun gbogbo wà, àti àwa nípasẹ̀ rẹ̀.
تَتھاپْیَسْماکَمَدْوِتِییَ اِیشْوَرَح سَ پِتا یَسْماتْ سَرْوّیشاں یَدَرْتھَنْچاسْماکَں سرِشْٹِ رْجاتا، اَسْماکَنْچادْوِتِییَح پْرَبھُح سَ یِیشُح کھْرِیشْٹو یینَ سَرْوَّوَسْتُوناں ییناسْماکَمَپِ سرِشْٹِح کرِتا۔
7 Ṣùgbọ́n kì í ṣe gbogbo ènìyàn lo mọ èyí. Ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn tí ó ti ń bọ̀rìṣà lọ́jọ́ tó ti pẹ́ títí di ìsinsin yìí jẹ ẹ́ bí ohun tí a fi rú ẹbọ sí òrìṣà, àti ẹ̀rí ọkàn wọn tí ó ṣe àìlera sì di aláìmọ́.
اَدھِکَنْتُ جْنانَں سَرْوّیشاں ناسْتِ یَتَح کیچِدَدْیاپِ دیوَتاں سَمَّنْیَ دیوَپْرَسادَمِوَ تَدْ بھَکْشْیَں بھُنْجَتے تینَ دُرْبَّلَتَیا تیشاں سْوانْتانِ مَلِیمَسانِ بھَوَنْتِ۔
8 Ṣùgbọ́n oúnjẹ kò mú wa súnmọ́ Ọlọ́run, nítorí pé kì í ṣe bí àwa bá jẹun ni àwa burú jùlọ tàbí nígbà tí a kò jẹ ni àwa dára jùlọ.
کِنْتُ بھَکْشْیَدْرَوْیادْ وَیَمْ اِیشْوَرینَ گْراہْیا بھَوامَسْتَنَّہِ یَتو بھُنْکْتْوا وَیَمُتْکرِشْٹا نَ بھَوامَسْتَدْوَدَبھُنْکْتْواپْیَپَکرِشْٹا نَ بھَوامَح۔
9 Ṣùgbọ́n ẹ máa kíyèsi ara gidigidi nípa ìlò òmìnira yín kí ẹ má ba à mú kí àwọn arákùnrin mìíràn tí í ṣe onígbàgbọ́, tí ọkàn wọn ṣe aláìlera, ṣubú sínú ẹ̀ṣẹ̀.
اَتو یُشْماکَں یا کْشَمَتا سا دُرْبَّلانامْ اُنْماتھَسْوَرُوپا یَنَّ بھَویتْ تَدَرْتھَں ساوَدھانا بھَوَتَ۔
10 Ẹ kíyèsára, nítorí bi ẹnìkan ba rí i ti ìwọ ti o ni ìmọ̀ bá jókòó ti oúnjẹ ní ilé òrìṣà, ǹjẹ́ òun kò ha ni mú ọkàn le, bi ẹ̀rí ọkàn rẹ̀ bá ṣe aláìlera, láti jẹ oúnjẹ tí a fi rú ẹbọ sí òrìṣà?
یَتو جْنانَوِشِشْٹَسْتْوَں یَدِ دیوالَیے اُپَوِشْٹَح کیناپِ درِشْیَسے تَرْہِ تَسْیَ دُرْبَّلَسْیَ مَنَسِ کِں پْرَسادَبھَکْشَنَ اُتْساہو نَ جَنِشْیَتے؟
11 Nítorí náà, nípa ìmọ̀ rẹ ni arákùnrin aláìlera náà yóò ṣe ṣègbé, arákùnrin ẹni tí Kristi kú fún.
تَتھا سَتِ یَسْیَ کرِتے کھْرِیشْٹو مَمارَ تَوَ سَ دُرْبَّلو بھْراتا تَوَ جْناناتْ کِں نَ وِنَںکْشْیَتِ؟
12 Bí ẹ bá dẹ́ṣẹ̀ sí arákùnrin rẹ̀ tí ẹ sì ń pa ọkàn àìlera wọn lára, ẹ̀yìn ǹ dẹ́ṣẹ̀ sí Kristi jùlọ.
اِتْیَنینَ پْرَکارینَ بھْراترِناں وِرُدّھَمْ اَپَرادھْیَدْبھِسْتیشاں دُرْبَّلانِ مَناںسِ وْیاگھاتَیَدْبھِشْچَ یُشْمابھِح کھْرِیشْٹَسْیَ وَیپَرِیتْییناپَرادھْیَتے۔
13 Nítorí nà án, bí oúnjẹ bá mú arákùnrin mi kọsẹ̀, èmi kì yóò sì jẹ ẹran mọ́ títí láé, kí èmi má ba à mú arákùnrin mi kọsẹ̀. (aiōn g165)
اَتو ہیتوح پِشِتاشَنَں یَدِ مَمَ بھْراتُ رْوِگھْنَسْوَرُوپَں بھَویتْ تَرْہْیَہَں یَتْ سْوَبھْراتُ رْوِگھْنَجَنَکو نَ بھَوییَں تَدَرْتھَں یاوَجِّیوَنَں پِشِتَں نَ بھوکْشْیے۔ (aiōn g165)

< 1 Corinthians 8 >